< Genesis 11 >
1 Lẹ́yìn náà, gbogbo àgbáyé sì ń sọ èdè kan ṣoṣo.
Maꞌahulu na, basa atahori sia raefafoꞌ ia olaꞌ rendiꞌ a dedꞌeat esaꞌ a.
2 Bí àwọn ènìyàn ṣe ń tẹ̀síwájú lọ sí ìhà ìlà-oòrùn, wọ́n rí pẹ̀tẹ́lẹ̀ kan ní ilẹ̀ Ṣinari, wọ́n sì tẹ̀dó síbẹ̀.
Ruma sangga lali risiꞌ seriꞌ rulu, losa rae tetuꞌ esa sia Sinear, de ara leo sia naa.
3 Wọ́n sì wí fún ara wọn pé, “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a mọ bíríkì kí a sì sún wọ́n jìnà.” Bíríkì ni wọ́n ń lò ní ipò òkúta, àti ọ̀dà ilẹ̀ tí wọn ń lò láti mú wọn papọ̀ dípò ẹfun (òkúta láìmù tí wọ́n fi ń ṣe símẹ́ńtì àti omi).
Basa se rala hara esa rae, “We! Toronooꞌ re! Ima fo tafefela nusa monaeꞌ esa. Ata musi tao fatu mbilas, fo lalangge losa manggatee. Basa fo ata lutu fatu mbilas naa ra no ter, fo tariri ume naruꞌ esa, tonggo na losa lalai. Naa fo, ata hambu naraꞌ ma dadꞌi leo monaeꞌ sa nda banggi-bꞌanggiꞌ sa.”
4 Nígbà náà ni wọ́n wí pé, “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a tẹ ìlú kan dó fún ara wa, kí a sì kọ́ ilé ìṣọ́ kan tí yóò kan ọ̀run, kí a ba à lè ní orúkọ, kí a má sì tú káàkiri sórí gbogbo ilẹ̀ ayé.”
5 Ṣùgbọ́n, Olúwa sọ̀kalẹ̀ láti wo ìlú àti ilé ìṣọ́ tí àwọn ènìyàn náà ń kọ́.
Boe ma LAMATUALAIN nema mete sobꞌa nusaꞌ naa, no ume naruꞌ fo rafefelaꞌ a.
6 Olúwa wí pé, “Bí àwọn ènìyàn bá ń jẹ́ ọ̀kan àti èdè kan tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí í ṣe iṣẹ́ yìí, kò sí ohun tí wọ́n gbèrò tí wọn kò ní le ṣe yọrí.
Ana olaꞌ nae, “Basa atahori ia ra, leo esa, ma dedꞌeat esa. Saa fo ara taoꞌ a ia, feꞌe fefeuꞌ. Mbila-fini esaꞌ, mete ma basa se raꞌabꞌue reu esa onaꞌ ia, naa, ara bisa tao sudꞌi a saa.
7 Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a sọ̀kalẹ̀ lọ, kí a da èdè wọn rú kí èdè wọn má ba à yé ara wọn mọ́.”
Malole lenaꞌ Hita onda fo tao se esa-esaꞌ no dedꞌea na, fo esa nda nahine esa dedꞌea na saꞌ boe.”
8 Olúwa sì tú wọn ká sórí ilẹ̀ gbogbo, wọ́n sì ṣíwọ́ ìlú náà tí wọn ń tẹ̀dó.
Boe ma Lamatualain onda tao tasibu dedꞌea nara. No taꞌo naa, Ana tao atahori ra sea-saranggaa risiꞌ basa mamanaꞌ sia raefafoꞌ a. Ara o nda rafefela rakandoo nusaꞌ naa saꞌ ena.
9 Ìdí èyí ni a fi pè é ní Babeli nítorí ní ibẹ̀ ni Olúwa ti da èdè gbogbo ayé rú. Olúwa tí sì tú àwọn ènìyàn ká sí gbogbo orí ilẹ̀ ayé.
Naa de, ara babꞌae nusaꞌ naa, Babel, (lii na naeꞌ a onaꞌ dedꞌeat esa, fo sosoa na ‘tabꞌanganga’), huu LAMATUALAIN tao tasibꞌu dedꞌea nara, ma fee se sea-saranggaa sudꞌiꞌ a bee reu sia raefafoꞌ a.
10 Wọ̀nyí ni ìran Ṣemu. Ọdún méjì lẹ́yìn ìkún omi, tí Ṣemu pé ọgọ́rùn-ún ọdún ni ó bí Arfakṣadi.
Ia, Sem tititi-nonosi nara. Leleꞌ oe mandali monaeꞌ a naloeꞌ too rua ena, nandaa no Sem too natun esa ma, ana hambu ana touꞌ esa, naran Arpaksad.
11 Lẹ́yìn tí ó bí Arfakṣadi, Ṣemu tún wà láààyè fún ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ọdún, ó sì bí àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.
Basa ma, Sem feꞌe nasodꞌa too natun lima, de hambu seluꞌ ana touꞌ ma inaꞌ fai.
12 Nígbà tí Arfakṣadi pé ọdún márùndínlógójì ni ó bí Ṣela.
Arpaksad too telu nulu lima ma, ana hambu ana touꞌ esa, naran Sela.
13 Arfakṣadi sì wà láààyè fún ọdún mẹ́tàlénírinwó lẹ́yìn tí ó bí Ṣela, ó sì bí àwọn ọmọbìnrin àti àwọn ọmọkùnrin mìíràn.
Basa ma, Arpaksad feꞌe nasodꞌa too natun haa telu, de hambu seluꞌ ana touꞌ ma inaꞌ fai.
