< Ezra 2 >

1 Lákòókò náà, wọ̀nyí ni àwọn ènìyàn agbègbè Juda tí ó gòkè wá láti ìgbèkùn láàrín àwọn tí a kó lọ, ẹni tí Nebukadnessari ọba Babeli ti fi agbára mú ní ìgbèkùn lọ sí Babeli (wọ́n padà sí Jerusalẹmu àti Juda, olúkúlùkù sí ìlú rẹ̀.
A cić są ludzie onej krainy, którzy wyszli z pojmania i z niewoli, w którą ich był zaprowadził Nabuchodonozor, król Babiloński, do Babilonu, a wrócili się do Jeruzalemu i do Judy, każdy do miasta swego.
2 Àwọn wọ̀nyí bá Serubbabeli, Jeṣua, Nehemiah, Seraiah, Reelaiah, Mordekai, Bilṣani, Mispari, Bigfai, Rehumu àti Baanah wá). Iye àwọn ọkùnrin àwọn ènìyàn Israẹli.
Którzy przyszli z Zorobabelem, z Jesuą, Nehemijaszem, Sarajaszem, Rehelijaszem, Mardocheuszem, Bilsanem, Misparem Bigwajem, Rechumem, i Baaną. A poczet ludu Izraelskiego ten był:
3 Àwọn ọmọ Paroṣi jẹ́ ẹgbàá ó lé méjìléláàádọ́sàn-án
Synów Farosowych dwa tysiące sto siedmdziesiąt i dwa;
4 Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá
Synów Sefatyjaszowych trzy sta siedmdziesiąt i dwa;
5 Arah jẹ́ ẹgbẹ̀rin ó dín mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n
Synów Arachowych siedm set siedmdziesiąt i pięć;
6 Pahati-Moabu (láti ipasẹ̀ àwọn ọmọ Jeṣua àti Joabu) jẹ́ ẹgbẹ̀rún méjì àti ẹgbẹ̀rin lé méjìlá
Synów Pachat Moabowych, synów Jesui Joabowych dwa tysiące ośm set i dwanaście;
7 Elamu jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀fà ó lé mẹ́rin
synów Elamowych tysiąc dwieście pięćdziesiąt i cztery;
8 Sattu jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rún ó lé márùn-ún
Synów Zatuowych dziewięć set i czterdzieści i pięć;
9 Sakkai jẹ́ òjìdínlẹ́gbẹ̀rin
Synów Zachajowych siedm set i sześćdziesiąt;
10 Bani jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀ta ó lé méjì
Synów Bani sześć set czterdzieści i dwa;
11 Bebai jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mẹ́tàlélógún
Synów Bebajowych sześć set dwadzieścia i trzy.
12 Asgadi jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé méjìlélógún
Synów Azgadowych tysiąc dwieście dwadzieścia i dwa.
13 Adonikami jẹ́ ọ̀tàlélẹ́gbẹ̀ta ó lé mẹ́fà
Synów Adonikamowych sześć set sześćdziesiąt i sześć;
14 Bigfai jẹ́ ẹgbàá ó lé mẹ́rìndínlọ́gọ́ta
Synów Bigwajowych dwa tysiące pięćdziesiąt i sześć;
15 Adini jẹ́ àádọ́ta lé ní irinwó ó lé mẹ́rin
Synów Adynowych cztery sta pięćdziesiąt i cztery.
16 Ateri (nípasẹ̀ Hesekiah) jẹ́ méjìdínlọ́gọ́run
Synów Aterowych, co poszli z Ezechyjasza, dziewięćdziesiąt i ośm;
17 Besai jẹ́ ọrùndínnírinwó ó lé mẹ́ta
Synów Besajowych trzy sta dwadzieścia i trzy.
18 Jora jẹ́ méjìléláàádọ́fà
Synów Jory sto i dwanaście;
19 Haṣumu jẹ́ igba ó lé mẹ́tàlélógún
Synów Hasumowych dwieście dwadzieścia i trzy.
20 Gibbari jẹ́ márùndínlọ́gọ́rùn.
Synów Gibbarowych dziewięćdziesiat i pięć;
21 Àwọn ọmọ Bẹtilẹhẹmu jẹ́ mẹ́tàlélọ́gọ́fà
Synów z Betlehemu sto dwadzieścia i trzy;
22 Netofa jẹ́ mẹ́rìndínlọ́gọ́ta
Mężów z Netofatu pięćdziesiąt i sześć;
23 Anatoti jẹ́ méjìdínláàádóje
Mężów z Anatotu sto dwadzieścia i ośm;
24 Asmafeti jẹ́ méjìlélógójì
Synów z Azmawetu czterdzieści i dwa;
25 Kiriati-Jearimu, Kefira àti Beeroti jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó lé mẹ́ta
Synów z Karyjatyjarymu, z Kafiry i z Beerotu siedm set i czterdzieści i trzy;
26 Rama àti Geba jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mọ́kànlélógún
Synów z Ramy i z Gabaa sześć set dwadzieścia i jeden;
27 Mikmasi jẹ́ méjìlélọ́gọ́fà
Mężów z Machmas sto dwadzieścia i dwa;
28 Beteli àti Ai jẹ́ igba ó lé mẹ́tàlélógún
Mężów z Betela i z Haj dwieście dwadzieścia i trzy;
29 Nebo jẹ́ méjìléláàádọ́ta
Synów z Nebo pięćdziesiąt i dwa;
30 Magbiṣi jẹ́ mẹ́rìndínlọ́gọ́jọ
Synów Magbisowych sto pięćdziesiąt i sześć;
31 Elamu mìíràn jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́rìnléláàádọ́ta
Synów Elama drugiego tysiąc dwieście pięćdziesiąt i cztery;
