< Ezra 2 >

1 Lákòókò náà, wọ̀nyí ni àwọn ènìyàn agbègbè Juda tí ó gòkè wá láti ìgbèkùn láàrín àwọn tí a kó lọ, ẹni tí Nebukadnessari ọba Babeli ti fi agbára mú ní ìgbèkùn lọ sí Babeli (wọ́n padà sí Jerusalẹmu àti Juda, olúkúlùkù sí ìlú rẹ̀.
Dies sind die Kinder aus den Landen, die heraufzogen aus dem Gefängnis, die Nebukadnezar, der König zu Babel, hatte gen Babel geführet, und wieder gen Jerusalem und nach Juda kamen, ein jeglicher in seine Stadt.
2 Àwọn wọ̀nyí bá Serubbabeli, Jeṣua, Nehemiah, Seraiah, Reelaiah, Mordekai, Bilṣani, Mispari, Bigfai, Rehumu àti Baanah wá). Iye àwọn ọkùnrin àwọn ènìyàn Israẹli.
Und kamen mit Serubabel, Jesua, Nehemia, Seraja, Reelja, Mardochai, Bilsan, Mispar, Bigevai, Rehum und Baena. Dies ist nun die Zahl der Männer des Volks Israel:
3 Àwọn ọmọ Paroṣi jẹ́ ẹgbàá ó lé méjìléláàádọ́sàn-án
der Kinder Pareos zweitausend hundert und zweiundsiebenzig;
4 Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá
der Kinder Sephatja dreihundert und zweiundsiebenzig;
5 Arah jẹ́ ẹgbẹ̀rin ó dín mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n
der Kinder Arah, siebenhundert und fünfundsiebenzig;
6 Pahati-Moabu (láti ipasẹ̀ àwọn ọmọ Jeṣua àti Joabu) jẹ́ ẹgbẹ̀rún méjì àti ẹgbẹ̀rin lé méjìlá
der Kinder Pahath-Moab, unter der Kindern Jesua, Joab, zweitausend achthundert und zwölf;
7 Elamu jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀fà ó lé mẹ́rin
der Kinder Elam tausend zweihundert und vierundfünfzig;
8 Sattu jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rún ó lé márùn-ún
der Kinder Sathu neunhundert und fünfundvierzig;
9 Sakkai jẹ́ òjìdínlẹ́gbẹ̀rin
der Kinder Sakai siebenhundert und sechzig;
10 Bani jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀ta ó lé méjì
der Kinder Bani sechshundert und zweiundvierzig;
11 Bebai jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mẹ́tàlélógún
der Kinder Bebai sechshundert und dreiundzwanzig;
12 Asgadi jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé méjìlélógún
der Kinder Asgad tausend zweihundert und zweiundzwanzig;
13 Adonikami jẹ́ ọ̀tàlélẹ́gbẹ̀ta ó lé mẹ́fà
der Kinder Adonikam sechshundert und sechsundsechzig;
14 Bigfai jẹ́ ẹgbàá ó lé mẹ́rìndínlọ́gọ́ta
der Kinder Bigevai zweitausend und sechsundfünfzig;
15 Adini jẹ́ àádọ́ta lé ní irinwó ó lé mẹ́rin
der Kinder Adin vierhundert und vierundfünfzig;
16 Ateri (nípasẹ̀ Hesekiah) jẹ́ méjìdínlọ́gọ́run
der Kinder Ater von Hiskia achtundneunzig;
17 Besai jẹ́ ọrùndínnírinwó ó lé mẹ́ta
der Kinder Bezai dreihundert und dreiundzwanzig;
18 Jora jẹ́ méjìléláàádọ́fà
der Kinder Jorah hundert und zwölf
19 Haṣumu jẹ́ igba ó lé mẹ́tàlélógún
der Kinder Hasum zweihundert und dreiundzwanzig;
20 Gibbari jẹ́ márùndínlọ́gọ́rùn.
der Kinder Gibbar fünfundneunzig;
21 Àwọn ọmọ Bẹtilẹhẹmu jẹ́ mẹ́tàlélọ́gọ́fà
der Kinder Beth-Lehem hundert und dreiundzwanzig;
22 Netofa jẹ́ mẹ́rìndínlọ́gọ́ta
der Männer Netopha sechsundfünfzig;
23 Anatoti jẹ́ méjìdínláàádóje
der Männer von Anathoth hundert und achtundzwanzig;
24 Asmafeti jẹ́ méjìlélógójì
der Kinder Asmaveth zweiundvierzig;
25 Kiriati-Jearimu, Kefira àti Beeroti jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó lé mẹ́ta
der Kinder von Kiriath-Arim, Kaphira und Beeroth siebenhundert und dreiundvierzig;
26 Rama àti Geba jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mọ́kànlélógún
der Kinder von Rama und Gaba sechshundert und einundzwanzig;
27 Mikmasi jẹ́ méjìlélọ́gọ́fà
der Männer von Michmas hundert und zweiundzwanzig;
28 Beteli àti Ai jẹ́ igba ó lé mẹ́tàlélógún
der Männer von Bethel und Ai zweihundert und dreiundzwanzig;
29 Nebo jẹ́ méjìléláàádọ́ta
der Kinder Nebo zweiundfünfzig;
30 Magbiṣi jẹ́ mẹ́rìndínlọ́gọ́jọ
der Männer von Magbis hundert und sechsundfünfzig;
31 Elamu mìíràn jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́rìnléláàádọ́ta
der Kinder des andern Elam tausend zweihundert und vierundfünfzig;
