< Ezra 9 >

1 Lẹ́yìn ìgbà tí a ti ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí tán, àwọn olórí tọ̀ mí wá, wọ́n sì wí pé, “Àwọn ènìyàn Israẹli, tí ó fi mọ́ àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, kò tì í ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn agbègbè tí wọ́n ń ṣe ohun ìríra bí i ti àwọn ará Kenaani, àwọn ará Hiti, àwọn ará Peresi, àwọn ará Jebusi, àwọn ará Ammoni, àwọn ará Moabu, àwọn ará Ejibiti àti ti àwọn ará Amori.
“Idi nalpas dagitoy a banbanag, immasideg kaniak dagiti opisial ket kinunada, 'Dagiti tattao ti Israel, dagiti padi, ken dagiti Levita ket saanda nga inlasin dagiti bagida manipud kadagiti kinarimon dagiti tattao iti sabali a daga a: Canaanita, Heteo, Perezeo, Jebuseo, ken Ammonitas, Moabitas, Egipcios, ken dagiti Amoreos.
2 Wọ́n ti fẹ́ lára àwọn ọmọbìnrin wọn fún ara wọn àti fún àwọn ọmọkùnrin wọn gẹ́gẹ́ bí aya, wọ́n ti da irú-ọmọ ìran mímọ́ pọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn ti ó wà ní àyíká wọn. Àwọn olórí àti àwọn ìjòyè ta àwọn ènìyàn tókù yọ nínú híhu ìwà àìṣòótọ́.”
Gapu ta innalada dagiti dadduma nga annakda a babbai ken lallaki, ket inlaokda dagiti nasantoan a tattao kadagiti tattao iti sabali a daga. Ket dagiti pay opisial ken mangidadaulo ti nangiyun-una iti daytoy a kina-awan ti pammati.'
3 Nígbà tí mo gbọ́ èyí, mo fa àwọ̀tẹ́lẹ̀ àti agbádá mi ya, mo tu irun orí àti irùngbọ̀n mi, mo sì jókòó ní ìjayà.
Idi nangngegko daytoy, rinay-abko ti pagan-anay ken ti kagayko ken pinarutko dagiti buok iti ulok ken ti barbasko. Ket nagtugawak a mababain.
4 Nígbà náà ni gbogbo àwọn tí ó wárìrì sí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Israẹli kó ara wọn jọ yí mi ká nítorí àìṣòótọ́ àwọn ìgbèkùn yìí. Èmi sì jókòó níbẹ̀ ní ìjayà títí di àkókò ìrúbọ àṣálẹ́.
Amin dagidiay a nagtigerger iti sasao ti Dios ti Israel maipanggep iti daytoy a kinaawan pammati ket naguummong iti ayanko kabayatan nga agtugtugawak a mababain agingga iti rabii a panagidatag iti daton.
5 Ní ìgbà tí ó di àkókò ìrúbọ àṣálẹ́, mo dìde kúrò nínú ìrẹ̀wẹ̀sì ọkàn mi, pẹ̀lú àwọ̀tẹ́lẹ̀ àti agbádá mi yíya ní ọrùn mi, mo kúnlẹ̀ lórí eékún mi méjèèjì, mo sì tẹ́ ọwọ́ mi méjèèjì sí Olúwa Ọlọ́run mi.
Ngem iti panagidaton iti rabii, nagtakderak manipud iti pwesto a nakaibabainak a naray-ab ti pagan-anay ken kagayko, nagparintumengak ket inyunnatko dagiti imak kenni Yahweh a Diosko.
6 Mo sì gbàdúrà: “Ojú tì mí gidigidi, tí n kò fi lè gbé ojú mi sókè sí ọ̀dọ̀ rẹ, Ọlọ́run mi, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wá di púpọ̀ ní orí wa, ẹ̀bi wa sì ga kan àwọn ọ̀run.
Kinunak: 'Diosko, mababainak unay a mangitangad iti rupak kenka, ta nangatngaton dagiti nadagsen a basolmi ngem ti ulomi, ken dimmanonen kadagiti langit ti biddutmi.
7 Láti ọjọ́ àwọn baba wá ni ẹ̀bi wa ti pọ̀ jọjọ títí di ìsinsin yìí. Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa, àwa àti àwọn ọba wa àti àwọn àlùfáà wa ni a ti sọ di ẹni idà, ẹni ìgbèkùn, ìkógun àti ẹni ẹ̀sín lọ́wọ́ àwọn àjèjì ọba, bí ó ti rí lónìí.
Manipud kadagiti al-aldaw dagiti kapuonanmi agingga ita ket adun ti nagbasolanmi. Gapu kadagiti nadagsen a basolmi, dakami, dagiti arimi, ken dagiti padimi ket naipaimakami kadagiti ari iti daytoy a lubong, iti kampilan, iti pannaka-ibalud, ken iti pannakasamsam ken iti pannakaibabain, kas iti kasasaadmi ita.
8 “Ṣùgbọ́n ni ìsinsin yìí, fún ìgbà díẹ̀, ni a ti fi oore-ọ̀fẹ́ fún wa láti ọ̀dọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa wá láti sálà, àti láti fi èèkàn fún wa ni ibi mímọ́ rẹ̀, nítorí kí Ọlọ́run kí ó lè mú ojú wa mọ́lẹ̀, kí ó sì tún wa gbé dìde díẹ̀ kúrò nínú ìgbèkùn wa.
