< Genesis 21 >

1 Olúwa sì bẹ Sara wò bí ó ti wí, Olúwa sì ṣe fún Sara gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí.
Na ka tirohia mai a Hara e Ihowa, ka peratia me tana i korero ai, a rite tonu ki tana kupu ta Ihowa i mea ai ki a Hara.
2 Sara sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan fún Abrahamu ní ọjọ́ ogbó rẹ̀, ní àkókò náà gan an tí Ọlọ́run ti ṣèlérí fún un.
Na ka hapu a Hara, a ka whanau he tama ma Aperahama i tona koroheketanga i te wa ano i whakaritea e te Atua ki a ia.
3 Abrahamu sì sọ orúkọ ọmọ náà tí Sara bí fun un ní Isaaki.
Na ka huaina e Aperahama te ingoa o tana tama i whanau nei mana, i whanau mai nei i a Hara, ko Ihaka.
4 Nígbà tí Isaaki pé ọmọ ọjọ́ mẹ́jọ, Abrahamu sì kọ ọ́ ní ilà gẹ́gẹ́ bí Ọlọ́run ti pàṣẹ fún un.
A, ka waru ona ra, ka kotia e Aperahama a Ihaka, tana tama, ka peratia me ta te Atua i whakahau ai ki a ia.
5 Ẹni ọgọ́rùn-ún ọdún ni Abrahamu nígbà tí ó bí Isaaki.
A kotahi rua nga tau o Aperahama i te whanautanga o tana tama, o Ihaka.
6 Sara sì wí pé, “Ọlọ́run ti pa mí lẹ́rìn-ín. Gbogbo ẹni tí ó bá sì gbọ́ pé mo bímọ yóò rẹ́rìn-ín pẹ̀lú mi.”
Na ka mea a Hara, Kua meinga ahau e te Atua kia kata; a ka kata tahi matou ko nga tangata e rongo mai ana.
7 Ó sì fi kún un pé, “Ta ni ó le sọ fún Abrahamu pé, Sara yóò di ọlọ́mọ? Síbẹ̀síbẹ̀, mo sì tún bí ọmọ fún Abrahamu ní ìgbà ogbó rẹ.”
A i mea ano ia, Ko wai o mua hei mea ki a Aperahama, tera e whakangote tamariki a Hara? kua whanau nei i ahau he tama mana, i a ia kua koroheketia.
8 Nígbà tí ọmọ náà dàgbà, ó sì gbà á lẹ́nu ọmú, ní ọjọ́ tí a gba Isaaki lẹ́nu ọmú, Abrahamu ṣe àsè ńlá.
Na ka tupu te tamaiti ra, a ka whakamutua tana kai u: na ka tukua e Aperahama tetahi hakari nui i te ra i whakamutua ai te ngote u a Ihaka.
9 Ṣùgbọ́n Sara rí ọmọ Hagari ará Ejibiti tí ó bí fún Abrahamu tí ó fi ṣe ẹlẹ́yà,
A ka kite a Hara i te tama a Hakara, a te wahine o Ihipa, i whanau nei i a raua ko Aperahama, e kata whakahawea ana.
10 ó sì wí fún Abrahamu pé, “Lé ẹrúbìnrin yìí àti ọmọ rẹ̀ jáde, nítorí ọmọ ẹrú yìí kò ní bá ọmọ mi Isaaki pín ogún.”
Na ka mea ia ki a Aperahama, Peia atu tenei pononga me tana tama: e kore rawa te tama a tenei wahine pononga e tu tahi me taku tama, me Ihaka, i nga whakarerenga iho.
11 Ọ̀rọ̀ náà sì ba Abrahamu lọ́kàn jẹ́ gidigidi nítorí ọmọ rẹ̀ náà sá à ni Iṣmaeli i ṣe.
A ko taua mea he he rawa ki te titiro a Aperahama, ko tana tama hoki ia.
12 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run wí fun Abrahamu pé, “Má ṣe ba ọkàn jẹ́ nítorí ọmọ náà àti ẹrúbìnrin rẹ. Gbọ́ ohun tí Sara wí fún ọ, nítorí nínú Isaaki ni a ó ti pe irú-ọmọ rẹ̀.
Ka mea te Atua ki a Aperahama, Kei kino tena ki tau titiro, kaua e whakaaro ki te tamaiti raua ko tau pononga wahine; engari i nga mea katoa i korero ai a Hara ki a koe, whakarongo atu ki tona reo; kei a Ihaka hoki te karangatanga mo tou uri.
