< Genesis 18 >

1 Olúwa sì farahan Abrahamu nítòsí àwọn igi ńlá Mamre, bí ó ti jókòó ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ rẹ̀, nígbà tí ọjọ́-kanrí tí oòrùn sì mú.
Mamre munna gangpi phung komma chun Pakai chu Abraham henga ahung kilah in ahi. Nikhat hi nichangsat pettah hin Abraham chu aponbuh maiya ana touvin ahi.
2 Abrahamu gbójú sókè, ó sì rí àwọn ọkùnrin mẹ́ta tí wọn dúró nítòsí rẹ̀. Nígbà tí ó rí wọn, ó sáré láti lọ pàdé wọn, ó sì tẹríba bí ó ti ń kí wọn.
Ama ahung dahdoh in ahile akomma mithum ana din amun ahi. Amaho chu amu phat in ama alhai jel in amaho lemnan tol ah abohkhup in ahi.
3 Ó wí pé, “Bí mo bá rí ojúrere yín Olúwa mi, ẹ má ṣe lọ láì yà sọ́dọ̀ ìránṣẹ́ yín.
Chuin Abraham'in “Ka Pakai,” tin adonbut in, “Nanghon pha nasah uleh phat chomkhat naki ngah thei diu ham.
4 Ẹ jẹ́ kí a bu omi díẹ̀ wá kí ẹ̀yin kí ó wẹ ẹsẹ̀ yín, kí ẹ sì sinmi lábẹ́ igi níhìn-ín.
Nakeng sil na ding'u kahin choi kah in hiche thing limnoiya hin ana kicholdo ta diu vin.
5 Ẹ jẹ́ kí n wá oúnjẹ wá fún un yín, kí ẹ̀yin kí ó lè jẹ, kí ara sì tù yín, kí ẹ si tẹ̀síwájú ní ọ̀nà yín, nígbà tí ẹ ti yà ní ọ̀dọ̀ ìránṣẹ́ yín.” Wọn sì wí pé “Ó dára.”
Chule nang hon na lhacha pa hi khoto na neitah a nei hungvil ngal'u ahi leh na kholyin na mano masang in na tha kido na ding un naneh ding'u them khat nahin gon peh ing nge, ama hon aphai, nasei bang chun hin bol tan ati uve.
6 Abrahamu sì yára tọ Sara aya rẹ̀ lọ nínú àgọ́, ó wí pé, “Tètè mú òsùwọ̀n ìyẹ̀fun dáradára mẹ́ta kí o sì pò ó pọ̀, kí o sì ṣe oúnjẹ.”
Hichun Abraham chu apon buh kom langa alhai jel'in Sarah kom ah asei tan ahi, “Kinloi tah in changbong ate na dimthum tedoh in lang twi to mehnang in, chule changlhah hin keng loi tem in,” aga tin ahi.
7 Abrahamu sì tún sáré lọ sí ibi agbo ẹran, ó sì mú ọmọ màlúù kan fún ìránṣẹ́ rẹ̀, ìránṣẹ́ náà sì tètè ṣè é.
Hichun Abraham'in gancha ho kivah na lang ajon in bongnou athao pen asohte ho apen, gangtah in ahin hon sah in ahi.
8 Ó sì mú wàrà àti mílíìkì àti màlúù tí ó ti pèsè, ó sì gbé síwájú wọn. Ó sì dúró nítòsí wọn lábẹ́ igi bí wọn ti ń jẹ ẹ́.
An neh ding ho amin phat in Abraham'in bongnoi ha le bongnoi toh chule bongnou sa ahon u-chu amaho angsung ah aneh diuvin aga lui peh in amaho anneh laisen ama jong thinglim a chun ading jinge.
9 Wọn béèrè pé, “Sara aya rẹ ń kọ́?” Ó dáhùn pé, “Ó wà nínú àgọ́.”
Chuin ama hon Abraham jah'a “Na loinu Sarah hoilam a um aham?” atiu leh Abraham'in ponbuh sunga aum nai ati.