32 Harimu jẹ́ ọ̀rìndínnírinwó.
Synów Harymowych trzy sta i dwadzieścia;
33 Lodi, Hadidi àti Ono jẹ́ ọ̀rìndínlẹ́gbẹ̀rin ó lé márùn-ún
Synów Lodowych, Hadydowych, i Onowych siedm set dwadzieścia i pięć;
34 Jeriko jẹ́ ọ̀tàdínnírinwó ó lé márùn-ún
Synów Jerechowych trzy sta czterdzieści i pięć;
35 Senaa jẹ́ egbèji dín lógún ó lé ọgbọ̀n.
Synów Senaa trzy tysiące i sześć set i trzydzieści.
36 Àwọn àlùfáà. Àwọn ọmọ Jedaiah (láti ipasẹ̀ ìdílé Jeṣua) jẹ́ ogún dín lẹ́gbẹ̀rin ó dín méje
Kapłanów: Synów Jedajaszowych z domu Jesui, dziewięć set siedmdziesiąt i trzy;
37 Immeri jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀rún ó lé méjì
Synów Immerowych tysiąc pięćdziesiąt i dwa;
38 Paṣuri jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́tàdínláàádọ́ta
Synów Pashurowych tysiąc dwieście czterdzieści i siedm;
39 Harimu jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó lé mẹ́tàdínlógún.
Synów Harymowych tysiąc i siedmnaście.
40 Àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ọmọ Jeṣua àti Kadmieli (ti ìdílé Hodafiah) jẹ́ mẹ́rìnléláàádọ́rin.
Lewitów: synów Jesui i Kadmiela, synów Hodawyjaszowych siedmdziesiąt i cztery.
41 Àwọn akọrin. Àwọn ọmọ Asafu jẹ́ méjìdínláàádóje.
Śpiewaków: synów Asafowych sto dwadzieścia i ośm.
42 Àwọn aṣọ́bodè. Àwọn ará Ṣallumu, Ateri, Talmoni, Akkubu, Hatita àti Ṣobai jẹ́ mọ́kàndínlógóje.
Synów odźwiernych: synów Sallumowych, synów Aterowych, synów Talmonowych, synów Akkubowych, synów Hatytowych, synów Sobajowych, wszystkich sto trzydzieści i dziewięć.
43 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili. Àwọn ọmọ. Siha, Hasufa, Tabboati,
Z Netynejczyków: synów Sycha, synów Chasufa, synów Tabbaota,
44 Kerosi, Siaha, Padoni,
Synów Kierosa, synów Syaa, synów Fadona,
45 Lebana, Hagaba, Akkubu,
Synów Lebana, synów Hagaba,
46 Hagabu, Ṣalmai, Hanani,
Synów Akkuba, synów Hagaba, synów Salmaja, synów Hanana,
47 Giddeli, Gahari, Reaiah,
Synów Gieddela, synów Gachera, synów Reajasza,
48 Resini, Nekoda, Gassamu,
Synów Rezyna, synów Nekoda, synów Gazama,
49 Ussa, Pasea, Besai,
Synów Uzy, synów Fasejacha, synów Besaja,
50 Asna, Mehuni, Nefisimu,
Synów Asena, synów Mehunima, synów Nefusyma;
51 Bakbu, Hakufa, Harhuri.
Synów Bakbuka, synów Chakufa, synów Charchura,
52 Basluti, Mehida, Harṣa,
Synów Basluta, synów Mechyda, synów Charsa,
53 Barkosi, Sisera, Tema,
Synów Barkosa, synów Sysera, synów Tamacha,
54 Nesia àti Hatifa.
Synów Nezyjacha, synów Chatyfa,
55 Àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni. Àwọn ọmọ Sotai, Sofereti, Peruda,
Synów sług Salomonowych, synów Sotaja, synów Sofereta, synów Peruda,
56 Jaala, Darkoni, Giddeli,
Synów Jahala, synów Darkona, synów Giddela,
57 Ṣefatia, àwọn ọmọ Hattili, Pokereti ti Haṣebaimu àti àwọn ọmọ Ami.
Synów Sefatyjasza, synów Chatyla, synów Pocheret Hasebaim, synów Ami;
58 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni jẹ́ irinwó ó dín mẹ́jọ.
