< Genesis 24 >
1 Abrahamu sì ti di arúgbó ní àkókò yìí, Olúwa sì ti bùkún fún un ni gbogbo ọ̀nà,
A: ibalaha: me da ode bagohame lai dagoiba: le, da: idafa ba: su. Be Hina Gode da ea hou huluane amo ganodini hahawane dogolegelewane fidilalusu.
2 Abrahamu wí fún olórí àwọn ìránṣẹ́ ilẹ̀ rẹ̀, tí ó jẹ́ alábojútó ohun gbogbo tí ó ní pé, “Fi ọwọ́ rẹ sí abẹ́ itan mi.
E da ea da: i hamoi hawa: hamosu dunu (amo da ea liligi huluane ouligisu) ema amane sia: i, “Dia lobo amo na masele hagudu ligisili, dafawane ilegele sia: ma!
3 Èmi yóò mú ọ búra lórúkọ Olúwa Ọlọ́run ọ̀run àti ayé, pé, ìwọ kì yóò fẹ́ aya fún ọmọ mi nínú àwọn ọmọbìnrin ará Kenaani, láàrín àwọn ẹni tí èmi ń gbé.
Na da agoane hanai galebe. Di da Hina Gode amo da Hebene Hina amola osobo bagade Hina, amo Ea Dioba: le gasa bagade sia: ma. Di da Ga: ina: ne fi (amo ganodini na da wali esala) amoga nagofe uda lama: ne mae ilegema.
4 Ṣùgbọ́n, ìwọ yóò lọ sí orílẹ̀-èdè mi, láàrín àwọn ará mi láti fẹ́ aya fún Isaaki, ọmọ mi.”
Be na musa: fi sogega asili, na fidafa amo ganodini hogolalu, nagofe Aisage uda lama: ne, a:fini sia: sima!”
5 Ìránṣẹ́ náà bi í wí pé, “Ǹjẹ́ bí ọmọbìnrin náà bá kọ̀ láti bá mi wá sí ilẹ̀ yìí ń kọ́? Ǹjẹ́ mo lè mú ọmọ rẹ padà lọ sí orílẹ̀-èdè níbi tí ìwọ ti wá?”
Ea hawa: hamosu dunu da bu adole ba: i, “Be amo uda da na amola bu sigi misunu hihi galea, na da adi hamoma: bela: ? Na da dia mano amo dia musa: sogega bu oule masa: bela: ?”
6 Abrahamu sì wí fún un pé, “Rí i dájú pé ìwọ kò mú ọmọ mi padà lọ sí ibẹ̀.”
Be A: ibalaha: me da amane sia: i, “Hame mabu! Di amoga nagofe bu mae oule masa!
7 “Olúwa, Ọlọ́run ọ̀run tí ó mú mi jáde láti ilẹ̀ baba mi àti ní ilẹ̀ tí a bí mi, tí ó bá mi sọ̀rọ̀ tí ó sì búra fún mi pé, ‘Irú-ọmọ rẹ ni n ó fi ilẹ̀ yìí fún,’ yóò rán angẹli rẹ̀ ṣáájú rẹ, kí ìwọ kí ó lè rí aya fẹ́ wá fún ọmọ mi láti ibẹ̀.
Hina Gode amo Hebene amoga Hina esala, e da na ada amo ea diasu amola na soge yolesili ga masa: ne sia: ne, nama gasawane amane sia: i, ‘Na da dafawane ilegele sia: sa! Na da amo soge (Ga: ina: ne) digaga fi ilima imunu.’ Amo Gode da Ea a: igele dunu dima bisimusa: asunasimu. Bai di da amo sogega nagofema ima: ne uda lamu defele ba: mu.
8 Bí obìnrin náà kò bá fẹ́ tẹ̀lé ọ wá, nígbà náà ni a tú ọ sílẹ̀ kúrò nínú ìbúra yìí, ṣùgbọ́n pàtàkì ni pé ìwọ kò gbọdọ̀ mú ọmọ mi padà lọ sí ibẹ̀.”
