< Genesis 15 >

1 Lẹ́yìn èyí, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Abramu wá lójú ìran pé, “Abramu má ṣe bẹ̀rù. Èmi ni ààbò rẹ, Èmi sì ni èrè ńlá rẹ.”
Sabara gahıle İbramıs dyaguyne Rəbbee inəxdun cuvab eyhe: – Qıməyq'ən İbram. Ğu havacesda Zı vorna, Zı vas geed xədın mukaafat heles.
2 Ṣùgbọ́n Abramu wí pé, “Olúwa Olódùmarè, kí ni ìwọ yóò fi fún mi níwọ̀n ìgbà tí èmi kò bímọ, Elieseri ará Damasku ni yóò sì jogún mi,”
İbramee uvhuyn: – Zas, yizda Xudaavanda Rəbb, hucoone heles? Uşax zaqa deşin, yizın kar Damask şahareençene Eliezerıs axvas.
3 Abramu sì tún tẹ̀síwájú pé, “Ìwọ kò fún mi ní ọmọ, nítorí náà ẹrú nínú ilé mi sì ni yóò jẹ́ àrólé mi.”
Ğu zas uşax hidevul-alla, ina yizda xaana insan yizda varis ixhes.
4 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tún tọ̀ ọ́ wá pé, “Ọkùnrin yìí kọ́ ni yóò jẹ́ àrólé rẹ bí kò ṣe ọmọ tí ìwọ bí fúnra rẹ̀ ni yóò jẹ́ àrólé rẹ.”
Rəbbee mang'us inəxdun alidghıniy qele: – Mana yiğna varis ixhes deş, yiğna varis vake g'adıyn uşax ixhes.
5 Olúwa sì mú Abramu jáde sí ìta ó sì wí fún un pé, “Gbé ojú sókè sí ọ̀run kí o sì ka àwọn ìràwọ̀ bí ó bá ṣe pé ìwọ le è kà wọ́n.” Ó sì wí fun un pé, “Nítorí náà, báyìí ni irú-ọmọ rẹ yóò rí.”
Qiyğa Rəbbee İbram g'aqa qığavu eyhen: – Xəybışiqa ilekke, xənebı qətqəs əxəxhee qətqe. Vake g'abına nasılıb hamanimee xəbna vuxhes.
6 Abramu gba Olúwa gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un.
İbramee Rəbbee uvhuynçilqa inyam ha'a, mançil-alla Rəbbeyir mana qorkuna insan xhinne hı'sab ha'a.
7 Ó sì tún wí fún un pé, “Èmi ni Olúwa tí ó mú ọ jáde láti Uri ti Kaldea láti fún ọ ní ilẹ̀ yìí láti jogún.”
Rəbbee İbramık'le eyhen: – Vas in cigabı helesva, ğu Xaldeyaaşine Ur şahareençe qığavhuna Rəbb Zı vorna.
8 Ṣùgbọ́n Abramu wí pé, “Olúwa Olódùmarè, báwo ni mo ṣe lè mọ̀ pé ilẹ̀ náà yóò jẹ́ ohun ìní mi?”
İbramee Rəbbike qidghın ha'an: – Yizda Xudaavanda Rəbb, nençene zak'le ats'axhes, in cigabı yizınbı ixhesva?
9 Nítorí náà, Olúwa wí fún un pé, “Mú abo màlúù, ewúrẹ́ àti àgbò ọlọ́dún mẹ́ta mẹ́ta wá, àti àdàbà kan àti ọmọ ẹyẹlé kan.”
Rəbbee mang'uk'le eyhen: – Yizdemee sa vuç'e, sa ts'e, sayib g'arg able. Adıyne gırgınçiqa xhebılle sen ixhecen. Sayib qı'nerkeyiy k'urk'uray able.
10 Abramu sì mú gbogbo nǹkan wọ̀nyí wá, ó sì là wọ́n sí méjì méjì, ó sì fi ẹ̀là èkínní kọjú sí èkejì, ṣùgbọ́n kò la àwọn ẹyẹ ní tiwọn.
