< Genesis 10 >

1 Èyí ni ìran àwọn ọmọ Noa: Ṣemu, Hamu àti Jafeti, tí àwọn náà sì bí ọmọ lẹ́yìn ìkún omi.
Oto dzieje rodu synów Noego: Sema, Chama i Jafeta, którym po potopie urodzili się synowie.
2 Àwọn ọmọ Jafeti ni: Gomeri, Magogu, Madai, Jafani, Tubali, Meṣeki àti Tirasi.
Synowie Jafeta: Gomer, Magog, Madaj, Jawan, Tubal, Meszek i Tiras.
3 Àwọn ọmọ Gomeri ni: Aṣkenasi, Rifati àti Togarma.
Synowie Gomera: Aszkenaz, Rifat i Togarma.
4 Àwọn ọmọ Jafani ni: Eliṣa, Tarṣiṣi, Kittimu, àti Dodanimu.
Synowie Jawana: Elisza, Tarszisz, Kittim i Dodanim.
5 (Láti ọ̀dọ̀ àwọn wọ̀nyí ni àwọn tí ń gbé agbègbè tí omi wà ti tàn ká agbègbè wọn, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, ìdílé wọn ní orílẹ̀-èdè wọn, olúkúlùkù pẹ̀lú èdè tirẹ̀).
Od nich rozdzielone zostały wyspy narodów po swych ziemiach; każdy według swojego języka i według swoich rodów, w swoich narodach.
6 Àwọn ọmọ Hamu ni: Kuṣi, Ejibiti, Puti àti Kenaani.
A synowie Chama: Kusz, Misraim, Put i Kanaan.
7 Àwọn ọmọ Kuṣi ni: Seba, Hafila, Sabta, Raama, àti Sabteka. Àwọn ọmọ Raama ni: Ṣeba àti Dedani.
Synowie zaś Kusza: Seba, Chawila, Sabta, Rama i Sabteka. Synowie Ramy: Szeba i Dedan.
8 Kuṣi sì bí Nimrodu, ẹni tí ó di alágbára jagunjagun ní ayé.
Kusz spłodził Nimroda, który zaczął być mocarzem na ziemi.
9 Ó sì jẹ́ ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa; nítorí náà ni a ṣe ń wí pé, “Bí Nimrodu, ògbójú ọdẹ níwájú Olúwa.”
Ten był mocarnym myśliwym przed PANEM. Dlatego mówi się: Tak jak Nimrod, mocarny myśliwy przed PANEM.
10 Ìjọba rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ni Babeli, Ereki, Akkadi, Kalne, gbogbo wọn wà ní ilẹ̀ Ṣinari.
Początkiem jego królestwa były Babel, Erek, Akkad i Kalne w ziemi Szinear.
11 Láti ilẹ̀ náà ni ó ti lọ sí Asiria, níbi tí ó ti tẹ ìlú Ninefe, Rehoboti àti Kala,
Z tej ziemi wyszedł Assur i zbudował Niniwę i miasto Rechobot, i Kalach.
12 àti Resini, tí ó wà ní àárín Ninefe àti Kala, tí ó jẹ́ ìlú olókìkí.
Także wielkie miasto Resan pomiędzy Niniwą i Kalach.
13 Ejibiti sì bí Ludimu, Anamimu, Lehabimu, Naftuhimu.
Misraim zaś spłodził Ludima, Ananima, Lahabima i Naftuchima;
14 Patrusimu, Kasluhimu (láti ọ̀dọ̀ ẹni tí àwọn ará Filistini ti wá) àti àwọn ará Kaftorimu.
Oraz Patrusyma, Kasluchima (z których pochodzą Filistyni) i Kaftoryma.