10 Nígbà náà ni Olúwa wí fún un pé, “Èmi yóò sì tún padà tọ̀ ọ́ wá nítòótọ́ ní ìwòyí àmọ́dún; Sara aya rẹ yóò sì bí ọmọkùnrin kan.” Sara sì ń dẹtí gbọ́ láti ẹnu-ọ̀nà àgọ́ tí ó wà lẹ́yìn ọkùnrin náà.
Chuin amaho lah a khat chun aseiyin, “Keima hi khovei tulai phat mama le kahung ki nungle kit ding ahi, vetan hiche phatteng chule na inneipi Sarah khun chapa khat ana hin ding ahi,” ati chu anunga ponbuh sunglam a um Sarah chun angai lhin ahi.
11 Abrahamu àti Sara sì ti di arúgbó, Sara sì ti kọjá àsìkò ìbímọ.
Abraham le Sarah chu atahsa kum lhon chu atam gel lhon tan, chule Sarah jong nao nei phat kum akhel ahi tai.
12 Nítorí náà, Sara rẹ́rìn-ín nínú ara rẹ̀ bí ó ti ń rò ó lọ́kàn rẹ̀ pé, “Lẹ́yìn ìgbà tí mo ti di arúgbó tán tí olúwa mi pẹ̀lú sì ti gbó jọ̀kújọ̀kú, èmi yóò ha tún lè bímọ?”
Hichun Sarah guhthim in ama le ama aki nuisat in hitin aseiye, “Iti hithei ding ham, kei tobang aching sa numeiyin kipana thilpha kamu ding ham, ka jipa jeng jong akum atam lheh tai,” ati.
13 Nígbà náà ni Olúwa wí fún Abrahamu pé, “Kín ló dé tí Sara fi rẹ́rìn-ín tí ó sì wí pé, ‘Èmi yóò ha bímọ nítòótọ́, nígbà tí mo di ẹni ogbó tán?’
Pathen in Abraham jah achun aseiye, “Ipi dinga Sarah khu nuiya ka teh nunga keiman cha kanei tahbeh mong ding hi nam,” ati ham?
14 Ǹjẹ́ ohunkóhun wà tí ó ṣòro jù fún Olúwa? Èmi ó padà tọ̀ ọ́ wá ní ìwòyí àmọ́dún, Sara yóò sì bí ọmọkùnrin.”
Pakai Pathen ading'a ipi ahahsa umham? keima khovei tulai phat na kahung kit ding chule Sarah in cha pasal khat anei ding ahi.”
15 Ẹ̀rù sì ba Sara, ó sì sẹ́ pé òun kò rẹ́rìn-ín. Ṣùgbọ́n Olúwa wí fún un pé, “Dájúdájú ìwọ rẹ́rìn-ín.”
Chuphat in Sarah chu atija tan hichun Sarah in aseilep tan, “Keima ka nuipoi” atin ahin la, “Pathen in adonbut in nangma na nui nai,” ati.
16 Nígbà tí àwọn ọkùnrin náà dìde láti máa lọ, wọn kọjú sí ọ̀nà Sodomu, Abrahamu sì sìn wọ́n dé ọ̀nà.
Hichun pasal thum hochu an aneh jou un ading doh un Sodom lang chu galdot un, ama hon adalha uvin, Abraham chu amaho thah doh ding tin lampi gei aga kilhonpin ahi.
17 Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Ǹjẹ́ èmi yóò ha pa ohun tí mo fẹ́ ṣe mọ́ fún Abrahamu bí?
Pathen chun aseiye, “Keiman katoh gon hohi Abraham kom a kasei lou ding ham?” ati.
