< Genesis 20 >

1 Abrahamu sì kó kúrò níbẹ̀ lọ sí ìhà gúúsù ó sì ń gbé ní agbede-méjì Kadeṣi àti Ṣuri; ó sì gbé ní ìlú Gerari fún ìgbà díẹ̀.
Te phoeiah Abraham loh Negev kho la puen uh tih Kadesh neh Shur laklo ah kho a sak vaengkah Gerar ah bakuep.
2 Abrahamu sì sọ ní ti Sara aya rẹ̀ níbẹ̀ pé, “Arábìnrin mi ni.” Abimeleki ọba Gerari sì ránṣẹ́ mú Sara wá sí ààfin rẹ̀.
Te vaengah Abraham loh a yuu Sarah te ka ngannu ni a ti dongah Gerar manghai Abimelek a tah tih Sarah te a loh.
3 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run tọ Abimeleki wá ní ojú àlá lọ́jọ́ kan, ó sì wí fún un pé, “Kíyèsi, kò sí ohun tí o fi sàn ju òkú lọ, nítorí obìnrin tí ìwọ mú sọ́dọ̀ n nì, aya ẹni kan ní íṣe.”
Tedae Abimelek te khoyin a mang ah Pathen loh a paan tih a taengah, “Rhukom tangtae hlang yuu te na rhawt dongah na duek coeng ne,” a ti nah.
4 Ṣùgbọ́n Abimeleki kò tí ìbá obìnrin náà lòpọ̀, nítorí náà ó wí pé, “Olúwa ìwọ yóò run orílẹ̀-èdè aláìlẹ́bi bí?
Te dongah Abimelek loh anih te ben pawh. Tedae, “Boeipa namtom loh dueng cakhaw na ngawn aya?
5 Ǹjẹ́ òun kò sọ fún mi pé, ‘Arábìnrin mi ni,’ obìnrin náà pẹ̀lú sì sọ pé, ‘Arákùnrin mí ni’? Ní òtítọ́ pẹ̀lú ọkàn mímọ́ àti ọwọ́ mímọ́, ni mo ṣe èyí.”
Amah loh kai taengah, ‘Anih ka ngannu a ti tih he long khaw ka nganpa ni,’ a ti moenih a? Ka thinko thincaknah neh, ka kut cimcaihnah nen ni he khaw ka saii,” a ti nah.
6 Nígbà náà ni Ọlọ́run wí fún un nínú àlá náà pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, mo mọ̀ pé pẹ̀lú òtítọ́ inú ni ìwọ ṣe èyí, èyí ni mo fi pa ọ́ mọ́ tí ń kò jẹ́ kí o ṣẹ̀ sí mi. Ìdí nìyí tí n kò fi jẹ́ kí o ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú obìnrin náà.
Te dongah anih te a mang ah Pathen loh, “Ue hekah he nang loh thinko thincaknah neh na saii tila ka ming. Tedae anih taek sak ham nang kam paek pawt dongah kai taengah tholh khui lamloh nang te kan tuem kan soem.
7 Nísinsin yìí, dá aya ọkùnrin náà padà, nítorí pé wòlíì ni, yóò sì gbàdúrà fún ọ, ìwọ yóò sì yè. Ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá dá a padà, mọ̀ dájú pé ìwọ àti gbogbo ẹni tí í ṣe tìrẹ yóò kú.”
Tahae ah hlang yuu te mael laeh. Anih te tonghma tih nang ham a thangthui daengah ni na hing eh. Na mael pawt atah na taengkah boeih neh namah khaw na duek rhoe na duek ni tila ming laeh,” a ti nah.
8 Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù ọjọ́ kejì, Abimeleki pe gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀. Nígbà tí ó sì sọ gbogbo ohun tí ó ṣẹlẹ̀ fún wọn, ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi.
Te dongah Abimelek te mincang ah thoo tih a sal boeih te a khue. Te phoeiah hekah olka boeih he amih hna ah a thui hatah hlang boeih loh a rhih uh.
9 Nígbà náà ni Abimeleki pe Abrahamu ó sì wí fún un pé, “Èwo ni èyí tí ìwọ ṣe sí wa yìí? Ẹ̀ṣẹ̀ wo ni mo ṣẹ̀ ọ́ tí ìwọ fi mú ìdálẹ́bi ńlá wá sí orí èmi àti ìjọba mi? Kò yẹ kí ìwọ hu irú ìwà yìí sí mi.”
