< Galatians 6 >
1 Ará, bí a tilẹ̀ mú ènìyàn nínú ẹ̀ṣẹ̀ kan, kí ẹ̀yin tí í ṣe ti Ẹ̀mí mú irú ẹni bẹ́ẹ̀ bọ̀ sípò nínú ẹ̀mí ìwà tútù; kí ìwọ tìkára rẹ̀ máa kíyèsára, kí a má ba à dán ìwọ náà wò pẹ̀lú.
Bhaili, labha omunu agwatilwe mu bhibhibhi, emwe bhanu omutangasibhwa no mwoyo, mumusubhye omunu uyo mu mwoyo gwo bhwololo. Enu nimwiyangalila bhenene koleleki mutasakwa.
2 Ẹ máa ru ẹrù ọmọnìkejì yín, kí ẹ sì fi bẹ́ẹ̀ mú òfin Kristi ṣẹ.
Musakilanega emijigo, kutyo omukumisha echilagilo cha Kristo.
3 Nítorí bí ènìyàn kan bá ń ro ara rẹ̀ sí ẹnìkan, nígbà tí kò jẹ́ nǹkan, ó ń tan ara rẹ̀ jẹ.
Labha omunu wona wona kelola ati ni wa kisi kenu nti chinu, kejiga omwene.
4 Ṣùgbọ́n kí olúkúlùkù yẹ iṣẹ́ ara rẹ̀ wò, nígbà náà, ohun ìmú-ṣogo rẹ̀ yóò jẹ́ nínú ti ara rẹ̀ nìkan, kì yóò sì jẹ nínú ti ọmọnìkejì rẹ̀.
Bhuli umwi alole omulimu gwae omwene. Niwo kabha ne chinu cho kwilata omwene wenyele, amwi tali okwisusanya no munu undi.
5 Nítorí pé olúkúlùkù ni yóò ru ẹrù ara rẹ̀.
Kwo kubha bhuli munu alitwika omujigo gwae omwene.
6 Ṣùgbọ́n kí ẹni tí a ń kọ́ nínú ọ̀rọ̀ náà máa pèsè ohun rere gbogbo fún ẹni tí ń kọ́ni.
Unu eigisibhwe omusango gwo bhuanga ni bhusibhusi abhwile omwiigisha waye gone ge kisi.
7 Kí a má ṣe tàn yín jẹ; a kò lè gan Ọlọ́run: nítorí ohunkóhun tí ènìyàn bá fúnrúgbìn, òhun ni yóò sì ká.
Mutabheibhwa. Nyamuanga atakujimibhwa. Okubha chone chone chinu omunu kayamba, nicho aligesa.
8 Nítorí ẹni tí ó bá ń fúnrúgbìn sípa ti ara yóò ká ìdíbàjẹ́ ti ara ṣùgbọ́n ẹni tí ń fúnrúgbìn sípa ti ẹ̀mí yóò ti inú ẹ̀mí ká ìyè àìnípẹ̀kun. (aiōnios )
Bhuli unu kayamba imbibho ku mubhili gwae niwe aligesa obhubhole, nawe unu kayamba ku Mwoyo, niwe aligesa obhuanga bhwa kajanende okusoka ku Mwoyo. (aiōnios )
9 Ẹ má sì jẹ́ kí àárẹ̀ ọkàn mú wa ní ṣíṣe rere, nítorí tí a ó kórè nígbà tí àkókò bá dé, bí a kò bá ṣe àárẹ̀.
Chisige kuigwa okukola ebhye kisi, okubha alibha jinsiku jeya chiligesa labha chitakulengala.
10 Ǹjẹ́ bí a ti ń rí àǹfààní gba, ẹ jẹ́ kí a máa ṣoore fún gbogbo ènìyàn, àti pàápàá fún àwọn tí í ṣe ará ilé ìgbàgbọ́.
Mbe kutyo, olwo chilabhonaga omwanya, chibhakolele kisi bhone. Nawe okukilao chibhakolele kisi abho bhali mu likilisha.
11 Ẹ wo bí mo ti fi ọwọ́ ara mi kọ̀wé gàdàgbà-gàdàgbà sí yín.
Mulole obhunene bhwa jinyalubha jinu nabhandikie kwo kubhoko kwani omwene.
12 Iye àwọn tí ń fẹ́ ṣe àṣehàn ni ara wọn ń rọ yín láti kọlà; kìkì nítorí pé kí a má ba à ṣe inúnibíni sí wọn nítorí àgbélébùú Kristi.
Abho abhenda okwikondya mu bhyo mubhili nibho abho abhabhasinyilisha musalwe. Abhakola kutyo koleleki bhasige okunyasibhwa kulwo musalabha gwa Kristo.
13 Nítorí àwọn tí a kọ ní ilà pàápàá kò pa òfin mọ́, ṣùgbọ́n wọ́n ń fẹ́ mú yin kọlà, kí wọn lè máa ṣògo nínú ara yín.
Okubha bhanu bhasalilwe one bhatakugwata ebhilagilo abhene. Nawe abhenda emwe musalwe koleleki bhelate ku mibhili jemwe.
14 Ṣùgbọ́n kí a má ṣe rí i pé èmi ń ṣògo, bí kò ṣe nínú àgbélébùú Jesu Kristi Olúwa wa, nípasẹ̀ ẹni tí a ti kan ayé mọ́ àgbélébùú fún mi, àti èmi fún ayé.
Nawe itaja kusokelela ninilata tali ku musalabha gwa Latabhugenyi weswe Yesu Kristo. Ni kubhwo mwene echalo chabhambilwe kwanye nanye ku chalo.
15 Nítorí pé nínú Kristi Jesu, ìkọlà kò jẹ́ ohun kan, tàbí àìkọlà, bí kò ṣe ẹ̀dá tuntun.
Okubha okusalwa chitali chinu. Nawe ni kwibhulwa bhuyaya.
16 Kí àlàáfíà àti àánú wà lórí gbogbo àwọn tí ń rìn ní ìlànà yìí, àti lórí Israẹli Ọlọ́run.
Na bhone bhanu abhalibhatila mu chilagilo echo, omulembe ne chigongo bhibhe ku bhene, na ku Israeli ya Nyamuanga.
17 Láti ìsinsin yìí lọ, kí ẹnikẹ́ni má ṣe yọ mí lẹ́nu mọ́; nítorí èmi ń ru àpá Jesu Olúwa kiri ní ara mi.
Okusoka wolyanu omunu wone asige okunyasha, okubha nigegele jinkamo ja Yesu mu mubhili gwani.
18 Ará, oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa, kí ó wà pẹ̀lú ẹ̀mí yín. Àmín.
Echigongo cha Latabhugenyi weswe Yesu Kristo chibhe ne myoyo jemwe, bhaili. Amina.