32 Harimu jẹ́ ọ̀rìndínnírinwó.
der Kinder Harim dreihundert und zwanzig;
33 Lodi, Hadidi àti Ono jẹ́ ọ̀rìndínlẹ́gbẹ̀rin ó lé márùn-ún
der Kinder Lod, Hadid und Ono siebenhundert und fünfundzwanzig;
34 Jeriko jẹ́ ọ̀tàdínnírinwó ó lé márùn-ún
der Kinder Jereho dreihundert und fünfundvierzig;
35 Senaa jẹ́ egbèji dín lógún ó lé ọgbọ̀n.
der Kinder Senaa dreitausend sechshundert und dreißig;
36 Àwọn àlùfáà. Àwọn ọmọ Jedaiah (láti ipasẹ̀ ìdílé Jeṣua) jẹ́ ogún dín lẹ́gbẹ̀rin ó dín méje
der Priester: der Kinder Jedaja vom Hause Jesua neunhundert und dreiundsiebenzig;
37 Immeri jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀rún ó lé méjì
der Kinder Immer tausend und zweiundfünfzig;
38 Paṣuri jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́tàdínláàádọ́ta
der Kinder Pashur tausend zweihundert und siebenundvierzig;
39 Harimu jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó lé mẹ́tàdínlógún.
der Kinder Harim tausend und siebenzehn;
40 Àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ọmọ Jeṣua àti Kadmieli (ti ìdílé Hodafiah) jẹ́ mẹ́rìnléláàádọ́rin.
der Leviten: der Kinder Jesua und Kadmiel von den Kindern Hodavja vierundsiebenzig;
41 Àwọn akọrin. Àwọn ọmọ Asafu jẹ́ méjìdínláàádóje.
der Sänger: der Kinder Assaph hundert und achtundzwanzig;
42 Àwọn aṣọ́bodè. Àwọn ará Ṣallumu, Ateri, Talmoni, Akkubu, Hatita àti Ṣobai jẹ́ mọ́kàndínlógóje.
der Kinder der Torhüter: die Kinder Sallum, die Kinder Ater, die Kinder Talmon, die Kinder Akub, die Kinder Hatita und die Kinder Sobai, allesamt hundert und neununddreißig;
43 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili. Àwọn ọmọ. Siha, Hasufa, Tabboati,
der Nethinim: die Kinder Ziha, die Kinder Hasupha, die Kinder Tabaoth,
44 Kerosi, Siaha, Padoni,
die Kinder Keros, die Kinder Sieha, die Kinder Padon,
45 Lebana, Hagaba, Akkubu,
die Kinder Lebana, die Kinder Hagaba, die Kinder Akub,
46 Hagabu, Ṣalmai, Hanani,
die Kinder Hagab, die Kinder Samlai, die Kinder Hanan,
47 Giddeli, Gahari, Reaiah,
die Kinder Giddel, die Kinder Gahar, die Kinder Reaja,
48 Resini, Nekoda, Gassamu,
die Kinder Rezin, die Kinder Nekoda, die Kinder Gasam,
49 Ussa, Pasea, Besai,
die Kinder Usa, die Kinder Paseah, die Kinder Besai,
50 Asna, Mehuni, Nefisimu,
die Kinder Asna, die Kinder Meunim, die Kinder Nephusim,
51 Bakbu, Hakufa, Harhuri.
die Kinder Bakbuk, die Kinder Hakupha, die Kinder Harhur,
52 Basluti, Mehida, Harṣa,
die Kinder Bazeluth, die Kinder Mehida, die Kinder Harsa,
53 Barkosi, Sisera, Tema,
die Kinder Barkom, die Kinder Sissera, die Kinder Thamah,
54 Nesia àti Hatifa.
die Kinder Neziah, die Kinder Hatipha;
55 Àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni. Àwọn ọmọ Sotai, Sofereti, Peruda,
die Kinder der Knechte Salomos: die Kinder Sotai, die Kinder Sophereth, die Kinder Pruda,
56 Jaala, Darkoni, Giddeli,
die Kinder Jaela, die Kinder Darkon, die Kinder Giddel,
57 Ṣefatia, àwọn ọmọ Hattili, Pokereti ti Haṣebaimu àti àwọn ọmọ Ami.
die Kinder Sephatja, die Kinder Hattil, die Kinder Pochereth von Zebaim, die Kinder Ami.
