< Ezra 6 >

1 Nígbà náà ni ọba Dariusi pàṣẹ, wọ́n sì wá inú ilé ìfí nǹkan pamọ́ sí ní ilé ìṣúra ní Babeli.
Te vaengah Darius manghai loh saithainah a paek tangloeng tih Babylon kah a khueh cabu im kah cabu te a thaih uh.
2 A rí ìwé kíká kan ní Ekbatana ibi kíkó ìwé sí ní ilé olódi agbègbè Media, wọ̀nyí ni ohun tí a kọ sínú rẹ̀. Ìwé ìrántí.
Tedae Media paeng kah manghai im, Akhametha ah cayol te a hmuh tih a khui ah cathut a daek.
3 Ní ọdún kìn-ín-ní ìjọba ọba Kirusi, ọba pa àṣẹ kan nípa tẹmpili Ọlọ́run ní Jerusalẹmu. Jẹ́ kí a tún tẹmpili ibi tí a ti ń rú onírúurú ẹbọ kọ́, kí a fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ lélẹ̀ ni gíga àti fífẹ̀ rẹ̀ jẹ́ àádọ́rùn-ún ẹsẹ̀ bàtà,
Manghai Cyrus kah kum khat dongah tah manghai Cyrus amah loh Jerusalem kah Pathen im te saithainah a paek tih, “Im te hmueih aka nawn kah hmuen ah sa saeh. A khoengim te a sang dong sawmrhuk a ka dong sawmrhuk la saeng.
4 pẹ̀lú ipele òkúta ńlá ńlá mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ àti ipele pákó kan, kí a san owó rẹ̀ láti inú ilé ìṣúra ọba.
Lung nu than thum, thing than at saeh. Hnonah ham te manghai im lamloh pae saeh.
5 Sì jẹ́ kí wúrà àti àwọn ohun èlò fàdákà ti ilé Ọlọ́run, tí Nebukadnessari kó láti ilé Olúwa ní Jerusalẹmu tí ó sì kó lọ sí Babeli, di dídápadà sí ààyè wọn nínú tẹmpili ní Jerusalẹmu; kí a kó wọn sí inú ilé Ọlọ́run.
Pathen im hnopai pataeng sui khaw cak khaw, Nebukhadnezzar loh Jerusalem bawkim lamkah a loh tih Babylon la a khuen te mael saeh lamtah Jerusalem kah bawkim te amah hmuen la paan saeh lamtah Pathen im ah khueh laeh? a ti nah.
6 Nítorí náà, kí ìwọ, Tatenai baálẹ̀ agbègbè Eufurate àti Ṣetar-bosnai àti àwọn ẹlẹgbẹ́ yín, àwọn ìjòyè ti agbègbè náà kúrò níbẹ̀.
Tattenai, sok paem boei Shetharboznai neh sok paem kah a boei hui rhoek te lamloh val om laeh saeh.
7 Ẹ fi iṣẹ́ ilé Ọlọ́run yìí lọ́rùn sílẹ̀ láì dí i lọ́wọ́. Ẹ jẹ́ kí baálẹ̀ àwọn Júù àti àwọn àgbàgbà Júù tún ilé Ọlọ́run yín kọ́ sí ipò rẹ̀.
Pathen im kah imsak nen he hlah uh laeh. Yahudi boei neh Yahudi a hamca rhoek loh Pathen im he amah hmuen la sa uh saeh.
8 Síwájú sí i, mo pàṣẹ ohun tí ẹ gbọdọ̀ ṣe fún àwọn àgbàgbà Júù wọ̀nyí lórí kíkọ́ ilé Ọlọ́run yìí. Gbogbo ìnáwó àwọn ọkùnrin yìí ni kí ẹ san lẹ́kùnrẹ́rẹ́ lára ìṣúra ti ọba, láti ibi àkójọpọ̀ owó ìlú ti agbègbè Eufurate kí iṣẹ́ náà má bà dúró.
Yahudi a hamca rhoek taengah na saii uh ham te kai lamloh saithainah om coeng tih Pathen im he sa saeh. Te vaengah manghai koe lamloh sok paem mangmu lamkah tluem tluem hnonah saeh. Hlang rhoek taengah pae saeh lamtah paa boel saeh.