Be uda da di guiguda: oule misunu amo higasea, defea, dia da nama Gode Ea Dioba: le sia: i, amo na da bu hame dawa: mu. Be na mano maedafa bu oule masa.”
9 Ìránṣẹ́ náà sì fi ọwọ́ rẹ̀ sí abẹ́ itan Abrahamu olúwa rẹ̀, ó sì búra fún nítorí ọ̀rọ̀ náà.
Amaiba: le, hawa: hamosu dunu da ea hina A: ibalaha: me amo ea masele hagudu ea lobo ligisili, Gode Ea Dioba: le gasa bagade amo liligi hamoma: ne ilegele sia: i.
10 Ìránṣẹ́ náà sì mú ìbákasẹ mẹ́wàá, pẹ̀lú onírúurú ohun dáradára láti ọ̀dọ̀ olúwa rẹ̀, ó sì dìde ó sì lọ sí Aramu-Naharaimu, sí ìlú Nahori,
Amalalu, hawa: hamosu dunu da ea hina ga: mele nabuane gala amo lale, ea hina ea liligi noga: iwane aguni, gadili asi. E da Alame Nahalaime soge amoga doaga: musa: asili, Na: iho moilaiga doaga: i.
11 ó sì mú àwọn ìbákasẹ náà kúnlẹ̀ nítòsí kànga lẹ́yìn ìlú, ó ti ń di ọwọ́ ìrọ̀lẹ́ ní àkókò tí àwọn obìnrin máa ń lọ pọn omi.
Hano uli dogoi moilai gadili sogebi gala amoga doaga: loba, ea sia: beba: le, ga: mele da muguni bugi. Eso dabe da gadenenewane ba: i. Amoha, uda ilia hou da hano uli dogoi amoga hano dima: ne hiougimusa: ahoasu.
12 Ó sì gbàdúrà wí pé, “Olúwa, Ọlọ́run Abrahamu olúwa à mi; jẹ́ kí n ṣe àṣeyọrí lónìí, sì fi àánú hàn fún Abrahamu olúwa mi.
Amalalu, e da Godema amane sia: ne gadoi, “Hina Godedafa! Na hina A: ibalaha: me amo ea Gode! Na hawa: hamosu hahawane dagoma: ne Di fidima, amola na hina A: ibalaha: mema dia asigi hou olelema.
13 Kíyèsi i, mo dúró ní ẹ̀bá kànga omi yìí, àwọn ọmọbìnrin ìlú yìí sì ń jáde wá pọn omi.
Ba: ma! Na da amo hano nasu ulidou gadenene lela amola amo moilai dunu ilia uda mano da hano dimusa: manebe.
14 Jẹ́ kí ó ṣe pé nígbà tí mo bá wí fún ọ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin pe, ‘Jọ̀wọ́ sọ ládugbó rẹ kalẹ̀, kí n le mu omi,’ tí ó bá sì wí pé, ‘Mu ún, èmi ó sì fún àwọn ìbákasẹ rẹ náà mu pẹ̀lú,’ jẹ́ kí ó ṣe èyí tí o yàn fún ìránṣẹ́ rẹ Isaaki. Nípa èyí ni n ó fi mọ̀ pé o ti fi àánú hàn fún olúwa mi.”
Na da agoane hanai gala. Na da a: finima ‘Dia hano disu amo na hano moma: ne ligisima.’ sia: sea, amola e da amane sia: sea, ‘Defea! Moma! Amola na da dia ga: mele moma: ne hano dili imunu.’ Amo hou ba: sea, Hina Gode da amo a: fini na hina ea mano lama: ne ilegei dagoi na da dawa: mu. Amola Di da na hinama asigi hou olelei dagoi, amo na da dawa: mu.”
15 Kí o tó di pé, ó parí àdúrà, Rebeka dé pẹ̀lú ìkòkò omi rẹ̀ ní èjìká rẹ̀. Ọmọ Betueli ni. Betueli yìí ni Milka bí fún Nahori arákùnrin Abrahamu.
