< Genesis 18 >

1 Olúwa sì farahan Abrahamu nítòsí àwọn igi ńlá Mamre, bí ó ti jókòó ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ rẹ̀, nígbà tí ọjọ́-kanrí tí oòrùn sì mú.
Abrahamu'a zagemo tusi amuho higeno, Mamrea hunagru hu'nea oki zafa agafare seli noma'a kasante mani'negeno, Ra Anumzamo'a anante ehanati'ne.
2 Abrahamu gbójú sókè, ó sì rí àwọn ọkùnrin mẹ́ta tí wọn dúró nítòsí rẹ̀. Nígbà tí ó rí wọn, ó sáré láti lọ pàdé wọn, ó sì tẹríba bí ó ti ń kí wọn.
Seli noma'a kasante mani'nereti kesga huno keana, taregi magoki vahe oti'nageno keteno, agareno viazamo zamagafi ome arena areno kepri huno,
3 Ó wí pé, “Bí mo bá rí ojúrere yín Olúwa mi, ẹ má ṣe lọ láì yà sọ́dọ̀ ìránṣẹ́ yín.
anage hu'ne, Ranimota nagrama knare nehanugeta musema nehusuta eri'za vahetami mani'nogu muse huramantoanki nagatereta eoviho!
4 Ẹ jẹ́ kí a bu omi díẹ̀ wá kí ẹ̀yin kí ó wẹ ẹsẹ̀ yín, kí ẹ sì sinmi lábẹ́ igi níhìn-ín.
Muse huramantoanki ama zafa agafare manigsa hunenke'za osia tina afi'za eme tamina tamaga sese hiho.
5 Ẹ jẹ́ kí n wá oúnjẹ wá fún un yín, kí ẹ̀yin kí ó lè jẹ, kí ara sì tù yín, kí ẹ si tẹ̀síwájú ní ọ̀nà yín, nígbà tí ẹ ti yà ní ọ̀dọ̀ ìránṣẹ́ yín.” Wọn sì wí pé “Ó dára.”
Ana nehanage'na ne'zana uri'na eme taminena neneta manifru huteta kama vanarega vugahaze. Eri'za vahekamo'na noni'a kasante nantu ante nante'nagu ne'zana neteta vugahaze, hige'za knareki kema hanaza huo.
6 Abrahamu sì yára tọ Sara aya rẹ̀ lọ nínú àgọ́, ó wí pé, “Tètè mú òsùwọ̀n ìyẹ̀fun dáradára mẹ́ta kí o sì pò ó pọ̀, kí o sì ṣe oúnjẹ.”
Anage hazageno Abrahamu'a ame huno noma'afi umarerino amanage huno nenaro Serana asamine, Knare hu'nesnia flaua tagufa kevu urinka eme herunka bretia kro,
7 Abrahamu sì tún sáré lọ sí ibi agbo ẹran, ó sì mú ọmọ màlúù kan fún ìránṣẹ́ rẹ̀, ìránṣẹ́ náà sì tètè ṣè é.
nehuno Abrahamu'a agareno vuno bulimaka'afinti anenta afu ome aheno eri'za vahe'a eme amigeno, hantka huno erino ome kre'ne.
8 Ó sì mú wàrà àti mílíìkì àti màlúù tí ó ti pèsè, ó sì gbé síwájú wọn. Ó sì dúró nítòsí wọn lábẹ́ igi bí wọn ti ń jẹ ẹ́.
Abrahamu'a meme'mofo ami rima'a tagino eme ante nezmanteno, ko'ma kragefe'neama'a erino kaone eme ante nezamanteno tva'onte zafa agafare otino mani'nege'za ne'naze.
9 Wọn béèrè pé, “Sara aya rẹ ń kọ́?” Ó dáhùn pé, “Ó wà nínú àgọ́.”
Nene'za mani'ne'za Abrahamuna amanage hu'za antahige'naze, Negnaro Sera'a iga mani'ne? Hazageno Abrahamu'a huno, Ami seli nompi mani'ne.
