< Galatians 3 >
1 Ẹ̀yin aláìnírònú ará Galatia! Ta ní ha tàn yín jẹ, kí ẹ̀yin má ṣe gba òtítọ́ gbọ́? Ní ojú ẹni tí a fi Jesu Kristi hàn gbangba láàrín yín ni ẹni tí a kàn mọ́ àgbélébùú.
Bhagalatia bhajinga, lihu leleku la uovu lalibhahalibu? Je Yesu Kristu alasibhu lepi katya msulubibwa palongolo pa mihu gha yhomo?
2 Kìkì èyí ni mo fẹ́ béèrè lọ́wọ́ yín, nípa iṣẹ́ òfin ni ẹ̀yin gba Ẹ̀mí bí, tàbí nípa ìgbọ́ràn pẹ̀lú ìgbàgbọ́?
Nene nilonda tu kumanya ele kuhomela kwa muenga. Je mwapokili Roho kwa matendo gha Sheria au ndo mwaamini kela kamwapeliki?
3 Báyìí ni ẹ̀yin ṣe jẹ òmùgọ̀ tó bí? Ẹ̀yin tí ó ti bẹ̀rẹ̀ ìgbé ayé ìgbàgbọ́ yín nípa ti Ẹ̀mí, ṣé a ti wá sọ yín di pípé nípa ti ara ni?
Ko, muenga ni bhajinga kiasi ekhe? ko mwayandili mu Roho ili mmalai mu mbhele?
4 Ẹ̀yin ha ti jìyà ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan wọ̀nyí lásán? Bí ó bá ṣe pé nítòótọ́ lásán ni.
Ko mwatesiki kwa mambo mingi mebhwa, katya kueli ghayele gha mebhwa?
5 Ṣé Ọlọ́run fún yín ní Ẹ̀mí rẹ̀, tí ó sì ṣe iṣẹ́ ìyanu láàrín yín nítorí tí ẹ̀yin pa òfin mọ, tàbí nítorí ẹ ní ìgbàgbọ́ sí ohun tí ẹ gbọ́?
Ko muene yaipisya Roho kwa muenga ni kubhomba matendo gha nghofo kwa yhomo iketa kwa matendo gha sheria au kwa kup'etela pamonga ni imani?
6 Gẹ́gẹ́ bí Abrahamu “Ó gba Ọlọ́run gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un.”
Abraham “Amwamini K'yara ahesabibhu kujo mwenye haki”.
7 Ẹ jẹ́ kí ó yé é yín nígbà náà pé, àwọn ti ó gbàgbọ́, àwọn náà ní í ṣe ọmọ Abrahamu.
Kwa namna yela yela muyelewahi ya ndabha, bhala bhabhiamini yakuwa ni bhana bha Abraham.
8 Bí ìwé mímọ́ sì tí wí tẹ́lẹ̀ pé, Ọlọ́run yóò dá aláìkọlà láre nípa ìgbàgbọ́, ó tí wàásù ìyìnrere ṣáájú fún Abrahamu, ó ń wí pé, “Nínú rẹ̀ ni a ó bùkún fún gbogbo orílẹ̀-èdè.”
Liyandiku latabilibhu yakuwa K'yara ngabhahesabili haki bhanu bha mataifa kwa njela ya imani. Injili yahubilibhu hosi kwa Abraham:”Kwa bhebhe mataifa ghoa ghibalikibhwa”.
9 Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni àwọn tí i ṣe tí ìgbàgbọ́ jẹ́ ẹni alábùkún fún pẹ̀lú Abrahamu olódodo.
Ili kabhele bhabhayele niimani bhabalikibhuayi pamonga ni Abraham, yaayele ni imani.
10 Nítorí pé iye àwọn tí ń bẹ ni ipa iṣẹ́ òfin ń bẹ lábẹ́ ègún: nítorí tí a tí kọ ọ́ pé, “Ìfibú ni olúkúlùkù ẹni tí kò dúró nínú ohun gbogbo tí a kọ sínú ìwé òfin láti máa ṣe wọ́n”.
Bhala bhoa bhabhitegemela matendo gha sheria bhayele pasi mu laana. Kwa ndabha iyandikibhu, “Alanibhu kila munu yaishikamanahee ni mambo ghoa ghaghayandikibhu mukitabu ka sheria, kughabhomba ghoa.”
