< Genesis 20 >

1 Abrahamu sì kó kúrò níbẹ̀ lọ sí ìhà gúúsù ó sì ń gbé ní agbede-méjì Kadeṣi àti Ṣuri; ó sì gbé ní ìlú Gerari fún ìgbà díẹ̀.
UAbrahama wasesuka lapho waya elizweni leningizimu, wahlala phakathi kweKadeshi leShuri wahlala njengowezizwe eGerari.
2 Abrahamu sì sọ ní ti Sara aya rẹ̀ níbẹ̀ pé, “Arábìnrin mi ni.” Abimeleki ọba Gerari sì ránṣẹ́ mú Sara wá sí ààfin rẹ̀.
UAbrahama wasesithi ngoSara umkakhe: Ungudadewethu. UAbhimeleki inkosi yeGerari wathuma-ke, wathatha uSara.
3 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run tọ Abimeleki wá ní ojú àlá lọ́jọ́ kan, ó sì wí fún un pé, “Kíyèsi, kò sí ohun tí o fi sàn ju òkú lọ, nítorí obìnrin tí ìwọ mú sọ́dọ̀ n nì, aya ẹni kan ní íṣe.”
Kodwa uNkulunkulu weza kuAbhimeleki ephutsheni ebusuku, wathi kuye: Khangela, ufile ngenxa yowesifazana omthetheyo, ngoba uganile endodeni.
4 Ṣùgbọ́n Abimeleki kò tí ìbá obìnrin náà lòpọ̀, nítorí náà ó wí pé, “Olúwa ìwọ yóò run orílẹ̀-èdè aláìlẹ́bi bí?
Kodwa uAbhimeleki wayengasondelanga kuye. Ngakho wathi: Nkosi, uzabhubhisa lesizwe esilungileyo yini?
5 Ǹjẹ́ òun kò sọ fún mi pé, ‘Arábìnrin mi ni,’ obìnrin náà pẹ̀lú sì sọ pé, ‘Arákùnrin mí ni’? Ní òtítọ́ pẹ̀lú ọkàn mímọ́ àti ọwọ́ mímọ́, ni mo ṣe èyí.”
Kayisuye yini othe kimi: Ungudadewethu? Laye uqobo wasesithi: Ungumnewethu. Ngobuqotho benhliziyo yami langobuhlophe bezandla zami ngikwenzile lokhu.
6 Nígbà náà ni Ọlọ́run wí fún un nínú àlá náà pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, mo mọ̀ pé pẹ̀lú òtítọ́ inú ni ìwọ ṣe èyí, èyí ni mo fi pa ọ́ mọ́ tí ń kò jẹ́ kí o ṣẹ̀ sí mi. Ìdí nìyí tí n kò fi jẹ́ kí o ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin náà.
UNkulunkulu wasesithi kuye ephutsheni: Lami sengazile ukuthi ngobuqotho benhliziyo yakho ukwenzile lokhu; lami futhi ngikuvimbele ukuze ungoni kimi; ngenxa yalokhu kangikuvumelanga ukuthi umthinte.
7 Nísinsin yìí, dá aya ọkùnrin náà padà, nítorí pé wòlíì ni, yóò sì gbàdúrà fún ọ, ìwọ yóò sì yè. Ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá dá a padà, mọ̀ dájú pé ìwọ àti gbogbo ẹni tí í ṣe tìrẹ yóò kú.”
Ngakho-ke buyisela umfazi wendoda, ngoba ingumprofethi; njalo izakukhulekela ukuze uphile; kodwa uba ungambuyiseli, yazi ukuthi isibili uzakufa wena labo bonke abangabakho.
8 Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù ọjọ́ kejì, Abimeleki pe gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀. Nígbà tí ó sì sọ gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún wọn, ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi.
UAbhimeleki wasevuka ekuseni kakhulu, wabiza zonke inceku zakhe, wakhuluma wonke la amazwi endlebeni zazo; njalo amadoda esaba kakhulu.
9 Nígbà náà ni Abimeleki pe Abrahamu ó sì wí fún un pé, “Èwo ni èyí tí ìwọ ṣe sí wa yìí? Ẹ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ ọ́ tí ìwọ fi mú ìdálẹ́bi ńlá wá sí orí èmi àti ìjọba mi? Kò yẹ kí ìwọ hu irú ìwà yìí sí mi.”