10 Nígbà náà ni Olúwa wí fún un pé, “Èmi yóò sì tún padà tọ̀ ọ́ wá nítòótọ́ ní ìwòyí àmọ́dún; Sara aya rẹ yóò sì bí ọmọkùnrin kan.” Sara sì ń dẹtí gbọ́ láti ẹnu-ọ̀nà àgọ́ tí ó wà lẹ́yìn ọkùnrin náà.
Higeno anampinti mago'mo'a amanage huno hu'ne, Henka'a ama ana knare'ma esnuana negnaro Sera'a ne' mofavre kasente'nena egahue. Huno nehigeno agu'afi Sera'a seli no kasama'are mani'neno ana ke antahi'ne.
11 Abrahamu àti Sara sì ti di arúgbó, Sara sì ti kọjá àsìkò ìbímọ.
Abrahamuke ozafa tavava rakeno, kafu zanimo'a agaterege'ne. Sera'a mofavre antega osu'negeno avufagamo ampasagigeno mani'ne.
12 Nítorí náà, Sara rẹ́rìn-ín nínú ara rẹ̀ bí ó ti ń rò ó lọ́kàn rẹ̀ pé, “Lẹ́yìn ìgbà tí mo ti di arúgbó tán tí olúwa mi pẹ̀lú sì ti gbó jọ̀kújọ̀kú, èmi yóò ha tún lè bímọ?”
Ana higeno Sera'ma ana kema nentahino'a agu'afi kiza nereno amanage huno agesa antahi'ne, Nagrane ranimo'enena ozafa tavava renoanki, inankna huno mofavrea fore huraminogu nehie?
13 Nígbà náà ni Olúwa wí fún Abrahamu pé, “Kín ló dé tí Sara fi rẹ́rìn-ín tí ó sì wí pé, ‘Èmi yóò ha bímọ nítòótọ́, nígbà tí mo di ẹni ogbó tán?’
Ra Anumzamo'a amanage huno Abrahamuna asami'ne, Nahigeno Sera'a kizana nereno, tavavamo'na inankna huna mofavrea kasenteku hugeno nehie huno nehie?
14 Ǹjẹ́ ohunkóhun wà tí ó ṣòro jù fún Olúwa? Èmi ó padà tọ̀ ọ́ wá ní ìwòyí àmọ́dún, Sara yóò sì bí ọmọkùnrin.”
Nazamo Ra Anumzamofona amuho huntegahie? Anaga'a kafufina ama ana knare, Sera'a ne' mofavre kasente'nena egahie.
15 Ẹ̀rù sì ba Sara, ó sì sẹ́ pé òun kò rẹ́rìn-ín. Ṣùgbọ́n Olúwa wí fún un pé, “Dájúdájú ìwọ rẹ́rìn-ín.”
Sera'a amano vazigeno havige huno, A'o kizana ore nogenka nehane, huno higeno Anumzamo huno, A'o kagra kiza re'nane.
16 Nígbà tí àwọn ọkùnrin náà dìde láti máa lọ, wọn kọjú sí ọ̀nà Sodomu, Abrahamu sì sìn wọ́n dé ọ̀nà.
Ana tagufa vahe'mo'za oti'za vunaku nehu'za, Sodomu kuma me'nea kaziga zamavurga negageno (Abrahamu kantega ome zamatreteno enaku nevigeno),
17 Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Ǹjẹ́ èmi yóò ha pa ohun tí mo fẹ́ ṣe mọ́ fún Abrahamu bí?
Ra Anumzamo'a amanage hu'ne, Menima hunaku'ma nehua zana Abrahamu avurera eri frara okisue.
18 Dájúdájú Abrahamu yóò sá à di orílẹ̀-èdè ńlá àti alágbára, àti gbogbo orílẹ̀-èdè ayé ni a ó bùkún fún nípasẹ̀ rẹ̀.
Tamage huno Abrahamumpinti tusi'a hankavenentake vahe fore hu'za kuma ante'za manigahaze. Kokankoka mika kumate vahe'mo'za agripinti asomura erigahaze.
19 Nítorí tí èmi ti yàn án láti kọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ará ilé rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀, láti máa pa ọ̀nà Olúwa mọ nípa ṣíṣe olóòtítọ́ àti olódodo: kí Olúwa le è mú ìlérí rẹ̀ fún Abrahamu ṣẹ.”