E da sia: ne gadolaloba, Lebega da misini, ea hano ganagu amo gisa manebe ba: i. Lebega da Bediuele ea idiwi, amola Bediuele ea: me da A: ibalaha: me ola Na: iho amo idua, ea dio amo Miliga.
16 Ọmọbìnrin náà rẹwà, wúńdíá ni, kò sì tí ì mọ ọkùnrin, ó lọ sí ibi ìsun omi náà, ó sì pọn omi sínú ìkòkò omi, ó sì gbé e, ó ń gòkè bọ̀ kúrò níbi omi.
Lebega ea ba: su da noga: idafa ba: i. E da a: fini galu. Dunu afae da e amola gilisili hame golai. E da hano nasua asili, ea ganagu nabalesili, bu heda: i.
17 Ìránṣẹ́ náà súré lọ pàdé rẹ̀, ó sì wí fun un pé, “Jọ̀wọ́ fún mi ni omi díẹ̀ nínú ìkòkò omi rẹ.”
A: ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu da hedolo ema misini, amane sia: i, “Na da dia ganagu amoga hano fonobahadi manu da defeala: ?”
18 Òun náà dáhùn pé, “Mu, olúwa mi,” ó sì yára sọ ìkòkò omi náà ka ọwọ́ rẹ̀, ó sì fún un mu.
A: fini da amane sia: i, “Defea! Ada! Di moma!” Amalalu, e da ganagu ligisili, ea lobo ganodini gaguli, ema hano i.
19 Lẹ́yìn tí ó ti fún un ni omi mu tán, ó wí pé, “Èmi ó bu omi fún àwọn ìbákasẹ rẹ pẹ̀lú títí wọn yóò fi mu àmutẹ́rùn.”
Hano dili ianu, e amane sia: i, “Na da dia ga: mele moma: ne amola hano dili imunu. Ilia sadi dagoiba: le fawane yolesimu.”
20 Ó sì yára da omi inú ìkòkò omi rẹ̀ sínú ìbùmu, ó sáré padà lọ sí ibi omi láti pọn sí i wá fún àwọn ìbákasẹ, títí tí ó fi pọn fún gbogbo wọn.
Amaiba: le, e da ea ganagu amo hano ga: mele hano nasu ganodini sogasalili, hano uli dogoi amoga hehenane, hano eno dili, ga: mele sadi dagoiba: le yolesi.
21 Láìsọ ọ̀rọ̀ kan, ìránṣẹ́ yìí ń wo ọmọbìnrin náà fínní fínní láti mọ̀ bóyá Olúwa ti ṣe ìrìnàjò òun ní rere tàbí bẹ́ẹ̀ kọ́.
A: ibalaha: me hawa: hamosu dunu da ouiya: le esalu. Gode da ea ahoabe bai amo noga: le fidi amo dawa: musa: gini, E da amo a: fini ea hou ha: giwane ba: lalu.
22 Lẹ́yìn tí àwọn ìbákasẹ náà ti mu omi tán, ni ọkùnrin náà mú òrùka wúrà ààbọ̀ ìwọ̀n ṣékélì àti júfù méjì fún ọwọ́ rẹ̀, tí ìwọ̀n ṣékélì wúrà mẹ́wàá.
Ga: mele da hano na dagoloba, A:ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu da mi bione gala: su gouliga hamoi amo Lebega ea mi ga: i, amola gouli lobofasele fei. Mi bione gala: su ea dioi defei da gala: me biyale agoane amola fesuale fesu da gala: me 100agoane.
23 Lẹ́yìn náà, ó béèrè pé, “Ọmọ ta ni ìwọ í ṣe? Jọ̀wọ́ wí fún mi, ǹjẹ́ ààyè wà ní ilé baba rẹ láti wọ̀ sí ní alẹ́ yìí?”
Amalalu, A:ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu da ema amane adole ba: i, “Di da nowa ea manola: ? Nama adoma! Dia ada diasu amo ganodini nini golama: ne sogebi ganabela: ?
24 Ó dáhùn pé, “Betueli ọmọ tí Milka bí fún Nahori ni baba mi.”