11 Nítorí ó dánilójú pé, a kò dá ẹnikẹ́ni láre níwájú Ọlọ́run nípa iṣẹ́ òfin: nítorí pé, “Olódodo yóò yè nípa ìgbàgbọ́.”
Henu ndo bhuasi yakuwa K'yara akamwesabilahee haki hata immonga musheria, kwa ndabha, “Yaayele ni haki alaishi ki imani”
12 Òfin kì í sì í ṣe ti ìgbàgbọ́: ṣùgbọ́n, “Ẹni tí ó ba ṣe, yóò yè nípa wọn.”
Sheria yihomelahe ni imani, Badala yaki “Yaifwanyai mambo agha kup'etela sheria, alaishi kisheria”.
13 Kristi ti rà wá padà kúrò lọ́wọ́ ègún òfin, ẹni tí a fi ṣe ègún fún wa: nítorí tí a ti kọ ọ́ pé, “Ìfibú ni olúkúlùkù ẹni tí a fi kọ́ sórí igi.”
istu atukombhuili tete kuhomela mu laana ya sheria yapayafwanyikai laana kwajia yhoto. Kwa ndabha iyandikibhu, “Alanibhuayi” kila munu yaibinai munani mulibehe.”
14 Ó gbà wá là ki ìbùkún Abrahamu ba à lè wá sórí àwọn aláìkọlà nípa Kristi Jesu; kí àwa ba à lè gba ìlérí Ẹ̀mí nípa ìgbàgbọ́.
Lilengo layele ya ndabha, baraka ambasyo sasa yele kwa Ibrahimu ngasaidai kwa bhanu bhamataifa kup'etela Yesu Kristu, yakuwa tubhwesyai kuyhopa ahadi ya Roho kup'etela imani.
15 Ará, èmi ń sọ̀rọ̀ bí ènìyàn, gẹ́gẹ́ bi májẹ̀mú ènìyàn ti a ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, kò sí ẹni tí ó lè sọ ọ́ di asán, tàbí tí ó lè fi kún un mọ́.
Ndongo, nikabhajobhela na kibinadamu. Kabhele magono ambapo agano la kibinadamu palimalikai kubhekibhwa imara, ayelepi yaibhwesyai kupuuza au kuyongesela.
16 Ǹjẹ́ fún Abrahamu àti fún irú-ọmọ rẹ̀ ni a ti ṣe àwọn ìlérí náà. Ìwé Mímọ́ kò ṣọ wí pé, “fún àwọn irú-ọmọ rẹ̀,” bí ẹni pé ọ̀pọ̀lọpọ̀; ṣùgbọ́n bí ẹni pé ọ̀kan ṣoṣo, “àti fún irú-ọmọ rẹ̀,” èyí tí í ṣe Kristi.
Henu ahadi sajobhibhu kwa Ibrahimu ni kizazikya muene. Yijobhahee, “Kwa vizazi,” kumaanisya bhingi, badala yaki kwa mmonga yumuene, “Kwa kizazi kyako,” ambaye ndo Kristu.
17 Èyí tí mò ń wí ni pé: májẹ̀mú tí Ọlọ́run ti fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ níṣàájú, òfin ti ó dé lẹ́yìn ọgbọ̀nlénírinwó ọdún kò lè sọ ọ́ di asán, kí ó sì mú ìlérí náà di aláìlágbára.
Henu nijobha nah, sheria ya yahidili miaka 430 badaye, yibhosya lepi agano la kunyuma lalibheki bhusima ni K'yara.
18 Nítorí bí ogún náà bá dúró lórí ṣíṣe gẹ́gẹ́ bí í òfin kì í ṣe ti ìlérí mọ́, ṣùgbọ́n Ọlọ́run ti fi í fún Abrahamu nípa ìlérí.
Yandabha kujo ulisi ngawahidili ki njela ya sheria, ngaiyelepi kabhele kuhida kwa njela ya ahadi. Ndabha K'yara apisili mebhwa kwa Ibrahimu kwa njela ya ahadi.