9 Ohunkóhun tí wọ́n bá fẹ́—àwọn ọ̀dọ́ akọ màlúù, àwọn àgbò, ọ̀dọ́-àgùntàn fún ẹbọ sísun sí Ọlọ́run ọ̀run, àti jéró, iyọ̀, wáìnì àti òróró, bí àwọn àlùfáà ní Jerusalẹmu ti béèrè ni ẹ gbọdọ̀ fún wọn lójoojúmọ́ láìyẹ̀.
A ngoe te tah vaan Pathen taengah hmueihhlutnah vaito ca neh tutal khaw tuca khaw, cangyen, lungkaehtael, misurtui neh situi khaw Jerusalem kah khosoih rhoek loh a hoe bangla a hnin, a hnin ah amih te dalrhanah om kolla pae.
10 Kí wọn lè rú àwọn ẹbọ tí ó tẹ́ Ọlọ́run ọ̀run lọ́rùn kí wọ́n sì gbàdúrà fún àlàáfíà ọba àti àwọn ọmọ rẹ̀.
Vaan pathen taengah hlihlim neh a nawn la om uh saeh lamtah manghai neh a ca rhoek kah hingnah ham thangthui saeh.
11 Síwájú sí i, mo pàṣẹ pé tí ẹnikẹ́ni bá yí àṣẹ yìí padà, kí fa igi àjà ilé rẹ̀ yọ jáde, kí a sì gbe dúró, kí a sì fi òun náà kọ́ sí orí rẹ̀ kí ó wo ilé rẹ̀ palẹ̀ a ó sì sọ ọ́ di ààtàn.
Kai lamkah saithainah om tih he ol aka poe hlang boeih tah a im kah rhungsut te phong saeh lamtah a sut phoeiah anih te hoei saeh. Te dongah a im khaw kawnhnawt la om saeh.
12 Kí Ọlọ́run, tí ó ti jẹ́ kí orúkọ rẹ̀ máa gbé ibẹ̀, kí ó pa gbogbo ọba àti orílẹ̀-èdè rún tí ó bá gbé ọwọ́ sókè láti yí àṣẹ yìí padà tàbí láti wó tẹmpili yìí tí ó wà ní Jerusalẹmu run. Èmi Dariusi n pàṣẹ rẹ̀, jẹ́ kí ó di mímúṣẹ láìyí ohunkóhun padà.
Pathen loh amah ming a khueh thil Jerusalem kah Pathen im he hoilae ham neh palet ham a kut a thueng boeih tah manghai neh pilnam khaw palet van saeh. Kai Darius kah saithainah ka khueh he tluem tluem saii saeh,” a ti.
13 Nígbà náà, nítorí àṣẹ tí ọba Dariusi pa, Tatenai, baálẹ̀ ti agbègbè Eufurate, àti Ṣetar-bosnai pẹ̀lú àwọn ẹlẹgbẹ́ wọn pa á mọ́ láìyí ọ̀kan padà.
Sok paem boei Tattenai, Shetharboznai neh a hui rhoek long khaw manghai Darius kah a pat bangla tluem tluem a saii uh.
14 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn àgbàgbà Júù tẹ̀síwájú wọ́n sì ń gbèrú sí i lábẹ́ ìwàásù wòlíì Hagai àti wòlíì Sekariah, ìran Iddo. Wọ́n parí kíkọ́ ilé Olúwa gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí Ọlọ́run Israẹli àti àwọn àṣẹ Kirusi, Dariusi àti Artasasta àwọn ọba Persia pọ̀.
Yahudi a hamca rhoek khaw a sak uh vaengah tonghma Haggai neh Iddo capa Zekhariah kah olphong dongah thaihtak uh. Persia manghai Cyrus, Darius neh Artaxerxes lamkah saithainah dongkah Israel Pathen kah saithainah bangla a sak uh tih a coeng uh.