A: fini da bu adole i, “Na da Bediuele ea mano. Bediuele da Na: iho amola idua Miliga ela mano.”
25 Ó sì fi kún un pé, “Àwa ní koríko àti ṣakaṣaka tó pẹ̀lú, àti ààyè láti wọ̀ sí.”
Amalalu, e bu adole i, “Ninia diasua da gisi ha: i manu bagohame gala. Amola dilia gasia golama: ne, sogebi bagade gala.
26 Nígbà náà ni ọkùnrin náà tẹríba, ó sì sin Olúwa,
Amalalu, hawa: hamosu dunu e da beguduli, Hina Godema nodone sia: ne gadoi.
27 wí pe, “Olùbùkún ni fún Olúwa, Ọlọ́run Abrahamu olúwa mi ti kò jẹ́ kí àánú àti òtítọ́ rẹ̀ kí ó yẹ̀ lọ́dọ̀ olúwa mi. Ní ti èmi Olúwa ti darí ìrìnàjò mi sí ilé ìbátan olúwa mi.”
E amane sia: i, “Na da Hina Gode dio nodone gaguia gadosa. Na hina A: ibalaha: me, amo ea Gode da ema asigi hou hame yolesi. Be Hina Gode da na bisili asili, nama na hina ea fi dunu ilia diasu noga: le olelei.
28 Ọmọbìnrin náà sì sáré, ó sì lọ sọ ohun gbogbo wọ̀nyí fún àwọn ará ilé ìyá rẹ̀.
Lebega da hehenane, ea ame fi ilima amo hou olelei.
29 Rebeka ní arákùnrin tí ń jẹ́ Labani; Labani sì sáré lọ bá ọkùnrin náà ní etí odò.
Lebega ea ola amo ea dio La: iba: ne esalu. La: iba: ne da hehenane, hano nasu amoga doaga: musa: asi.
30 Bí ó sì ti rí òrùka imú àti ẹ̀gbà ní ọwọ́ arábìnrin rẹ̀ tí ó sì tún gbọ́ ohun tí Rebeka sọ pé ọkùnrin náà sọ fún òun, ó jáde lọ bá ọkùnrin náà, ó sì bá a, ó dúró ti ìbákasẹ wọ̀n-ọn-nì ní ẹ̀bá ìsun omi.
E da Lebega lai liligi, amo mi bione ga: i amola gouli lobofasele fei ba: i dagoi. E da Lebega ea sia: nabi dagoi. Amabeba: le, e da asili, A:ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu ea ga: mele amo hano nasu gadenene lelebe ba: i.
31 Ó wí fún ọkùnrin náà pé, “Wá, ìwọ ẹni ìbùkún Olúwa, èéṣe tí o dúró sí ìta níhìn-ín? Mo ti pèsè ààyè sílẹ̀ fún ọ àti ààyè fún àwọn ìbákasẹ rẹ.”
E amane sia: i, “Hina Gode da dima hahawane dogolegele ilegesa. Misa! Di da abuli gadili lela. Na da di golama: ne amola ga: mele golama: ne diasu hahamoi dagoi.”
32 Ọkùnrin náà sì bá Labani lọ ilé, ó sì tú ẹrù orí ìbákasẹ rẹ̀ sílẹ̀, ó sì fún wọn ni koríko àti oúnjẹ. Ó sì bu omi fún ọkùnrin náà àti àwọn arákùnrin rẹ̀ láti wẹ ẹsẹ̀ wọn.
Amaiba: le, dunu da diasuga asi. La: iba: ne da ga: mele amoga liligi lale ligisi. E da gisi amola ha: i manu ga: mele ilima gaguli misi, amola A: ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu amola ea fidisu dunu ilia emo dodofema: ne, hano dili i.
33 Wọ́n sì gbé oúnjẹ síwájú rẹ̀, ṣùgbọ́n, ó wí pé, “Èmi kò ní jẹun àyàfi bí mo bá sọ ohun tí mo ní í sọ.” Labani sì wí pé, “Kò burú, sọ ọ́.”