Nagra Abrahamuna huhamprinte'noankino mofavre'ane, agehe'ine huvempa keni'a rempi huzamisige'za, mani fatgo hu'za nemaniza fatgoma huno refkoma hu avu'ava zana nehu'za Ra Anumzamo'na kante vanazegu huhamprinte'noe.
20 Olúwa sì wí pé, igbe Sodomu àti Gomorra pọ̀ púpọ̀ àti pé ẹ̀ṣẹ̀ wọn burú jọjọ.
Anante Ra Anumzamo'a amanage hu'ne, Sodomune Gomora vahe'mokizmia tusi'a kumizmimofo kezanke antahue, hankino kumi'zmimo'a tusi'a zampi mareri'ne.
21 “Èmi yóò sọ̀kalẹ̀ síbẹ̀ láti ṣe ìwádìí igbe tí ó dé sí etí ìgbọ́ mi nípa wọn, kí èmi sì mọ òtítọ́ tí ó wà níbẹ̀.”
E'ina hu'nagu kumi zmimofo zamagenkema antahi'noa zana tamagefi, urami'na ome zamage'na antahina hanue.
22 Àwọn ọkùnrin náà yí padà, wọ́n sì ń lọ sí ìhà Sodomu. Ṣùgbọ́n Abrahamu dúró níbẹ̀ níwájú Olúwa.
Anage nehige'ne tare netremokea rukrahe hu'ne Sodomu kaziga vu'na'e. Nevakeno Abrahamu'a anante Ra Anumzamo'ene oti'ne.
23 Nígbà náà ni Abrahamu súnmọ́ ọ̀dọ̀ Olúwa, ó sì wí pé, “Ìwọ yóò ha pa olódodo ènìyàn àti ènìyàn búburú run papọ̀ bí?”
Hagi Abrahamu'a erava'o huno Ra Anumzamofona anage huno antahige'ne, Ana kumapima fatgo vahe'ene, hazenke vahe'ene mani'nazana ana maka zamahe fanane hugahano?
24 “Bí ó bá ṣe pé ìwọ rí àádọ́ta olódodo nínú ìlú náà, ìwọ yóò ha run ún, ìwọ kì yóò ha dá ìlú náà sí nítorí àwọn àádọ́ta olódodo tí ó wà nínú rẹ̀ náà?
Hagi 50'a ana kumapima fatgo vahe'ma mani'nesazana, ana 50'a fatgo vahera zamahoke henka ana kumara zamahe fanane osugahano?
25 Kò jẹ́ rí bẹ́ẹ̀! Dájúdájú ìwọ kì yóò ṣe ohun tí ó jọ bẹ́ẹ̀, láti pa olódodo pẹ̀lú àwọn ènìyàn rere àti àwọn ènìyàn búburú. Dájúdájú, ìwọ kì yóò ṣe èyí tí ó tọ́ bi?”
E'i kagri kavu kvara omane'neankinka, havi vahe'ene fatgo vahe'enema zamahe fanane hananke'za havi vahe'ene, fatgo vahe'mo'zanena mago'zahu knazana e'origahaze. Mika mopafi vahe'mota mago'zanke hunka Kagra refko hunerantane.
26 Olúwa wí pé, “Bí mo bá rí àádọ́ta olódodo ní ìlú Sodomu, èmi yóò dá ìlú náà sí nítorí tiwọn.”
Higeno Anumzamo'a amanage hu'ne, Nagra'ma kesugeno'ma 50'a fatgo vahe'ma Sodomu ran kumapima mani'nesazana, ana mika rankumara zamagriku hu'na zamahe fanane osugahue.
27 Abrahamu sì tún tẹ̀síwájú pé, “Wò ó nísinsin yìí, níwọ̀n bí èmi ti ní ìgboyà láti bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ níwájú Olúwa, èmi ẹni tí í ṣe erùpẹ̀ àti eérú,
Anante Abrahamu'a mago'ane antahigeno, Nagra kugusopage hu'na tanefake vahe'mo'na Ra Anumzamokane naneke nehue.