18 Dájúdájú Abrahamu yóò sá à di orílẹ̀-èdè ńlá àti alágbára, àti gbogbo orílẹ̀-èdè ayé ni a ó bùkún fún nípasẹ̀ rẹ̀.
Ajeh chu Abraham chu len tah le nam hattah chule vannoi ja nam jouse Abraham jeh a phatthei chang ding ahi ngal'in,
19 Nítorí tí èmi ti yàn án láti kọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ará ilé rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀, láti máa pa ọ̀nà Olúwa mọ nípa ṣíṣe olóòtítọ́ àti olódodo: kí Olúwa le è mú ìlérí rẹ̀ fún Abrahamu ṣẹ.”
Chule achapate le ama ban a ainsung mi aman thu apeh a, chutia chu adih abol theiyu va, thu adih a atan thei na dinguva Pakai lampi ajui thei uva, chuteng le Pakaiyin Abraham chung chang'a akitep nasa chu ahin molso theina dinga ama hi kilheng doh ahiti la ka henan,” ati.
20 Olúwa sì wí pé, igbe Sodomu àti Gomorra pọ̀ púpọ̀ àti pé ẹ̀ṣẹ̀ wọn burú jọjọ.
Hichun Pathen in Abraham ahoulimpi in “Sodom le Gomorrah douna thu kisei asangval tan chule achonset nau jong ase val tai,” ati.
21 “Èmi yóò sọ̀kalẹ̀ síbẹ̀ láti ṣe ìwádìí igbe tí ó dé sí etí ìgbọ́ mi nípa wọn, kí èmi sì mọ òtítọ́ tí ó wà níbẹ̀.”
Keima che suh ing kating ka henga thu hung kisei dungjuiya hi abol cheh'u ham, ahilou ham gapho chen inge,” ati.
22 Àwọn ọkùnrin náà yí padà, wọ́n sì ń lọ sí ìhà Sodomu. Ṣùgbọ́n Abrahamu dúró níbẹ̀ níwájú Olúwa.
Hichun miho chu chukom akon in aki heiyun Sodom lang chu ajon un ache tauve, ahin lah Abraham chu Pakai masanga chun ading chah den jing in ahi.
23 Nígbà náà ni Abrahamu súnmọ́ ọ̀dọ̀ Olúwa, ó sì wí pé, “Ìwọ yóò ha pa olódodo ènìyàn àti ènìyàn búburú run papọ̀ bí?”
Abraham'in Pathen chu anailut in hitin aseiye, “Nangman michonpha atheng chule mi phalou agilouho aboncha nasuh mang tha ding ham,” ati.
24 “Bí ó bá ṣe pé ìwọ rí àádọ́ta olódodo nínú ìlú náà, ìwọ yóò ha run ún, ìwọ kì yóò ha dá ìlú náà sí nítorí àwọn àádọ́ta olódodo tí ó wà nínú rẹ̀ náà?
Ijem tin khopi sunga chun michonpha som nga bang um ta le, asunga michonpha som nga ho jal'a jong chu akhomun chu khen dehlou hela nasuh mang jeng ding ham?
25 Kò jẹ́ rí bẹ́ẹ̀! Dájúdájú ìwọ kì yóò ṣe ohun tí ó jọ bẹ́ẹ̀, láti pa olódodo pẹ̀lú àwọn ènìyàn rere àti àwọn ènìyàn búburú. Dájúdájú, ìwọ kì yóò ṣe èyí tí ó tọ́ bi?”
Nang dinga hitobang thil nabol a, michonpha le migilou agoma natha cheh a, michonpha le migilou akibah ding chu bolda hel jengle chun kati! Leiset thutan pan adih a atan lou ding ham?” atile.
26 Olúwa wí pé, “Bí mo bá rí àádọ́ta olódodo ní ìlú Sodomu, èmi yóò dá ìlú náà sí nítorí tiwọn.”
Hichun Pathen'in adonbut in, “keiman mi somnga thudih thilpha bol Sodom khopi a kamu doh theile, amaho jal'a chu khopi kahuhdoh ding ahi.”