Amalalu, amo dunu ha: i moma: ne, ilia da ha: i manu gaguli misi. Be e amane sia: i, Na da na sia: ne iasu sia: i dagoiba: le fawane, ha: i manu. La: iba: ne da amane sia: i, “Defea! Ninima adoma!”
34 Nítorí náà, ó wí pé, “Ìránṣẹ́ Abrahamu ni èmi.
Amaiba: le, e amane sia: i, “Na da A: ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu.
35 Olúwa sì ti bùkún olúwa mi gidigidi. Ó sì ti di ọlọ́rọ̀, Ó sì ti fún un ní àgùntàn, màlúù, àti fàdákà àti wúrà, ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin àti ìbákasẹ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Hina Gode da na hina amo hahawane dogolegelewane bagade fidibiba: le, e da wali bagade gagui dunu esala. Gode da ema sibi, bulamagau, silifa, gouli, hawa: hamosu dunu, hawa: hamosu uda, ga: mele, amola dougi ema i dagoi.
36 Sara aya olúwa mi sì ti bí ọmọkùnrin kan fún un, ní ìgbà ogbó rẹ̀, olúwa mi sì ti fún ọmọ náà ní ohun gbogbo tí ó ní.
Ea uda Sela da da: i hamoi be ema dunu mano da lalelegei. Na hina da amo manoma ea gagui huluane i dagoi.
37 Olúwa mi sì ti mú mi búra wí pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ fẹ́ aya fún ọmọ mi, láàrín àwọn ọmọbìnrin Kenaani, ní ilẹ̀ ibi tí èmi ń gbé,
Na hina da logeiba: le, na da Gode Ea Dioba: le gasa bagade ilegele sia: i. Na hina da amane sia: i, “Na da Ga: ina: ne fi amo ganodini esala. Be amoga nagofe uda lama: ne, uda mae sia: sima.
38 ṣùgbọ́n lọ sí ìdílé baba mi láàrín àwọn ìbátan mi kí o sì fẹ́ aya fún ọmọ mi.’
Be na ada ea sosogo fi amola na fidafa ilima nagofe ea uda lala masa.’
39 “Mo sì bí olúwa mi léèrè pé, ‘Ǹjẹ́ bí ọmọbìnrin náà kò bá fẹ́ bá mi wá ń kọ́?’
Amalalu, na da na hinama amane adole ba: i, “Be amo uda da na amola bu sigi misunu hihi galea, na adi hamoma: bela: ?”
40 “Ó sì dáhùn wí pé, ‘Olúwa, níwájú ẹni tí èmi ń rìn yóò rán Angẹli rẹ̀ ṣáájú rẹ yóò sì jẹ́ kí o ṣe àṣeyọrí ní ìrìnàjò rẹ, kí ìwọ kí ó ba le fẹ́ aya fún ọmọ mi, láàrín àwọn ìbátan mi, àti láàrín àwọn ìdílé baba mi.
E da nama bu adole i, ‘Hina Godedafa, amo Ea sia: na eso huluane naba, E di fidima: ne Ea a: igele dunu asunasimu. Di na fidafa, amola na ada ea sosogo fi amoga uda na mano ea lama: ne sia: sima.
41 Nígbà tí ìwọ bá lọ sí ọ̀dọ̀ ìdílé baba mi (gẹ́gẹ́ bí mo tí wí), nígbà náà ni ìwọ tó bọ́ nínú ìbúra yìí.’
Dia gasa bagade sia: amo mae hamoma: ne, logo afadafa fawane gala. Di da na fi ilima asili amola ilia amo uda dima imunu higasea, defea, yolema.’
42 “Nígbà tí mo dé ibi ìsun omi lónìí, mo wí pé, ‘Olúwa Ọlọ́run Abrahamu olúwa mi, bí ìwọ bá fẹ́, jọ̀wọ́ jẹ́ kí n ṣe àṣeyọrí lórí ohun tí mo bá wá yìí.
