< Galatians 6 >
1 Ará, bí a tilẹ̀ mú ènìyàn nínú ẹ̀ṣẹ̀ kan, kí ẹ̀yin tí í ṣe ti Ẹ̀mí mú irú ẹni bẹ́ẹ̀ bọ̀ sípò nínú ẹ̀mí ìwà tútù; kí ìwọ tìkára rẹ̀ máa kíyèsára, kí a má ba à dán ìwọ náà wò pẹ̀lú.
Kebmibo, nokom tau nii bwirang keretiye, kom biro ki yuwatangbekeu, kom yilau kico mor yuwatangbeko lomcomeu. Dila ko nyom dorkumero, kati kom doken cuwaka.
2 Ẹ máa ru ẹrù ọmọnìkejì yín, kí ẹ sì fi bẹ́ẹ̀ mú òfin Kristi ṣẹ.
Kom ci bwini bwitikumero, la-nyeu an diim bolang kiristi ko
3 Nítorí bí ènìyàn kan bá ń ro ara rẹ̀ sí ẹnìkan, nígbà tí kò jẹ́ nǹkan, ó ń tan ara rẹ̀ jẹ.
Tano ka-nge antu dorcero kicin diker dila ci kebori, ci bol dorcer.
4 Ṣùgbọ́n kí olúkúlùkù yẹ iṣẹ́ ara rẹ̀ wò, nígbà náà, ohun ìmú-ṣogo rẹ̀ yóò jẹ́ nínú ti ara rẹ̀ nìkan, kì yóò sì jẹ nínú ti ọmọnìkejì rẹ̀.
Nii acuwa na-ngen cero, lana nyime catin diker buulang mor bwiyece kebo ka-nge nii nin.
5 Nítorí pé olúkúlùkù ni yóò ru ẹrù ara rẹ̀.
Nii atu na-ngen doret cer ki bwico.
6 Ṣùgbọ́n kí ẹni tí a ń kọ́ nínú ọ̀rọ̀ náà máa pèsè ohun rere gbogbo fún ẹni tí ń kọ́ni.
Wuro cii merangten dikereu, ca caluma dikeroco ka-nge wo merang ci nen neu.
7 Kí a má ṣe tàn yín jẹ; a kò lè gan Ọlọ́run: nítorí ohunkóhun tí ènìyàn bá fúnrúgbìn, òhun ni yóò sì ká.
ciiya bol komde, nii mani ayi Kwama mwan kereti, dike nii fiyeu co dike ca biyeetiye.
8 Nítorí ẹni tí ó bá ń fúnrúgbìn sípa ti ara yóò ká ìdíbàjẹ́ ti ara ṣùgbọ́n ẹni tí ń fúnrúgbìn sípa ti ẹ̀mí yóò ti inú ẹ̀mí ká ìyè àìnípẹ̀kun. (aiōnios )
Niiwo fii dum ki cwika bwiyekeri, cabiyee bubaka fiye bwiyo wiye. Nii wo fi dum yuwatangbekeri, ca biye dume fiye yuwatangbeko wiyi. (aiōnios )
9 Ẹ má sì jẹ́ kí àárẹ̀ ọkàn mú wa ní ṣíṣe rere, nítorí tí a ó kórè nígbà tí àkókò bá dé, bí a kò bá ṣe àárẹ̀.
A luwabore maka dikero ko ken, tano kiini lam dong-dong ri ban biye bituwe, ta bi cokbo nerbero ri
10 Ǹjẹ́ bí a ti ń rí àǹfààní gba, ẹ jẹ́ kí a máa ṣoore fún gbogbo ènìyàn, àti pàápàá fún àwọn tí í ṣe ará ilé ìgbàgbọ́.
Ki kiini biki keka-ngiyeu, bima nubonin dikero ken gwam, nobo nanubowo yilam akwama ce ki bilenke.
11 Ẹ wo bí mo ti fi ọwọ́ ara mi kọ̀wé gàdàgbà-gàdàgbà sí yín.
To bifumero durko mimukang kumen kikang mikeu.
12 Iye àwọn tí ń fẹ́ ṣe àṣehàn ni ara wọn ń rọ yín láti kọlà; kìkì nítorí pé kí a má ba à ṣe inúnibíni sí wọn nítorí àgbélébùú Kristi.
Nubo cwiti nacii dang dang nym mor bwiyeceu, cii ciidokkomti kibikwan nakom biyem lareu. Cii ma-nyeu kati yilo cii ne cii dota-nge ker kwoblom bwatiyem kiristim.
13 Nítorí àwọn tí a kọ ní ilà pàápàá kò pa òfin mọ́, ṣùgbọ́n wọ́n ń fẹ́ mú yin kọlà, kí wọn lè máa ṣògo nínú ara yín.
La kebo kanubo biyem lereu bwangteng bolong tiye, dila ciiki cwi kom biyem laro nacii kung dorti mor bwiye kume.
14 Ṣùgbọ́n kí a má ṣe rí i pé èmi ń ṣògo, bí kò ṣe nínú àgbélébùú Jesu Kristi Olúwa wa, nípasẹ̀ ẹni tí a ti kan ayé mọ́ àgbélébùú fún mi, àti èmi fún ayé.
La ayilam de mima bitenamti, nokebo ki kwoblom bwtiyem Teluwe be Yesu kiristi tiri, won co dike bwi cii kulken kalewo fiye mi wiye.
15 Nítorí pé nínú Kristi Jesu, ìkọlà kò jẹ́ ohun kan, tàbí àìkọlà, bí kò ṣe ẹ̀dá tuntun.
Biyeka lareko ka-nge wo biyebeu kebo dike ka-nge fiye miwiye. Kan boro fwir yilam dikero ken fiye miwiye.
16 Kí àlàáfíà àti àánú wà lórí gbogbo àwọn tí ń rìn ní ìlànà yìí, àti lórí Israẹli Ọlọ́run.
Birombo yiyimbo ken tiyeu, yobka nerek ka-nge jire dume ayilam cee, ka-nge dor Israila Kwamar ken.
17 Láti ìsinsin yìí lọ, kí ẹnikẹ́ni má ṣe yọ mí lẹ́nu mọ́; nítorí èmi ń ru àpá Jesu Olúwa kiri ní ara mi.
Tabti anwo yaken ciko ka-nge a kwomyere, wori mi tumki yirom Yesum bwimi.
18 Ará, oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa, kí ó wà pẹ̀lú ẹ̀mí yín. Àmín.
Luma Teluwebe Yesu abwangten ka-nge yuwatangbe kume ko, kebmibo. Ati nyo.