58 Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni jẹ́ irinwó ó dín mẹ́jọ.
Aller Nethinim und Kinder der Knechte Salomos waren zusammen dreihundert und zweiundneunzig.
59 Àwọn wọ̀nyí gòkè wá láti àwọn ìlú ti Teli-Mela, Teli-Harṣa, Kerubu, Addoni àti Immeri, ṣùgbọ́n wọn kò lè sọ pẹ̀lú ìdánilójú pé ìdílé àwọn wá láti ara ìran ẹ̀yà Israẹli.
Und diese zogen auch mit herauf: Mithel, Melah, Thel-Harsa, Cherub-Addon und Immer; aber sie konnten nicht anzeigen ihrer Väter Haus, noch ihren Samen, ob sie aus Israel wären.
60 Àwọn ọmọ Delaiah, Tobiah àti Nekoda jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀ta ó lé méjì.
Die Kinder Delaja, die Kinder Tobia, die Kinder Nekoda: sechshundert und zweiundfünfzig.
61 Àti nínú àwọn ọmọ àwọn àlùfáà. Àwọn ọmọ: Hobaiah, Hakosi àti Barsillai (ọkùnrin tí ó fẹ́ ọmọbìnrin Barsillai ará Gileadi a sì ń fi orúkọ náà pè é).
Und von den Kindern der Priester: die Kinder Habaja, die Kinder Hakoz, die Kinder Barsillai, der aus den Töchtern Barsillais, des Gileaditers, ein Weib nahm und ward unter derselben Namen genannt.
62 Àwọn wọ̀nyí wá ìwé ìrántí ìdílé wọn, ṣùgbọ́n wọn kò rí i, bẹ́ẹ̀ ni a kò kà wọ́n kún ara àlùfáà nítorí, a kà wọ́n sí aláìmọ́.
Dieselben suchten ihre Geburtsregister und fanden keine; darum wurden sie vom Priestertum los.
63 Baálẹ̀ pa á láṣẹ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ jẹ nínú oúnjẹ mímọ́ jùlọ títí tí àlùfáà kan yóò fi ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú Urimu àti Tumimu.
Und Hathirsatha sprach zu ihnen, sie sollten nicht essen vom Allerheiligsten, bis ein Priester stünde mit dem Licht und Recht.
64 Gbogbo ìjọ ènìyàn náà jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélógún ó lé òjìdínnírinwó.
Der ganzen Gemeine, wie ein Mann, war zweiundvierzigtausend dreihundert und sechzig,
65 Yàtọ̀ sí ẹgbẹ̀rin dín lẹ́gbàárin ó dín mẹ́tàlélọ́gọ́ta ìránṣẹ́ ọkùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin; wọ́n ní igba akọrin ọkùnrin àti obìnrin.
ausgenommen ihre Knechte und Mägde, der waren siebentausend dreihundert, und siebenunddreißig. Und hatten zweihundert Sänger und Sängerinnen,
66 Wọ́n ní ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́rin ẹṣin; ìbáaka òjìlélúgba ó lé márùn-ún,
siebenhundert und sechsunddreißig Rosse, zweihundert und fünfundvierzig Mäuler,
67 ràkunmí jẹ́ irinwó ó lé márùndínlógójì àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹgbẹ̀rin lé lọ́gbọ̀n ó dín ọgọ́rin.
vierhundert und fünfunddreißig Kamele und sechstausend siebenhundert und zwanzig Esel.
68 Ní ìgbà tí wọ́n dé ilé Olúwa ní Jerusalẹmu, díẹ̀ nínú àwọn olórí àwọn ìdílé fi ọrẹ àtinúwá sílẹ̀ fún ṣíṣe àtúnkọ́ ilé Ọlọ́run ní ààyè rẹ̀.
Und etliche der obersten Väter, da sie kamen zum Hause des HERRN zu Jerusalem, wurden sie freiwillig zum Hause Gottes, daß man es setzte auf seine Stätte.
69 Gẹ́gẹ́ bí agbára wọn, wọ́n fún ilé ìṣúra fún iṣẹ́ yìí ní ọ̀kẹ́ mẹ́ta ó lé lẹ́gbẹ̀rún ìwọ̀n dariki wúrà, ẹgbẹ̀rún márùn-ún fàdákà àti ọgọ́rùn-ún ẹ̀wù àlùfáà.
Und gaben nach ihrem Vermögen zum Schatz ans Werk einundsechzigtausend Gülden und fünftausend Pfund Silbers und hundert Priesterröcke.
70 Àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi, àwọn akọrin, àwọn aṣọ́bodè àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa ṣe àtìpó sínú àwọn ìlú wọn, pẹ̀lú àwọn ènìyàn mìíràn, àti ìyókù àwọn ọmọ Israẹli ṣe àtìpó sínú ìlú u wọn.
Also setzten sich die Priester und die Leviten und etliche des Volks und die Sänger und die Torhüter und die Nethinim in ihre Städte und alles Israel in seine Städte.

< Ezra 2 >