Na da wali eso hano nasu uli dogoi amoga doaga: loba, na amane sia: ne gadoi, ‘Hina Gode! Na hina A: ibalaha: me ea Gode! Dia na wali hou hamobe fidima!
43 Wò ó, mo dúró ní ẹ̀bá ìsun omi yìí, kí ó ṣe pé, nígbà tí wúńdíá kan bá jáde wá pọn omi, tí èmi sì wí fún un pé, “Jọ̀wọ́ fún mi ní ìwọ̀nba omi díẹ̀ mu nínú ládugbó rẹ,”
Na da hano nasu uli dogoiga esala. A: fini afae hano dimusa: masea, e da nama ea ganagu, hano dili ima: ne na da adole ba: mu.
44 tí ó bá sì wí fún mi pé, “Mu ún, èmi yóò sì tún pọn omi fún àwọn ìbákasẹ rẹ pẹ̀lú,” jẹ́ kí ẹni náà jẹ́ ẹni tí Olúwa yàn fún ọmọ Abrahamu, olúwa mi.’
E da amo iasea amola baligili na ga: mele ilima hano imunusa: sia: sea, amo da na hina ea mano lama: ne a: fini Di ilegei dagoi, na dawa: mu.’
45 “Kí n sì tó gbàdúrà tán nínú ọkàn mi, Rebeka jáde wá pẹ̀lú ìkòkò omi rẹ̀ ní èjìká rẹ̀, ó sì lọ sí ibi ìsun omi ó sì pọn omi. Mo sì wí fun un pé, ‘Jọ̀wọ́ fún mi ni omi mu.’
Na sia: ne gadoi da hame dagoloba, Lebega da hano ganagu gisa manebe ba: i. E hano nasu amoga hano dimusa: sa: i. Na ema amane sia: i, ‘Na da dima edegesa. Hano nama ima.’
46 “Kíákíá ni ó sọ ìkòkò rẹ̀ kalẹ̀ láti èjìká rẹ̀, ó sì wí fún mi pé, ‘Mu ún, èmi yóò sì tún fún àwọn ìbákasẹ rẹ mu pẹ̀lú.’ Mo sì mu, ó sì tún fún àwọn ìbákasẹ mi mu pẹ̀lú.
E hedolo ea ganagu gisi, amo osoba ligisili, amane sia: i, ‘Defea! Moma! Na da dia ga: mele amola ilima hano dili imunu.’ Amalalu, na hano mai, amola e da ga: mele ilima hano i.
47 “Mo béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, ‘Ọmọ ta ní ìwọ í ṣe?’ “Ó sì wí fún mi pé, ‘Ọmọbìnrin Betueli tí í ṣe ọmọ Nahori ni òun, Milka sì ni ìyá òun.’ “Nígbà náà ni mo fi òrùka náà bọ imú rẹ̀, mo sì fi ẹ̀gbà ọwọ́ náà si ní ọwọ́.
Na ema amane adole ba: i, ‘Dia ada nowala: ?’ E bu adole i, ‘Na ada da Bediuele amo Na: iho amola Miliga ela mano.’ Amalalu, na da ea mi amoga mi bione gala: su amola ea lobofasele fei.
48 Èmi sì tẹríba, mo sì wólẹ̀ fún Olúwa, mó sì fi ìbùkún fún Ọlọ́run Abrahamu olúwa mi, ẹni tí ó mú mi tọ ọ̀nà títọ́ láti rí ọmọ ọmọ arákùnrin olúwa mi mú wá fún ọmọ rẹ̀.
Na muguni bugili Hina Godema nodone sia: ne gadoi. Na da Hina Godedafa, na hina A: ibalaha: me ea Gode, amo Ea Dio nodone gaguia gadoi. E da moloiwane na hina ea fi amoga doaga: musa: logo olelei dagoiba: le amola na hina ea mano uda lamu amo noga: le oleleiba: le, na nodoi.