14 Nígbà tí Ṣela pé ọmọ ọgbọ̀n ọdún ni ó bí Eberi.
Sela too telu nulu ma, ana hambu ana touꞌ esa, naran Eber.
15 Ṣela sì wà láààyè fún ọdún mẹ́tàlénírinwó lẹ́yìn tí ó bí Eberi tán, ó sì bí àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.
Basa ma, Sela feꞌe nasodꞌa too natun haa telu, de hambu seluꞌ ana touꞌ ma inaꞌ fai.
16 Eberi sì jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n, ó sì bí Pelegi.
Eber too telu nulu haa ma, ana hambu ana touꞌ esa, naran Pelek.
17 Eberi sì wà láààyè fún irinwó ọdún ó lé ọgbọ̀n lẹ́yìn tí ó bí Pelegi, ó sì bí àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.
Basa ma, Eber feꞌe nasodꞌa seluꞌ too natun haa telu nulu, de ana hambu seluꞌ ana touꞌ ma inaꞌ fai.
18 Nígbà tí Pelegi pé ọmọ ọgbọ̀n ọdún ni ó bí Reu.
Pelek too telu nulu ma, ana hambu ana touꞌ esa, naran Rehu.
19 Pelegi sì tún wà láààyè fún igba ọdún ó lé mẹ́sàn-án lẹ́yìn tí ó bí Reu, ó sì bí àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.
Basa ma, Pelek nasodꞌa seluꞌ too natun rua sio, de hambu seluꞌ ana touꞌ ma inaꞌ fai.
20 Nígbà tí Reu pé ọdún méjìlélọ́gbọ̀n ni ó bí Serugu.
Rehu too telu nulu rua ma, ana hambu ana touꞌ esa, naran Seruk.
21 Reu tún wà láààyè lẹ́yìn tí ó bí Serugu fún igba ọdún ó lé méje, ó sì bí àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin mìíràn.
Basa ma, Rehu feꞌe nasodꞌa too natun rua hitu, de hambu seluꞌ ana touꞌ ma inaꞌ fai.
22 Nígbà tí Serugu pé ọmọ ọgbọ̀n ọdún ni ó bí Nahori.
Seruk too telu nulu ma, ana hambu ana touꞌ esa, naran Nahor.
23 Serugu sì wà láààyè fún igba ọdún lẹ́yìn tí ó bí Nahori, ó sì bí àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.
Basa ma, Seruk feꞌe nasodꞌa seluꞌ too natun rua, de hambu seluꞌ ana touꞌ ma inaꞌ fai.
24 Nígbà tí Nahori pé ọmọ ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n, ó bí Tẹra.
Nahor too rua nulu sio ma, ana hambu ana touꞌ esa, naran Tera.
25 Nahori sì wà láààyè fún ọdún mọ́kàn dín lọ́gọ́fà lẹ́yìn ìbí Tẹra, ó sì bí àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin mìíràn.
Basa ma, Nahor feꞌe nasodꞌa seluꞌ too natun esa sana hulu sio, de hambu seluꞌ ana touꞌ ma inaꞌ fai.
26 Lẹ́yìn tí Tẹra pé ọmọ àádọ́rin ọdún ó bí Abramu, Nahori àti Harani.
Tera too hitu nulu lena ma, ana hambu ana touꞌ telu ena, nara nara Abram, Nahor, ma Haran.
27 Wọ̀nyí ni ìran Tẹra. Tẹra ni baba Abramu, Nahori àti Harani. Harani sì bí Lọti.
Ia, Tera tititi-nonosi nara. Tera ana nara, Abram, Nahor, ma Haran. Haran hambu ana touꞌ esa, naran Lot.
28 Harani sì kú ṣáájú Tẹra baba rẹ̀ ní ilẹ̀ ìbí rẹ̀ ní Uri ti ilẹ̀ Kaldea.
Haran mate mia kambo na, naran Ur, sia atahori Kasdim ra rae na. Ana mate te, ama na Tera feꞌe masodꞌaꞌ.
29 Abramu àti Nahori sì gbéyàwó. Orúkọ aya Abramu ni Sarai, nígbà tí aya Nahori ń jẹ́ Milka, tí ṣe ọmọ Harani. Harani ni ó bí Milka àti Iska.
Abram sao na Sarai. Nahor sao nala Haran ana feto na, Milka. Haran o ma ana touꞌ esa, naran Yiska.
30 Sarai sì yàgàn, kò sì bímọ.
Te Sarai nda mana bꞌonggiꞌ sa.
31 Tẹra sì mú ọmọ rẹ̀ Abramu àti Lọti ọmọ Harani, ọmọ ọmọ rẹ̀, ó sì mú Sarai tí i ṣe aya ọmọ rẹ̀. Abramu pẹ̀lú gbogbo wọn sì jáde kúrò ní Uri ti Kaldea láti lọ sí ilẹ̀ Kenaani. Ṣùgbọ́n nígbà tí wọn dé Harani wọ́n tẹ̀dó síbẹ̀.
Lao esa, Tera nendi ana na Abram, ana feto feu na Sarai, ma umbu na Lot, de ara lao hela kambo Ur. Ara rae reu sia rae Kanaꞌan, te losa kambo Haran ma, ara leo reuꞌ a naa.
32 Nígbà tí Tẹra pé ọmọ igba ọdún ó lé márùn-ún ni ó kú ní Harani.
Tera too natun rua lima ma, ana mate sia naa.