< Genesis 20 >

1 Abrahamu sì kó kúrò níbẹ̀ lọ sí ìhà gúúsù ó sì ń gbé ní agbede-méjì Kadeṣi àti Ṣuri; ó sì gbé ní ìlú Gerari fún ìgbà díẹ̀.
Авраам а плекат де аколо ын цара де мязэзи, с-а ашезат ынтре Кадес ши Шур ши а локуит ка стрэин ын Герар.
2 Abrahamu sì sọ ní ti Sara aya rẹ̀ níbẹ̀ pé, “Arábìnrin mi ni.” Abimeleki ọba Gerari sì ránṣẹ́ mú Sara wá sí ààfin rẹ̀.
Авраам зичя деспре Сара, невастэ-са: „Есте сора мя!” С-а темут сэ спунэ кэ есте невастэ-са, ка сэ ну-л омоаре оамений дин четате дин причина ей. Абимелек, ымпэратул Герарулуй, а тримис ши а луат пе Сара.
3 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run tọ Abimeleki wá ní ojú àlá lọ́jọ́ kan, ó sì wí fún un pé, “Kíyèsi, kò sí ohun tí o fi sàn ju òkú lọ, nítorí obìnrin tí ìwọ mú sọ́dọ̀ n nì, aya ẹni kan ní íṣe.”
Атунч, Думнезеу С-а арэтат ноаптя ын вис луй Абимелек ши й-а зис: „Ятэ, ай сэ морь дин причина фемеий пе каре ай луат-о, кэч есте неваста унуй бэрбат.”
4 Ṣùgbọ́n Abimeleki kò tí ìbá obìnrin náà lòpọ̀, nítorí náà ó wí pé, “Olúwa ìwọ yóò run orílẹ̀-èdè aláìlẹ́bi bí?
Абимелек, каре ну се апропиясе де еа, а рэспунс: „Доамне, вей оморы Ту оаре кяр ши ун ням невиноват?
5 Ǹjẹ́ òun kò sọ fún mi pé, ‘Arábìnrin mi ni,’ obìnrin náà pẹ̀lú sì sọ pé, ‘Arákùnrin mí ni’? Ní òtítọ́ pẹ̀lú ọkàn mímọ́ àti ọwọ́ mímọ́, ni mo ṣe èyí.”
Ну мь-а спус ел кэ есте сорэ-са? Ши н-а зис еа ынсэшь кэ ел есте фрате-сэу? Еу ам лукрат ку инимэ куратэ ши ку мынь невиновате.”
6 Nígbà náà ni Ọlọ́run wí fún un nínú àlá náà pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, mo mọ̀ pé pẹ̀lú òtítọ́ inú ni ìwọ ṣe èyí, èyí ni mo fi pa ọ́ mọ́ tí ń kò jẹ́ kí o ṣẹ̀ sí mi. Ìdí nìyí tí n kò fi jẹ́ kí o ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin náà.
Думнезеу й-а зис ын вис: „Штиу ши Еу кэ ай лукрат ку инимэ куратэ, де ачея те-ам ши ферит сэ пэкэтуешть ымпотрива Мя. Ятэ де че н-ам ынгэдуит сэ те атинӂь де еа.
7 Nísinsin yìí, dá aya ọkùnrin náà padà, nítorí pé wòlíì ni, yóò sì gbàdúrà fún ọ, ìwọ yóò sì yè. Ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá dá a padà, mọ̀ dájú pé ìwọ àti gbogbo ẹni tí í ṣe tìrẹ yóò kú.”
Акум, дэ омулуй неваста ынапой, кэч ел есте пророк. Се ва руга пентру тине ши вей трэи. Дар, дакэ н-о дай ынапой, сэ штий кэ вей мури негрешит, ту ши тот че-й ал тэу.”
8 Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù ọjọ́ kejì, Abimeleki pe gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀. Nígbà tí ó sì sọ gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún wọn, ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi.
Абимелек с-а скулат дис-де-диминяцэ, а кемат пе тоць служиторий сэй ши ле-а спус тот че се ынтымпласе. Ши оамений ачея ау фост куприншь де о маре спаймэ.
9 Nígbà náà ni Abimeleki pe Abrahamu ó sì wí fún un pé, “Èwo ni èyí tí ìwọ ṣe sí wa yìí? Ẹ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ ọ́ tí ìwọ fi mú ìdálẹ́bi ńlá wá sí orí èmi àti ìjọba mi? Kò yẹ kí ìwọ hu irú ìwà yìí sí mi.”