49 Ǹjẹ́ nísinsin yìí bí ẹ̀yin yóò bá fi inú rere àti òtítọ́ bá olúwa mi lò, ẹ sọ fún mi, bí bẹ́ẹ̀ sì kọ́, ẹ sọ fún mi, kí ń le è mọ ọ̀nà tí èmi yóò yà sí.”
Defea! Dilia da moloiwane na hina ea hanai hamomusa: dawa: i galea, nama adoma. Be higa: i galea, amo nama adoma. Amasea, na da fa: no hamomu, amo na da sia: mu.
50 Labani àti Betueli sì dáhùn pé, “Lọ́dọ̀ Olúwa ni èyí ti wá, nítorí náà àwa kò le sọ rere tàbí búburú fún ọ.
La: iba: ne amola Bediuele da bu adole i, “Amo hou Hina Gode Hi hamoiba: le, ninia sia: mu da hamedei.
51 Rebeka nìyí, mú un kí ó máa lọ, kí ó sì di aya ọmọ olúwa à rẹ, bí Olúwa ti fẹ́.”
Lebega da amogai lela. Lale masa. Hina Godedafa Ea sia: defele, e da dia hina ea mano ema fimu da defea.”
52 Nígbà tí ọmọ ọ̀dọ̀ Abrahamu gbọ́ ohun tí wọ́n wí, ó wólẹ̀ níwájú Olúwa.
A: ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu da amo sia: nabaloba, beguduli, Hina Godema nodone sia: ne gadoi.
53 Nígbà náà ni ó kó ohun èlò wúrà àti fàdákà jáde àti aṣọ, ó sì fi wọ́n fún Rebeka, ó fún arákùnrin Rebeka àti ìyá rẹ̀ ní ẹ̀bùn olówó iyebíye pẹ̀lú.
Amalalu, ea liligi amoga e da abula, silifa, gouli amola muni bagade igi lale, Lebegama i. E da muni bagade liligi Lebega ea ola amola ea: mema i.
54 Lẹ́yìn náà ni òun àti àwọn ọkùnrin tí ó bá a wá tó jẹ, tí wọ́n sì mu, tí wọn sì sùn níbẹ̀ ní òru ọjọ́ náà. Bí wọ́n ti dìde ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó wí pé, “Ẹ rán mi padà lọ sí ọ̀dọ̀ olúwa mi.”
Amalalu, A:ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu amola ea fidisu dunu da ha: i amola hano nanu golai. Hahabe, nedigili, wa: legadole, e amane sia: i, “Dilia na hina ema na bu asunasima!”
55 Ṣùgbọ́n arákùnrin Rebeka àti ìyá rẹ̀ fèsì pé, “A fẹ́ kí Rebeka wà pẹ̀lú wa fún nǹkan bí ọjọ́ mẹ́wàá sí i, lẹ́yìn èyí, ìwọ le máa mu lọ.”
Be Lebega ea ola amola ea: me da amane sia: i, “A: fini da hi afae o eso nabuane gala amo gui esalumu da defea. Amolalu masunu da defea.”
56 Ṣùgbọ́n ó wí fún wọn pé, “Ẹ má ṣe dá mi dúró, Olúwa sá à ti ṣe ọ̀nà mi ní rere. Ẹ rán mi lọ, kí èmi kí ó le è tọ olúwa à mi lọ.”
Be e da bu adole i, “Ninia ouesalumu mae sia: ma. Bai Hina Gode da na sofe ahoasu amola hamobe noga: le didili fidi. Na da na hina ema bu masunu da defea.”
57 Nígbà náà ni wọ́n sọ pé, “Jẹ́ kí a pe ọmọ náà gan an kí a sì bi í.”
Ilia da bu adole i, “Ninia da a: fini misa: ne sia: mu. Ea sia: nabimu da defea.”
58 Wọ́n sì pe Rebeka wọ́n sì bi í, wí pé, “Ṣe ìwọ yóò bá ọkùnrin yìí lọ.” Ó sì dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, èmi yóò lọ.”
Amaiba: le, ilia da Lebega misa: ne sia: i. Ilia da ema amane adole ba: i, “Di da amo dunu sigi masa: bela: ?” E bu adole i, “Ma!”