13 Èmi yóò sọ ọmọ ẹrúbìnrin náà di orílẹ̀-èdè pẹ̀lú, nítorí ọmọ rẹ ni.”
Na, ko te tama a te pononga wahine, ka meinga ia e ahau hei iwi, no te mea he uri ia nou.
14 Abrahamu sì dìde ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó sì mú oúnjẹ àti ìgò omi kan, ó sì kó wọn fún Hagari, ó kó wọn lé e léjìká, ó sì lé e jáde pẹ̀lú ọmọ náà. Ó sì lọ lọ́nà rẹ, ó sì ń ṣe alárìnkiri ní ijù Beerṣeba.
Na ka maranga wawe a Aperahama i te ata, ka mau ki tetahi taro, ki tetahi taha wai, a hoatu ana e ia ki a Hakara, whakawaha ana ki tona pokohiwi, me te tamaiti hoki, a tonoa atu ana: na ka haere ia, ka kopikopiko i te koraha o Peerehepa.
15 Nígbà tí omi inú ìgò náà tan, ó gbé ọmọ náà sí abẹ́ igbó.
A kau pau te wai i roto i te taha, na whakarerea iho e ia te tamaiti i raro i tetahi rakau iti.
16 Ó sì lọ, ó sì jókòó nítòsí ibẹ̀, níwọ̀n bí ìtafà kan, nítorí, ó rò ó nínú ara rẹ̀ pé, “Èmi kò fẹ́ wo bí ọmọ náà yóò ṣe kú.” Bí ó sì ti jókòó sí tòsí ibẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ sí ní sọkún.
Na ka haere ia, a ka noho mai i tawhiti, me te anga nui mai ano ki a ia, he pera te matara me te taunga pere: i mea hoki ia, Kei kite ahau i te matenga o te tamaiti. Na ka noho ia me te aronui mai ki a ia, a ka puaki tona reo, ka tangi.
17 Ọlọ́run gbọ́ ohun ẹkún náà, Angẹli Ọlọ́run sì pe Hagari láti ọ̀run, ó sì wí fun un pé, “Hagari, kín ni ó ṣe ọ́? Má bẹ̀rù nítorí Ọlọ́run ti gbọ́ ẹkún ọmọ náà níbi tí o tẹ́ ẹ sí.
A i rongo te Atua ki te reo o te tamaiti: a ka karanga mai te anahera a te Atua ki a Hakara i runga i te rangi, ka mea ki a ia, He aha kei a koe, e Hakara? kaua e wehi; kua rongo hoki te Atua ki te reo o te tamaiti i a ia e takoto na.
18 Dìde, gbé ọmọ náà sókè, kí o sì dìímú (tù ú nínú) nítorí èmi yóò sọ ọmọ náà di orílẹ̀-èdè ńlá.”
Whakatika, hapainga ake te tamaiti, puritia hoki ki tou ringa; no te mea ka meinga ia e ahau hei iwi nui.
19 Ọlọ́run sì ṣí ojú Hagari, ó sì rí kànga kan, ó lọ síbẹ̀, ó rọ omi kún inú ìgò náà, ó sì fún ọmọ náà mu.
Na ka whakatirohia e te Atua ona kanohi, a ka kite ia i tetahi puna wai: na ka haere ia, ka whakaki i te taha ki te wai, a whakainumia ana te tamaiti.
20 Ọlọ́run sì wà pẹ̀lú ọmọ náà bí ó ti ń dàgbà, ó ń gbé nínú ijù, ó sì di tafàtafà.
A i noho te Atua ki te tamaiti, a ka tupu ia; i noho ia i te koraha, a ka mohio ki te kopere.
21 Nígbà tí ó ń gbé ni aginjù ní Parani, ìyá rẹ̀ fẹ́ ìyàwó fún un láti ilẹ̀ Ejibiti wá.
Na ka noho ia ki te koraha o Parana: a ka tikina atu e tona whaea he wahine mana i te whenua o Ihipa.
22 Ní àkókò yìí ni ọba Abimeleki àti Fikoli, olórí ogun rẹ̀ wí fún Abrahamu pé, “Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀ nínú gbogbo ohun tí ó ń ṣe.