Ngem ita, iti apagbiit a tiempo, immay ti asi manipud kenni Yahweh a Diosmi a nangibati kadakami kadagiti dadduma a nakalasat ken mangted kadakami iti namnama iti nasantoan a lugarna. Ti Dios ti nanglawag kadagiti matami ken nangted iti bassit nga inana manipud iti pannakatagabumi.
9 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwa jẹ́ ẹrú, Ọlọ́run wa kò fi wa sílẹ̀ nínú ìgbèkùn wa. Ó ti fi àánú hàn fún wa ni iwájú àwọn ọba Persia: Ó ti fún wa ní ìgbé ayé tuntun láti tún odi ilé Ọlọ́run wa mọ, kí a sì tún àwókù rẹ̀ ṣe, ó sì fi odi ààbò fún wa ní Juda àti ní Jerusalẹmu.
Ta tagabukami, ngem saannakami a nalipatan ti Diosmi ngem pinagtalinaedna ti kinapudnona iti tulagna kadakami. Inaramidna daytoy iti imatang ti ari ti Persia tapno pabilgennakami, tapno maibangonmi manen ti balay iti Diosmi ken maitarimaan dagiti dadaelna. Inaramidna daytoy tapno maikkanakami iti pader iti pannakasalaknib idiay Juda ken Jerusalem.
10 “Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, Ọlọ́run wa, kí ni àwa yóò wí lẹ́yìn èyí? Nítorí tí àwa kọ àṣẹ rẹ sílẹ̀
Ngem ita, O Diosmi, ania ti makunami kalpasan daytoy? Nalipatanmi dagiti bilinmo,
11 èyí tí ìwọ ti pa fún wa láti ẹnu àwọn wòlíì ìránṣẹ́ rẹ, nígbà ti ìwọ wí pé, ‘Ilẹ̀ náà ti ẹ̀yin ń wọ̀ lọ láti gbà n nì jẹ́ ilẹ̀ aláìmọ́ tó kún fún ẹ̀gbin àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, nípa ṣíṣe ohun ìríra àti híhu ìwà èérí ti kún ún láti ìkángun kan dé èkejì.
dagiti bilin nga intedmo kadagiti adipenmo a dagiti profeta, idi imbagam, “Daytoy a daga a serserkanyo tapno tagikuaen ket narugit a daga. Rinugitan daytoy dagiti tattao iti daga babaen kadagiti makarimon nga aramidda. Agsinumbangir a pinunnoda daytoy babaen kadagiti kinarugitda.
12 Nítorí náà, ẹ má ṣe fi àwọn ọmọbìnrin yín fún àwọn ọmọkùnrin wọn ní ìyàwó tàbí kí ẹ fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin yín ní ìyàwó. Ẹ má ṣe dá májẹ̀mú àlàáfíà pẹ̀lú wọn nígbàkígbà kí ẹ̀yin kí ó sì le lágbára, kí ẹ sì le máa jẹ ire ilẹ̀ náà, kí ẹ sì le fi í sílẹ̀ fún àwọn ọmọ yín gẹ́gẹ́ bí ogún ayérayé.’
Isu nga ita, saanmo nga ipaasawa dagiti annakmo a babbai kadagiti annakda a lallaki; saanmo nga ipaasawa kadagiti annakmo a lallaki kadagiti annakda a babbai, ken saanyo a sapulen ti madama a kinatalna ken ti kinarang-ayda, tapno pumigsakayo ken kanenyo ti nasayaat iti daga, tapno tawiddento daytoy dagiti annakyo iti agnanayon.”
13 “Ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀ sí wa jẹ́ àyọríṣí iṣẹ́ búburú wa àti ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ ńlá wa, síbẹ̀, Ọlọ́run wa, ìjìyà ti ìwọ fún wa kéré si ìjìyà tí ó yẹ fún ẹ̀ṣẹ̀ ti a dá, ìwọ sì fún wa ní àwọn ènìyàn tó ṣẹ́kù bí èyí.
Ngem kalpasan ti amin a dimteng kadakami gapu kadagiti dakes nga aramidmi ken kadagiti nakaro a basolmi—agsipud ta sika, a Diosmi, binabawim ti maikari a dusa kadagiti nadagsen a nagbasolanmi ket intulokmo a makalasatkami—
14 Ǹjẹ́ ó yẹ kí àwa tún yẹ̀ kúrò nínú àṣẹ rẹ, kí a sì máa ṣe ìgbéyàwó papọ̀ pẹ̀lú àwọn ènìyàn tí wọn ti ṣe onírúurú ohun ìríra báyìí? Ṣe ìwọ kò ní bínú sí wa láti pa wá run tí kì yóò sẹ́ ku ẹnikẹ́ni tí yóò là?
salungasingenmi kadi manen dagiti bilbilinmo ket makiasawa kadagitoy a makarimon a tattao? Saankanto kadi a makaunget ket ikisapnakami tapno awan ti uray maysa a mabati ket awan ti uray maysa a makalibas?
15 Ìwọ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, ìwọ jẹ́ olódodo! Àwa ìgbèkùn tí ó ṣẹ́kù bí ó ti rí lónìí. Àwa dúró níwájú rẹ nínú ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ wa, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé nítorí èyí ẹnikẹ́ni nínú wa kò lè dúró níwájú rẹ”.
Yahweh a Dios ti Israel, nalintegka, ta nagtalinaedkami a bassit a nakalasat iti daytoy nga aldaw. Adtoy! Adda kami iti sangoanam kadagiti biddutmi, ta awan ti uray maysa a makatakder iti sangoanam gapu iti daytoy.”'

< Ezra 9 >