Wszystkich Netynejczyków, i synów sług Salomonowych trzy sta dziewięćdziesiąt i dwa.
59 Àwọn wọ̀nyí gòkè wá láti àwọn ìlú ti Teli-Mela, Teli-Harṣa, Kerubu, Addoni àti Immeri, ṣùgbọ́n wọn kò lè sọ pẹ̀lú ìdánilójú pé ìdílé àwọn wá láti ara ìran ẹ̀yà Israẹli.
Ci też zasię wyszli z Telmelachu: Telcharsa, Cherub, Addam i Immer; ale nie mogli okazać domu ojców swoich, i nasienia swego, jeźli z Izraela byli.
60 Àwọn ọmọ Delaiah, Tobiah àti Nekoda jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀ta ó lé méjì.
Synów Delajaszowych, synów Tobijaszowych, synów Nekodowych, sześć set pięćdziesiąt i dwa.
61 Àti nínú àwọn ọmọ àwọn àlùfáà. Àwọn ọmọ: Hobaiah, Hakosi àti Barsillai (ọkùnrin tí ó fẹ́ ọmọbìnrin Barsillai ará Gileadi a sì ń fi orúkọ náà pè é).
A synów kapłańskich: synowie Habajowi, synowie Kozowi, synowie Barsylajego, który był pojął żonę z córek Barsylaja Galaadczyka; i nazwany był od imienia ich.
62 Àwọn wọ̀nyí wá ìwé ìrántí ìdílé wọn, ṣùgbọ́n wọn kò rí i, bẹ́ẹ̀ ni a kò kà wọ́n kún ara àlùfáà nítorí, a kà wọ́n sí aláìmọ́.
Ci szukali opisania rodu swego, ale nie znaleźli; przetoż zrzuceni są z kapłaństwa.
63 Baálẹ̀ pa á láṣẹ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ jẹ nínú oúnjẹ mímọ́ jùlọ títí tí àlùfáà kan yóò fi ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú Urimu àti Tumimu.
I zakazał im Tyrsata, aby nie jadali z rzeczy najświętszych, ażby powstał kapłan z Urym i z Tummim.
64 Gbogbo ìjọ ènìyàn náà jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélógún ó lé òjìdínnírinwó.
Wszystkiego zgromadzenia było w jednym poczcie cztredzieści tysięcy dwa tysiące trzy sta i sześćdziesiąt;
65 Yàtọ̀ sí ẹgbẹ̀rin dín lẹ́gbàárin ó dín mẹ́tàlélọ́gọ́ta ìránṣẹ́ ọkùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin; wọ́n ní igba akọrin ọkùnrin àti obìnrin.
Oprócz sług ich, i służebnic ich, których było siedm tysięcy trzy sta trzydzieści i siedm, a między nimi było śpiewaków i śpiewaczek dwieście.
66 Wọ́n ní ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́rin ẹṣin; ìbáaka òjìlélúgba ó lé márùn-ún,
Koni ich siedm set trzydzieści i sześć; mułów ich dwieście czterdziści i pięć.
67 ràkunmí jẹ́ irinwó ó lé márùndínlógójì àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹgbẹ̀rin lé lọ́gbọ̀n ó dín ọgọ́rin.
Wielbłądów ich cztery sta trzydzieści i pięć; osłów sześć tysięcy siedm set i dwadzieścia.
68 Ní ìgbà tí wọ́n dé ilé Olúwa ní Jerusalẹmu, díẹ̀ nínú àwọn olórí àwọn ìdílé fi ọrẹ àtinúwá sílẹ̀ fún ṣíṣe àtúnkọ́ ilé Ọlọ́run ní ààyè rẹ̀.
A niektórzy z książąt domów ojcowskich przyszli do domu Pańskiego, który był w Jeruzalemie, ofiarowawszy się dobrowolnie, aby budowali dom Boży na miejscu jego.
69 Gẹ́gẹ́ bí agbára wọn, wọ́n fún ilé ìṣúra fún iṣẹ́ yìí ní ọ̀kẹ́ mẹ́ta ó lé lẹ́gbẹ̀rún ìwọ̀n dariki wúrà, ẹgbẹ̀rún márùn-ún fàdákà àti ọgọ́rùn-ún ẹ̀wù àlùfáà.
Według przemożenia swego dali nakład na budowanie: złota łótów sześćdziesiąt tysięcy i jeden, a srebra grzywien pięć tysięcy, i szat kapłańskich sto.
70 Àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi, àwọn akọrin, àwọn aṣọ́bodè àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa ṣe àtìpó sínú àwọn ìlú wọn, pẹ̀lú àwọn ènìyàn mìíràn, àti ìyókù àwọn ọmọ Israẹli ṣe àtìpó sínú ìlú u wọn.
A tak osadzili się kapłani i Lewitowie, i niektórzy z ludu, i śpiewacy, i odźwierni, i Netynejczycy w miastach swych, i wszystek Izrael w miastach swych.

< Ezra 2 >