A i taua wa ano ka korero a Apimereke raua ko Pikora, ko te rangatira o tana ope, ki a Aperahama, ka mea, Na kei a koe te Atua i nga mea katoa e mea ai koe:
23 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, fi Ọlọ́run búra fún mi, ìwọ kì yóò tàn mí àti àwọn ọmọ mi àti àwọn ìran mi, ìwọ yóò fi inú rere hàn fún mi àti orílẹ̀-èdè tí ìwọ ti ṣe àtìpó, bí mo ti fihàn fún ọ pẹ̀lú.”
Tena oatitia mai te Atua ki ahau, e kore koe e teka ki ahau, ki taku tama, ki te tama ranei a taku tama; engari ka rite ki te aroha i whakaputaina e ahau ki a koe tau mahi ki ahau, ki te whenua ano hoki i noho nei koe.
24 Abrahamu sì wí pé, “Èmí búra.”
Na ka mea a Aperahama, Ka oati ahau.
25 Nígbà náà ni Abrahamu fi ẹ̀dùn ọkàn rẹ̀ hàn fún Abimeleki nípa kànga tí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ gbà lọ́wọ́ rẹ̀.
Na ka whakawa a Aperahama i a Apimereke mo tetahi puna wai i murua e nga tangata a Apimereke.
26 Ṣùgbọ́n Abimeleki dáhùn pé, “Èmi kò mọ ẹni tí ó ṣe nǹkan yìí. Ìwọ kò sì sọ fún mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò gbọ́, bí kò ṣe lónìí.”
Na ka mea a Apimereke, Kahore ahau e mohio na wai ranei tenei mahi: kihai hoki koe i korero mai ki ahau, a kihai ahau i rongo, no tenei ra tonu.
27 Abrahamu sì mú àgùntàn àti màlúù wá, ó sì kó wọn fún Abimeleki. Àwọn méjèèjì sì dá májẹ̀mú.
Na ka tikina e Aperahama he hipi, he kau, ka hoatu ki a Apimereke; na ka whakarite kawenata raua.
28 Abrahamu sì ya abo ọ̀dọ́-àgùntàn méje nínú agbo àgùntàn rẹ̀ sọ́tọ̀.
Na ka wehea e Aperahama ki tahaki e whitu nga reme uha o nga hipi.
29 Abimeleki sì béèrè lọ́wọ́ Abrahamu pé, “Kín ni ìtumọ̀ yíyà tí ìwọ ya àwọn ọ̀dọ́-àgùntàn méje wọ̀nyí sọ́tọ̀ sí.”
A ka mea a Apimereke ki a Aperahama, He aha te tikanga o enei reme uha e whitu i wehea nei e koe ki tahaki?
30 Ó dalóhùn pé, “Gba àwọn abo ọ̀dọ́-àgùntàn méje wọ̀nyí lọ́wọ́ mi gẹ́gẹ́ bí ẹ̀rí pé èmi ni mo gbẹ́ kànga yìí.”
Ka mea ia, Ko enei reme uha e whitu me tango e koe i toku ringa, kia ai enei mea hei whakaatu maku, naku i keri tenei poka.
31 Nítorí náà ni a ṣe ń pe ibẹ̀ náà ni Beerṣeba nítorí níbẹ̀ ni àwọn méjèèjì gbé búra.
Na reira i huaina ai e ia taua wahi ko Peerehepa; no raua hoki oati ki reira.
32 Lẹ́yìn májẹ̀mú tí wọ́n dá ní Beerṣeba yìí, ni Abimeleki àti Fikoli olórí ogun rẹ̀ padà sí ilẹ̀ àwọn ará Filistini.
Heoi whakaritea ana e raua te kawenata i Peerehepa: a ka whakatika a Apimereke raua ko Pikora, ko te rangatira o tana ope, a hoki ana ki te whenua o nga Pirihitini.
33 Abrahamu lọ́ igi tamariski kan sí Beerṣeba, níbẹ̀ ni ó sì pe orúkọ Olúwa Ọlọ́run ayérayé.
Na ka whakatokia e Aperahama he rakau, he tamarihi, ki Peerehepa, a ka karanga i reira ki te ingoa o Ihowa, o te Atua ora tonu.
34 Abrahamu sì gbé ilẹ̀ àwọn ará Filistini fún ọjọ́ pípẹ́.
A ka noho a Aperahama ki te whenua o nga Pirihitini mo nga ra maha.

< Genesis 21 >