Абимелек а кемат ши пе Авраам ши й-а зис: „Че не-ай фэкут? Ши ку че ам пэкэтуит еу ымпотрива та, де ай фэкут сэ винэ песте мине ши песте ымпэрэция мя ун пэкат атыт де маре? Ай фэкут фацэ де мине лукрурь каре ну требуяу ничдекум фэкуте.”
10 Abimeleki sì bi Abrahamu pé, “Kín ló dé tí ìwọ fi ṣe èyí?”
Ши Абимелек а зис луй Авраам: „Че ай вэзут де ай фэкут лукрул ачеста?”
11 Abrahamu sì dáhùn pé, “Mo ṣe èyí nítorí mo rò nínú ara mi pé, ẹ̀yin tí ẹ wà níhìn-ín, ẹ kò bẹ̀rù Ọlọ́run, pé, ẹ sì le pa mí nítorí aya mi.
Авраам а рэспунс: „Ымь зичям кэ, фэрэ ындоялэ, ну-й ничо фрикэ де Думнезеу ын цара ачаста ши кэ ау сэ мэ омоаре дин причина невестей меле.
12 Yàtọ̀ fún ìyẹn, òtítọ́ ni pé arábìnrin mi ni. Ọmọ baba kan ni wá, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, a kì í ṣe ọmọ ìyá kan. Mo sì fẹ́ ẹ ní aya.
Де алтфел, есте адевэрат кэ есте сора мя, фийка татэлуй меу; нумай кэ ну-й фийка мамей меле ши а ажунс сэ-мь фие невастэ.
13 Nígbà tí Ọlọ́run sì mú mi rìn kiri kúrò ní ilé baba mi, mo wí fún un pé, ‘Èyí ni ọ̀nà tí ó lè gbà fihàn pé ó fẹ́ràn mi. Gbogbo ibi tí a bá dé máa sọ pé, “Arákùnrin rẹ ni mí.”’”
Кынд м-а скос Думнезеу дин каса татэлуй меу, ам зис Сарей: ‘Ятэ хатырул пе каре ай сэ ми-л фачь: ын тоате локуриле унде вом мерӂе, спуне деспре мине кэ сунт фрателе тэу.’”
14 Nígbà náà ni Abimeleki mú àgùntàn àti màlúù wá, àti ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin, ó sì kó wọn fún Abrahamu, ó sì dá Sara aya rẹ̀ padà fún un.
Абимелек а луат ой ши бой, робь ши роабе ши ле-а дат луй Авраам ши й-а дат ынапой ши пе Сара, невастэ-са.
15 Abimeleki sì tún wí fún un pé, “Gbogbo ilẹ̀ mí nìyí níwájú rẹ, máa gbé ní ibikíbi tí o fẹ́ níbẹ̀.”
Абимелек а зис: „Ятэ, цара мя есте ынаинтя та; локуеште унде-ць ва плэчя.”
16 Abimeleki sì wí fún Sara pé, “Mo fi ẹgbẹ̀rún owó ẹyọ fàdákà fún arákùnrin rẹ. Èyí ni owó ìtánràn ẹ̀ṣẹ̀ mi sí ọ níwájú gbogbo ẹni tí ó wà pẹ̀lú rẹ àti pé, a dá ọ láre pátápátá.”
Ши Сарей й-а зис: „Ятэ, дау фрателуй тэу о мие де арӂинць; ачаста сэ-ць фие о довадэ де чинсте фацэ де тоць чей че сунт ку тине, аша кэ ынаинтя тутурор вей фи фэрэ винэ.”
17 Nígbà náà, Abrahamu gbàdúrà sí Ọlọ́run, Ọlọ́run sì wo Abimeleki àti aya rẹ̀ àti àwọn ẹrúbìnrin rẹ̀ sàn. Wọ́n sì tún ń bímọ,
Авраам с-а ругат луй Думнезеу, ши Думнезеу а ынсэнэтошит пе Абимелек, пе неваста ши роабеле луй, аша кэ ау путут сэ наскэ.
18 nítorí Olúwa ti sé gbogbo ará ilé Abimeleki nínú nítorí Sara aya Abrahamu.
Фииндкэ Домнул ынкуясе пынтечеле тутурор фемеилор дин каса луй Абимелек дин причина Сарей, неваста луй Авраам.

< Genesis 20 >