Abimelek loh Abraham te a khue tih, “Kaimih ham balae na saii, nang taengah metlam ka tholh tih kamah so neh ka ram ah tholh muep nan khuen. Kai taengah na saii bibi te a saii uh noek moenih,” a ti nah.
10 Abimeleki sì bi Abrahamu pé, “Kín ló dé tí ìwọ fi ṣe èyí?”
Te dongah Abimelek loh Abraham te, “Hekah dumlai he na saii vaengah balae na hmuh,” a ti nah.
11 Abrahamu sì dáhùn pé, “Mo ṣe èyí nítorí mo rò nínú ara mi pé, ẹ̀yin tí ẹ wà níhìn-ín, ẹ kò bẹ̀rù Ọlọ́run, pé, ẹ sì le pa mí nítorí aya mi.
Tedae Abraham loh, “Hekah hmuen ah Pathen hinyahnah om pawt tih ka yuu kah olka ah kai n'ngawn uh ve ka ti dongah ni.
12 Yàtọ̀ fún ìyẹn, òtítọ́ ni pé arábìnrin mi ni. Ọmọ baba kan ni wá, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, a kì í ṣe ọmọ ìyá kan. Mo sì fẹ́ ẹ ní aya.
Tedae anih te a pa canu ka ngannu rhep ni. A nu canu pawt dae ka yuu lam khaw om ngawn.
13 Nígbà tí Ọlọ́run sì mú mi rìn kiri kúrò ní ilé baba mi, mo wí fún un pé, ‘Èyí ni ọ̀nà tí ó lè gbà fihàn pé ó fẹ́ràn mi. Gbogbo ibi tí a bá dé máa sọ pé, “Arákùnrin rẹ ni mí.”’”
Te dongah a pa im lamkah Pathen loh kai kho m'hmang sak vaengah anih taengah, ‘Nang kah sitlohnah he kai taengah na saii ham atah mekah hmuen boeih ah m'pha cakhaw, anih he ka nganpa ni ti ne,’ tila kamah loh pahoi ka ti nah coeng,” a ti nah.
14 Nígbà náà ni Abimeleki mú àgùntàn àti màlúù wá, àti ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin, ó sì kó wọn fún Abrahamu, ó sì dá Sara aya rẹ̀ padà fún un.
Te vaengah Abimelek loh tu neh saelhung khaw, sal tongpa neh salnu khaw a loh tih Abraham te a paek. A yuu Sarah te khaw amah taengah a mael.
15 Abimeleki sì tún wí fún un pé, “Gbogbo ilẹ̀ mí nìyí níwájú rẹ, máa gbé ní ibikíbi tí o fẹ́ níbẹ̀.”
Te phoeiah Abimelek loh, “Na mikhmuh kah ka khohmuen aka om he namah mik ah then na ti bangla khosa ngawn ne,” a ti nah.
16 Abimeleki sì wí fún Sara pé, “Mo fi ẹgbẹ̀rún owó ẹyọ fàdákà fún arákùnrin rẹ. Èyí ni owó ìtánràn ẹ̀ṣẹ̀ mi sí ọ níwájú gbogbo ẹni tí ó wà pẹ̀lú rẹ àti pé, a dá ọ láre pátápátá.”
Sarah taengah khaw, “Na nganpa taengah tangka thawngkhat te, nang ham hmaithennah la ka paek coeng tih namah taengkah aka om boeih neh hlang boeih hmaiah na tang uh coeng he,” a ti nah.
17 Nígbà náà, Abrahamu gbàdúrà sí Ọlọ́run, Ọlọ́run sì wo Abimeleki àti aya rẹ̀ àti àwọn ẹrúbìnrin rẹ̀ sàn. Wọ́n sì tún ń bímọ,
Tedae Abraham te Pathen taengah thangthui. Pathen loh Abimelek khaw, a yuu khaw, a salnu rhoek khaw a hoeih sak dongah ca a sak uh.
18 nítorí Olúwa ti sé gbogbo ará ilé Abimeleki nínú nítorí Sara aya Abrahamu.
Abraham yuu Sarah kah lai ah Abimelek im kah hlang bung boeih te BOEIPA loh a khaih rhoela a khaih pah.

< Genesis 20 >