19 Ǹjẹ́ kí ha ni òfin? A fi kún un nítorí ìrékọjá títí irú-ọmọ tí a ti ṣe ìlérí fún yóò fi dé; a sì tipasẹ̀ àwọn angẹli ṣe ìlànà rẹ̀ láti ọwọ́ alárinà kan wá.
Kwandayakiki henu sheria yapisibhu? Yayongisibhu ndabha ya makosa, mpaka mzao wa Ibrahimu ulota kwa bhala ambabho kwa bhene amalili kuhaidibhwa. Sheria yabhekibhu ki shinikizo kup'etela malaika kwa kibhoko Kya kupatanisya.
20 Ǹjẹ́ onílàjà kì í ṣe alárinà ti ẹnìkan, ṣùgbọ́n ọ̀kan ni Ọlọ́run.
Henu mpatanishi imaanisya zaidi ya munu mmonga, ndo K'yara yumuene.
21 Nítorí náà òfin ha lòdì sí àwọn ìlérí Ọlọ́run bí? Kí a má rí i; nítorí ìbá ṣe pé a ti fi òfin kan fún ni tí ó lágbára láti sọ ni di ààyè nítòótọ́ òdodo ìbá ti tipasẹ̀ òfin wà.
Kwa ele ko sheria iyele kinyume ni ahadi sa K'yara? La hasha! kwa ndabha sheria yaiyele ipisibhu iyele ni ubhueso wa kuleta usima, haki ngaipatikene kwa sheria.
22 Ṣùgbọ́n ìwé mímọ́ ti fi yé wa pé gbogbo ènìyàn ni ń bẹ lábẹ́ ìdè ẹ̀ṣẹ̀, kí a lè fi ìlérí nípa ìgbàgbọ́ nínú Jesu Kristi fún àwọn tí ó gbàgbọ́.
Badala yaki, liyandiku lifungili mambo ghoa pasi mu thambi. K'yara aketili naa ili ya ndabha ahadi ya muene ya kutookola tete kwa imani kup'etela Yesu Kristu lbhuesyai kupatikana kwa bhala bhabhiamini.
23 Ṣùgbọ́n kí ìgbàgbọ́ tó dé, a ti pa wá mọ́ lábẹ́ òfin, a sì sé wa mọ́ de ìgbàgbọ́ tí a ń bọ̀ wá fihàn.
Kabula ya imani ya Kristu kuhida, twayele tufungibhu ni kuya pasi pa sheria hadi pawihidai ufunuo was imani.
24 Nítorí náà òfin ti jẹ́ olùtọ́jú láti mú ènìyàn wá sọ́dọ̀ Kristi, kí a lè dá wa láre nípa ìgbàgbọ́.
Kwa ele sheria yafwanyiki kwa kiongozi wa yhoto hadi Kristu pahaaidayi, ndabha tuhesabibhuayi mu haki ni mwimani.
25 Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà tí ìgbàgbọ́ ti dé, àwa kò sí lábẹ́ olùtọ́jú mọ́.
Henu yandabha imani ihidili, tuyelepi kabhele pasi pabha angalizi.
26 Nítorí pé ọmọ Ọlọ́run ni gbogbo yín, nípa ìgbàgbọ́ nínú Kristi Jesu.
Kwa ndabha muenga mwabhoa ndo bhana bha K'yara kup'etela imani ni Kristu Yesu.
27 Nítorí pé iye ẹ̀yin tí a ti bamitiisi sínú Kristi ti gbé Kristi wọ̀.
Mwabhoa bhambatizibhu kup'etela Kristu mmjifwekili Kristu.
28 Kò le sí Júù tàbí Giriki, ẹrú tàbí òmìnira, ọkùnrin tàbí obìnrin nítorí pé ọ̀kan ni nínú Kristi Jesu.
Ayelepi Myaudi wala Myunani, n'tumwa wala huru, bhagosi wala bhadala, kwandabha muenga mwabhoa n'do bhamonga kup'etela Kristu Yesu.
29 Bí ẹ̀yin bá sì jẹ́ ti Kristi, ǹjẹ́ ẹ̀yin ní irú-ọmọ Abrahamu, àti àrólé gẹ́gẹ́ bí ìlérí.
Kama muenga ndo bha Kristu, basi ndo uzao wa Ibrahimu, bharithi mu jibu wa ahadi.