15 Kenaani sì bí Sidoni àkọ́bí rẹ̀, àti Heti.
Kanaan zaś spłodził Sydona, swego pierworodnego, i Cheta;
16 Àti àwọn ará Jebusi, àti àwọn ará Amori, àti àwọn ará Girgaṣi,
I Jebusytów, Amorytów, i Girgaszytów;
17 àti àwọn ará Hifi, àti àwọn ará Arki, àti àwọn ará Sini,
I Chiwwitów, Arkitów, i Sinitów;
18 àti àwọn ará Arfadi, àti àwọn ará Semari, àti àwọn ará Hamati. Lẹ́yìn èyí ni àwọn ẹ̀yà Kenaani tànkálẹ̀.
I Arwadytów, Semarytów, i Chamatytów. A potem rozproszyły się rody Kananejczyków.
19 Ààlà ilẹ̀ àwọn ará Kenaani sì dé Sidoni, lọ sí Gerari títí dé Gasa, lọ sí Sodomu, Gomorra, Adma àti Seboimu, títí dé Laṣa.
A granica Kananejczyków biegła od Sydonu w kierunku Gerary aż do Gazy, w kierunku Sodomy i Gomory, Adamy i Seboima aż do Leszy.
20 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Hamu, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, àti èdè wọn, ní ìpínlẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
To [są] synowie Chama według ich rodów i języków, w ich ziemiach i narodach.
21 A bí àwọn ọmọ fún Ṣemu tí Jafeti jẹ́ ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin: Ṣemu sì ni baba gbogbo àwọn ọmọ Eberi.
A Semowi, ojcu wszystkich synów Ebera, bratu Jafeta, który był starszy, urodzili się synowie.
22 Àwọn ọmọ Ṣemu ni: Elamu, Aṣuri, Arfakṣadi, Ludi àti Aramu.
[Synowie] Sema: Elam, Assur, Arpachszad, Lud i Aram.
23 Àwọn ọmọ Aramu ni: Usi, Huli, Geteri àti Meṣeki.
Synowie Arama: Us, Chul, Geter i Masz.
24 Arfakṣadi sì bí Ṣela, Ṣela sì bí Eberi.
Arpachszad zaś spłodził Szelacha, a Szelach spłodził Ebera.
25 Eberi sì bí ọmọ méjì: ọ̀kan ń jẹ́ Pelegi, nítorí ní ìgbà ọjọ́ rẹ̀ ni ilẹ̀ ya; orúkọ arákùnrin rẹ̀ ni Joktani.
Eberowi urodzili się dwaj synowie: imię jednego – Peleg, gdyż za jego dni ziemia została rozdzielona; a imię jego brata – Joktan.
26 Joktani sì bí Almodadi, Ṣelefi, Hasarmafeti, Jera.
Joktan spłodził Almodada, Szelefa, Chasarmaweta i Jeracha;
27 Hadoramu, Usali, Dikla,
Hadorama, Uzala i Diklę;
28 Obali, Abimaeli, Ṣeba.
Obala, Abimaela i Szeba;
29 Ofiri, Hafila àti Jobabu. Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Joktani.
Ofira, Chawilę i Jobaba; ci wszyscy [byli] synami Joktana.
30 Agbègbè ibi tí wọn ń gbé bẹ̀rẹ̀ láti Meṣa títí dé Sefari, ní àwọn ilẹ̀ tó kún fún òkè ní ìlà-oòrùn.
A obszar ich zamieszkania ciągnął się od Meszy w kierunku Sefar, wschodniej góry.
31 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Ṣemu gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn, ní èdè wọn, ní ilẹ̀ wọn àti ní orílẹ̀-èdè wọn.
To [są] synowie Sema według ich rodów i języków, w ich ziemiach i narodach.
32 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ẹ̀yà ọmọ Noa gẹ́gẹ́ bí ìran wọn, ní orílẹ̀-èdè wọn. Ní ipasẹ̀ wọn ni àwọn ènìyàn ti tàn ká ilẹ̀ ayé lẹ́yìn ìkún omi.
To [są] rody synów Noego według ich pokoleń i w ich narodach. Od nich [wywodzą się] narody, które rozprzestrzeniły się na ziemi po potopie.

< Genesis 10 >