UAbhimeleki wasembiza uAbrahama, wathi kuye: Wenzeni kithi? Ngoneni kuwe ukuthi ungilethele mina lombuso wami isono esikhulu? Wenze kimi izenzo ezingafanelanga ukwenziwa.
10 Abimeleki sì bi Abrahamu pé, “Kín ló dé tí ìwọ fi ṣe èyí?”
UAbhimeleki wasesithi kuAbrahama: Uboneni, uze wenze into le?
11 Abrahamu sì dáhùn pé, “Mo ṣe èyí nítorí mo rò nínú ara mi pé, ẹ̀yin tí ẹ wà níhìn-ín, ẹ kò bẹ̀rù Ọlọ́run, pé, ẹ sì le pa mí nítorí aya mi.
UAbrahama wasesithi: Ngoba ngacabanga ukuthi: Isibili ukwesaba uNkulunkulu kakukho kulindawo; njalo bazangibulala ngenxa yomkami.
12 Yàtọ̀ fún ìyẹn, òtítọ́ ni pé arábìnrin mi ni. Ọmọ baba kan ni wá, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, a kì í ṣe ọmọ ìyá kan. Mo sì fẹ́ ẹ ní aya.
Kanti-ke isibili ungudadewethu, uyindodakazi kababa, kodwa kasiyo indodakazi kamama; wasesiba ngumkami.
13 Nígbà tí Ọlọ́run sì mú mi rìn kiri kúrò ní ilé baba mi, mo wí fún un pé, ‘Èyí ni ọ̀nà tí ó lè gbà fihàn pé ó fẹ́ràn mi. Gbogbo ibi tí a bá dé máa sọ pé, “Arákùnrin rẹ ni mí.”’”
Kwasekusithi mhla uNkulunkulu engizulisa ngisuka endlini kababa ngasengisithi kuye: Lo ngumusa ozawenza kimi, kuzo zonke indawo esizafika kuzo, uthi ngami: Ungumnewethu.
14 Nígbà náà ni Abimeleki mú àgùntàn àti màlúù wá, àti ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin, ó sì kó wọn fún Abrahamu, ó sì dá Sara aya rẹ̀ padà fún un.
UAbhimeleki wasethatha izimvu lezinkomo lezinceku lezincekukazi, wapha uAbrahama, wambuyisela uSara umkakhe.
15 Abimeleki sì tún wí fún un pé, “Gbogbo ilẹ̀ mí nìyí níwájú rẹ, máa gbé ní ibikíbi tí o fẹ́ níbẹ̀.”
UAbhimeleki wasesithi: Khangela, ilizwe lami liphambi kwakho; hlala lapho okuhle khona emehlweni akho.
16 Abimeleki sì wí fún Sara pé, “Mo fi ẹgbẹ̀rún owó ẹyọ fàdákà fún arákùnrin rẹ. Èyí ni owó ìtánràn ẹ̀ṣẹ̀ mi sí ọ níwájú gbogbo ẹni tí ó wà pẹ̀lú rẹ àti pé, a dá ọ láre pátápátá.”
LakuSara wathi: Khangela, ngimnikile umnewenu inhlamvu zesiliva eziyinkulungwane; khangela, uyisisibekelo samehlo kuwe, kuye wonke olawe, labo bonke, njalo ukhuziwe.
17 Nígbà náà, Abrahamu gbàdúrà sí Ọlọ́run, Ọlọ́run sì wo Abimeleki àti aya rẹ̀ àti àwọn ẹrúbìnrin rẹ̀ sàn. Wọ́n sì tún ń bímọ,
UAbrahama wasekhuleka kuNkulunkulu; uNkulunkulu wasemsilisa uAbhimeleki lomkakhe lencekukazi zakhe, ukuze bazale.
18 nítorí Olúwa ti sé gbogbo ará ilé Abimeleki nínú nítorí Sara aya Abrahamu.
Ngoba iNkosi yayizivalile ngokupheleleyo izizalo zonke zabendlu kaAbhimeleki ngenxa kaSara umkaAbrahama.

< Genesis 20 >