27 Abrahamu sì tún tẹ̀síwájú pé, “Wò ó nísinsin yìí, níwọ̀n bí èmi ti ní ìgboyà láti bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀ níwájú Olúwa, èmi ẹni tí í ṣe erùpẹ̀ àti eérú,
Hichun Abraham'in asei kit in, “Ka Pakai nangman neiphal peh thei dingle kasei ban ho kajom nom in keima vang bohse vutvai tobang kahin,
28 bí ó bá ṣe pe olódodo márùndínláàádọ́ta ni ó wà nínú ìlú, ìwọ yóò ha pa ìlú náà run nítorí ènìyàn márùn-ún bí?” Olúwa dáhùn pé, “Èmi kì yóò pa ìlú náà run bí mo bá rí olódodo márùndínláàádọ́ta nínú rẹ̀.”
Ijem tin mi somli le nga tobang chonpha mitheng mi som nga sanga lhomjo namu le amaho jeh'a chu khopi hi nasuh mang ding ham, mi nga lhahsam jeh chun, Pathenin adonbut in, Keiman hiche khopi a hi mi som li le nga kamu doh jouva ahile sumang ponge,” ati.
29 Òun sì tún wí lẹ́ẹ̀kan si pé, “Bí ó bá ṣe pé ogójì ni ń kọ́?” Olúwa sì tún wí pé, “Èmi kì yóò pa ìlú náà run bí mo bá rí olódodo ogójì nínú rẹ̀.”
Hichun Abraham'in adeichat angaichat avel in aseiyin, “Ijem tin mi som li bou umta le,” atin chuin Pakaiyin ahoulimpi kit in, “Keiman amaho mi somli jeh a chu kasuh manglou hel ding ahi,” ati.
30 Abrahamu sì tún bẹ Olúwa pé, “Kí Olúwa má ṣe bínú, ṣùgbọ́n èmi yóò sọ̀rọ̀. Bí ó bá ṣe pé ọgbọ̀n ni a rí níbẹ̀ ń kọ́?” Olúwa dáhùn pé, “Bí mó bá rí ọgbọ̀n, èmi kì yóò pa ìlú run.”
Ka Pakai lungset tah in lung hanglou jenin, Abraham atao kit leovin, neiphal peh theile chun kasei nom na laiye, Ijemtin mi som thum muta le chun,” atile Pakai Pathen in ahoulimpi in “Keiman mi somthum hijong le ka suhmang lou ding ahi,” ati.
31 Abrahamu wí pé, “Níwọ́n bí mo ti ní ìgboyà láti bá Olúwa sọ̀rọ̀ báyìí, jẹ́ kí n tẹ̀síwájú. Bí o bá ṣe pé olódodo ogún péré ni ó wà nínú ìlú náà ń kọ́?” Olúwa sì dáhùn pé, “Èmi kì yóò pa á run nítorí ogún ènìyàn náà.”
Hichun Abraham'in aseikit in, “Nangman neiphal peh theile ka thusei hi ka jom nome, Ijem tin mi som ni hi jongle atile,” Pakaiyin adonbut in, “Mi somni kamu jongle ka suhmang lou ding ahi,” ati.
32 Abrahamu sì wí pé, “Jọ̀wọ́ má ṣe bínú Olúwa. Jẹ́ kí ń béèrè lẹ́ẹ̀kan si. Bí ó bá ṣe pé ènìyàn mẹ́wàá ni ó jẹ́ olódodo ń kọ́?” Olúwa wí pé, “Nítorí ènìyàn mẹ́wàá náà, èmi kì yóò pa á run.”
Abraham'in achaina in asei peh tan, “Ka Pakai Pathen nei lung han hih beh in lang, khatvei neisei sah kit le tia katao ahi, mi som muta le chun” hichun Pathen in aseiye, “Mi som kamu doh jongle kasuh manglou ding ahi,” ati.
33 Olúwa sì bá tirẹ̀ lọ, nígbà tí ó bá Abrahamu sọ̀rọ̀ tán, Abrahamu sì padà sílé.
Hichun Abraham henga athusei dingin aboncha aseisoh phat'in Pakai chu ache tai; Abraham vang chu a in mun lam a ahung kile kit tai.

< Genesis 18 >