28 bí ó bá ṣe pe olódodo márùndínláàádọ́ta ni ó wà nínú ìlú, ìwọ yóò ha pa ìlú náà run nítorí ènìyàn márùn-ún bí?” Olúwa dáhùn pé, “Èmi kì yóò pa ìlú náà run bí mo bá rí olódodo márùndínláàádọ́ta nínú rẹ̀.”
Hagi 50'a fatgo vahe mani'nesafinti 5fu'a vahe'ma omanisnagenka, knare ama ana mika rankumara zamazeri havizana hugahampi? Higeno Ra Anumzamo'a ete ke nona'a amanage hu'ne, Kesugenoma 45'a fatgo vahe'ma mani'nesage'na Nagra zamazeri havizana osugahue.
29 Òun sì tún wí lẹ́ẹ̀kan si pé, “Bí ó bá ṣe pé ogójì ni ń kọ́?” Olúwa sì tún wí pé, “Èmi kì yóò pa ìlú náà run bí mo bá rí olódodo ogójì nínú rẹ̀.”
Higeno Abrahamu'a mago'ene antahige'no, 40'a fatgo vahe mani'nesagenka knare zamahe fanane hugahano? Higeno Ra Anumzamo'a ete ke nona'a hunteno, Kesugeno 40'a fatgo vahe'ma mani'nesage'na, Nagra zamazeri havizana osugahue.
30 Abrahamu sì tún bẹ Olúwa pé, “Kí Olúwa má ṣe bínú, ṣùgbọ́n èmi yóò sọ̀rọ̀. Bí ó bá ṣe pé ọgbọ̀n ni a rí níbẹ̀ ń kọ́?” Olúwa dáhùn pé, “Bí mó bá rí ọgbọ̀n, èmi kì yóò pa ìlú run.”
Hagi Abrahamu'a mago'ane amanage hu'ne, Ra Anumzamoka mago'ane kea hugahuanki krimpa aheonanto, 30'a fatgo vahe mani'nesagenka knare zamazeri havizana hugahano? Higeno Ra Anumzamo'a ke nona'a amanage hu'ne, Kesugeno'ma 30'a fatgo vahe'ma mani'nesage'na, Nagra zamazeri havizana osugahue.
31 Abrahamu wí pé, “Níwọ́n bí mo ti ní ìgboyà láti bá Olúwa sọ̀rọ̀ báyìí, jẹ́ kí n tẹ̀síwájú. Bí o bá ṣe pé olódodo ogún péré ni ó wà nínú ìlú náà ń kọ́?” Olúwa sì dáhùn pé, “Èmi kì yóò pa á run nítorí ogún ènìyàn náà.”
Higeno Abrahamu'a mago'ene hanave e'nerino Ra Anumzamofo antahige'ne, 20'a fatgo vahe'ma mani'nesagenka knare zamahe fanane hugahano? Higeno Ra Anumzamo'a kenona'a amanage hu'ne, Kesugenoma 20'a fatgo vahe'ma mani'nesage'na Nagra zamazeri havizana osugahue.
32 Abrahamu sì wí pé, “Jọ̀wọ́ má ṣe bínú Olúwa. Jẹ́ kí ń béèrè lẹ́ẹ̀kan si. Bí ó bá ṣe pé ènìyàn mẹ́wàá ni ó jẹ́ olódodo ń kọ́?” Olúwa wí pé, “Nítorí ènìyàn mẹ́wàá náà, èmi kì yóò pa á run.”
Higeno Abrahamu'a anage hu'ne, Ra Anumzamoka mago'ene kantahigegahuanki krimpa aheonanto, 10ni'a fatgo vahe'ma mani'nesagenka knare zamahe fanane hugahano? Higeno Ra Anumzamo'a ke nona'a amanage hu'ne, Kesanugenoma 10ni'a fatgo vahe'ma mani'nesage'na Nagra zamazeri havizana osugahue.
33 Olúwa sì bá tirẹ̀ lọ, nígbà tí ó bá Abrahamu sọ̀rọ̀ tán, Abrahamu sì padà sílé.
Hagi Anumzamo'ma Abrahamu'ene keaga huvagama nereno'a atreno vigeno, Abrahamu'a kuma'arega ete vu'ne.

< Genesis 18 >