59 Wọ́n sì gbà kí Rebeka àti olùtọ́jú rẹ̀, pẹ̀lú ìránṣẹ́ Abrahamu àti àwọn ọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ máa lọ.
Amabeba: le, ilia da Lebega amola ea hawa: hamosu uda da: i, amo A: ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu, amola ea fidisu dunu amo sigi masa: ne sia: i.
60 Wọ́n sì súre fún Rebeka, wọn sì wí fun un pé, “Ìwọ ni arábìnrin wa ìwọ yóò di ìyá ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rún; ǹjẹ́ kí àwọn irú-ọmọ rẹ kí ó ni ẹnu ibodè ọ̀tá wọn.”
Amola ilia da Lebegama amo hahawane dogolegele sia: su sia: i, “Di, ninia dalusi, dunu fi osea: idafa ilima ame esaloma! Dima lalelegei fi da ilima ha lai dunu, ilima osa: le heda: mu da defea!”
61 Nígbà náà ni Rebeka àti àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ múra, wọn sì gun àwọn ìbákasẹ, wọ́n sì bá ọkùnrin náà padà lọ. Ìránṣẹ́ náà sì mú Rebeka, ó sì bá tirẹ̀ lọ.
Amalalu, Lebega amola ea a: fini fidisu huluane da liligi momagele, ga: mele da: iya fila heda: le, A:ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu sigi asi. A: ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu da Lebega oule asi.
62 Isaaki sì ń ti ọ̀nà kànga Lahai-Roi bọ, nítorí ìhà gúúsù ni ó ń gbé.
Aisage da dunu hame esalebe hafoga: i soge amo ea dio da “Gode Esala da na Ba: lala amo Ea Hano Nasu Uli Dogoi.” amogai misini esalebe ba: i. Amo da Ga: ina: ne soge ga (south) la: idi dialu.
63 Isaaki sì jáde lọ sí oko ni ìrọ̀lẹ́ láti ṣe àṣàrò, bí ó sì ti gbé ojú sókè, ó rí àwọn ìbákasẹ tí ń bọ̀ wá.
E da baloga amo odagiaba sogega ahoanoba, ga: mele manebe ba: i.
64 Rebeka pẹ̀lú sì gbójú sókè, ó sì rí Isaaki. Ó sọ̀kalẹ̀ lórí ìbákasẹ,
Lebega da Aisage ba: loba, ga: mele amoga esalu, gudu aligila sa: i.
65 ó sì béèrè lọ́wọ́ ìránṣẹ́ náà wí pé, “Ta ni ọkùnrin tí ń bọ̀ wá pàdé wa láti inú oko?” Ìránṣẹ́ náà sì wí fun un pé, “Olúwa mi ni,” nítorí náà ni Rebeka mú ìbòjú, ó sì bo ojú rẹ̀.
E da A: ibalaha: me hawa: hamosu dunu ema amane adole ba: i, “Amo dunu ninima manebe da nowala: ?” A: ibalaha: me ea hawa: hamosu dunu da bu adole i, “E da na hina.” Amaiba: le, Lebega da ea dialuma abula lale, ea odagi dedeboi.
66 Nígbà náà ni ìránṣẹ́ náà ròyìn fún Isaaki ohun gbogbo tí ó ti ṣe.
Amalalu, hawa: hamosu dunu da ea hamoi huluane Aisagema olelei.
67 Nígbà náà ni Isaaki mú Rebeka wọ inú àgọ́ ìyá rẹ̀, Sara, ó sì di aya rẹ̀, ó sì fẹ́ràn rẹ̀; ó sì jẹ́ ìtùnú fún Isaaki lẹ́yìn ikú ìyá rẹ̀.
Amalalu, Aisage da Lebega lale, abula diasu amo ea: me Sela musa: esalu amoga oule misi. Aisage da Lebegama bagade asigi galu. Ea: me Sela da bogoi dagoiba: le e da da: i dioi galu. Be Lebega laiba: le ea dogo denesi.