15 A parí ilé Olúwa ní ọjọ́ kẹta, oṣù Addari tí í se oṣù kejì ní ọdún kẹfà ti ìjọba ọba Dariusi.
Te dongah manghai Darius ram kah a kum rhuk, Adar hla, hnin thum hlan ah im te a coeng.
16 Nígbà náà ni àwọn ènìyàn Israẹli—àwọn àlùfáà, àwọn Lefi àti àwọn ìgbèkùn tí ó padà, ṣe ayẹyẹ yíya ilé Ọlọ́run sí mímọ́ pẹ̀lú ayọ̀.
Te dongah Israel ca rhoek, khosoih rhoek neh Levi rhoek, hlangsol ca rhoek boeih loh Pathen im nawnnah he kohoenah neh a saii uh.
17 Fún yíya ilé Ọlọ́run yìí sí mímọ́, wọ́n pa ọgọ́rùn-ún akọ màlúù, igba àgbò àti irinwó akọ ọ̀dọ́-àgùntàn, àti gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹ̀ṣẹ̀ fún gbogbo Israẹli, àgbò méjìlá, ọ̀kọ̀ọ̀kan fún olúkúlùkù àwọn ẹ̀yà Israẹli.
Te vaengah Pathen im nawnnah ham te vaito yakhat, tutal yakhat, tuca ya li, boirhaem dongkah ham boirhaem maae tal khaw a nawn uh. Israel pum hlai nit ham te Israel koca kah hlangmi tarhing la a nawnuh.
18 Wọ́n sì fi àwọn àlùfáà sí àwọn ìpín wọ́n àti àwọn Lefi sì ẹgbẹẹgbẹ́ wọn fún ìsin ti Ọlọ́run ní Jerusalẹmu, gẹ́gẹ́ bí ohun tí a kọ sínú ìwé Mose.
Moses cabu dongkah cadaek bangla Jerusalem kah Pathen imsak dongah khosoih rhoek khaw amah boelnah neh, Levi khaw amah tarhoi neh a pai sakuh.
19 Ní ọjọ́ kẹrìnlá ti oṣù Nisani, àwọn tí a kó ní ìgbèkùn ṣe ayẹyẹ àjọ ìrékọjá.
Tedae vangsawn koca rhoek loh hla khat hnin hlai li vaengah Yoom te a saii uh.
20 Àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi ti ya ara wọn sí mímọ́, wọ́n sì jẹ́ mímọ́. Àwọn ará Lefi pa ọ̀dọ́-àgùntàn ti àjọ ìrékọjá fún gbogbo àwọn tí a kó ní ìgbèkùn, fún àwọn àlùfáà arákùnrin wọn àti fún ara wọn.
Khosoih rhoek neh Levi rhoek loh pakhat la caihcil uh tih amih te boeih a cim phoeiah tah vangsawn ca boeih ham khaw, a manuca khosoih ham khaw amamih ham Yoom a ngawn uh.
21 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli tí ó ti dé láti ìgbèkùn jẹ ẹ́ lápapọ̀ pẹ̀lú gbogbo àwọn tí ó ti ya ara wọn kúrò nínú gbogbo iṣẹ́ àìmọ́ ti àwọn kèfèrí aládùúgbò wọn láti wá Olúwa Ọlọ́run Israẹli.
Te vaengah vangsawn lamkah aka mael Israel ca rhoek neh a kaepvai khohmuen kah namtom tihnai khui lamloh Israel Pathen BOEIPA te toem ham aka hoep uh boeih loh a caak uh.
22 Fún ọjọ́ méje, wọ́n ṣe ayẹyẹ àkàrà àìwú pẹ̀lú àjẹtì àkàrà. Nítorí tí Olúwa ti kún wọn pẹ̀lú ayọ̀ nípa yíyí ọkàn ọba Asiria padà, tí ó fi ràn wọ́n lọ́wọ́ lórí iṣẹ́ ilé Ọlọ́run, Ọlọ́run Israẹli.
Vaidamding khotue khaw hnin rhih khuiah kohoenah neh a saii uh. Israel Pathen kah Pathen im bitat dongah amih kut te moem pah ham Assyria manghai loh amih taengah lungbuei a tho dongah BOEIPA loh amih te ko a hoe sak.

< Ezra 6 >