İbramee manbı gırgınbı gyaat'anbı. Qiyğad q'öne cigeeqa qı'ı sana sançine hiqa giyxhe. Saccu şit'yar mang'vee q'öne cigeeqa qidya'a.
11 Àwọn ẹyẹ igún sì ń wá sórí òkú ẹran náà, Abramu sì ń lé wọn.
Çurunulqa qadıyn yırtıciy şit'yar İbramee g'e'eedaşenbı.
12 Bí oòrùn ti ń wọ̀, Abramu sùn lọ fọnfọn, òkùnkùn biribiri tí ó kún fún ẹ̀rù sì bò ó.
Verığ k'yooçene gahıl İbram k'orane nik'eeqa ayk'an. Mang'ulqa sayangaba qəq'ənasda miç'axiyvalla t'yoose.
13 Nígbà náà ni Olúwa wí fún Abramu pé, “Mọ èyí dájú pé, irú-ọmọ rẹ yóò ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àjèjì, wọn ó sì sọ wọn di ẹrú, wọn ó sì pọ́n wọn lójú fún irinwó ọdún.
Rəbbee İbramık'le inəxüd eyhe: – İn vak'le ats'axhe, yiğna nasıl menne ölkee dağamiyvaleeyiy nukariyvalee yoq'ud vəş senna vuxhes.
14 Ṣùgbọ́n orílẹ̀-èdè náà tí wọn yóò máa sìn, ni èmi ó dá lẹ́jọ́, lẹ́yìn náà ni wọn ó sì jáde pẹ̀lú ọrọ̀ púpọ̀.
Manbışike nukarar hav'uyne milletıke Zı hı'sab qeqqas. Mançile qiyğa yiğne nasılınbı mançe geed xətta karaka qığeepç'es.
15 Ṣùgbọ́n ìwọ yóò tọ àwọn baba rẹ lọ ni àlàáfíà, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ yóò sì di arúgbó kí a tó gbé ọ sin.
Ğunab xıliyna ı'mı'r hav'u, q'əsvalee qik'as.
16 Ní ìran kẹrin àwọn ìran rẹ yóò padà wá sí ibi. Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ará Amori kò ì tí ì kún òsùwọ̀n.”
Emorğançenbışin bınahbı inçe ğadara'asınbı xhinne geed qideetxhava, yiğna yoq'ub'esda nasıl inyaqa savk'alas.
17 Nígbà tí oòrùn wọ̀ tí ilẹ̀ sì ṣú, ìkòkò iná tí ń ṣèéfín àti ọwọ́ iná sì ń kọjá láàrín ẹ̀là ẹran náà.
Verığ k'yooçu xəm quvxhayng'a, kuma q'ığəəna tanduriy ts'abı q'ığəənə yalav q'öna q'ı'iyne həyvanaaşine yı'q'neençe ılğooç'e.
18 Ní ọjọ́ náà gan an ni Olúwa dá májẹ̀mú pẹ̀lú Abramu, ó sì wí pé, “Àwọn ìran rẹ ni èmi yóò fi ilẹ̀ yìí fún, láti odò Ejibiti dé odò ńlá Eufurate:
Mane yiğıl Rəbbee İbramıka hav'uyne mugaavilee inəxüd eyhe: – Zı Misirne damayle xənne Fəratne damaysqameen ine milletbışin:
19 ilẹ̀ àwọn ará Keni, àti ti ará Kenissiti, àti ará Kadmoni,
Genbışin, Genizbışin, Gadmonbışin, Q'etbışin, Perizbışin, Rafabışin, Emorbışin, Kana'anbışin, Girgaşbışin, Yevusbışin cigabı yiğne nasılıs heles.
20 àti ti ará Hiti, àti ti ará Peresi, àti ti ará Refaimu.
21 Àti ti ará Amori, àti ti ará Kenaani, àti ti ará Girgaṣi àti ti ará Jebusi.”

< Genesis 15 >