< Ezra 10 >

1 Nígbà tí Esra ń gbàdúrà tí ó sì ń jẹ́wọ́, ti ó ń sọkún ti ó sì ń gbárayílẹ̀ níwájú ilé Ọlọ́run, ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ Israẹli ọkùnrin, obìnrin àti àwọn ọmọdé pagbo yí i ká. Àwọn náà ń sọkún kíkorò.
Acum, după ce Ezra s-a rugat şi a mărturisit, plângând şi aruncându-se jos înaintea casei lui Dumnezeu, s-a strâns la el din Israel o foarte mare adunare de bărbaţi şi femei şi copii, pentru că poporul plângea foarte tare.
2 Nígbà náà ni Ṣekaniah ọmọ Jehieli, ọ̀kan lára ìran Elamu, sọ fún Esra pé, “Àwa ti jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Ọlọ́run wa nípa fífẹ́ àwọn obìnrin àjèjì láàrín àwọn ènìyàn tí ó wà yí wa ká. Ṣùgbọ́n síbẹ̀ náà, ìrètí sì wà fún Israẹli
Şi Şecania, fiul lui Iehiel, unul dintre fiii lui Elam, a răspuns şi i-a zis lui Ezra: Noi am încălcat legea împotriva Dumnezeului nostru şi am luat soţii străine din poporul ţării; totuşi acum este speranţă în Israel în această privinţă.
3 Nísìnsinyìí, ẹ jẹ́ kí a dá májẹ̀mú níwájú Ọlọ́run wa láti lé àwọn obìnrin yìí àti àwọn ọmọ wọn lọ. Gẹ́gẹ́ bí ìmọ̀ràn Esra olúwa mi àti ti àwọn tí ó bẹ̀rù àṣẹ Olúwa Ọlọ́run wa. Ẹ jẹ́ kí a ṣe gẹ́gẹ́ bí òfin.
De aceea acum, să facem legământ cu Dumnezeul nostru de a pune deoparte toate soţiile şi pe cei care sunt născuţi din ele, conform cu sfatul domnului meu şi al acelora care tremură la porunca Dumnezeului nostru; şi să se facă după lege.
4 Dìde, nítorí, ọ̀rọ̀ tìrẹ ni èyí. Gbogbo wà yóò wá pẹ̀lú rẹ, mú ọkàn le kí o sì ṣe é.”
Ridică-te, pentru că acest lucru îţi aparţine; noi de asemenea vom fi cu tine; încurajează-te şi fă-o.
5 Nígbà náà ni Esra dìde, ó sì fi àwọn aṣíwájú àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi àti gbogbo Israẹli sí abẹ́ ìbúra, láti ṣe ohun tí wọ́n dá lábàá. Wọ́n sì búra.
Atunci s-a ridicat Ezra şi a făcut pe mai marii preoţilor, pe leviţi şi pe tot Israelul să jure că vor face conform cu acest cuvânt. Şi ei au jurat.
6 Nígbà náà ni Esra padà sẹ́yìn kúrò níwájú ilé Ọlọ́run, ó sì lọ sí iyàrá Jehohanani ọmọ Eliaṣibu. Nígbà tí ó wà níbẹ̀, kò jẹ oúnjẹ bẹ́ẹ̀ ni kò sì mu omi, nítorí ó sì ń káàánú fún àìṣòótọ́ àwọn ìgbèkùn.
Atunci Ezra s-a ridicat dinaintea casei lui Dumnezeu şi a mers în camera lui Iohanan, fiul lui Eliaşib; şi după ce a intrat acolo nu a mâncat pâine nici nu a băut apă, pentru că jelea din cauza încălcării legii celor care fuseseră duşi în captivitate.
7 Ìkéde kan jáde lọ jákèjádò Juda àti Jerusalẹmu fún gbogbo àwọn ìgbèkùn láti péjọ sí Jerusalẹmu.
Şi au proclamat în tot Iuda şi Ierusalim către toţi copiii captivităţii, să se adune la Ierusalim;
8 Ẹnikẹ́ni tí ó ba kọ̀ láti jáde wá láàrín ọjọ́ mẹ́ta yóò pàdánù ohun ìní rẹ̀ ní ìbámu pẹ̀lú ìpinnu àwọn ìjòyè àti àwọn àgbàgbà, àti pé a ó lé òun fúnra rẹ̀ jáde kúrò láàrín ìpéjọpọ̀ àwọn ìgbèkùn.
Şi oricine va refuza să vină în trei zile, conform cu sfatul prinţilor şi al bătrânilor, toată averea lui va fi confiscată, iar el însuşi separat de adunarea celor care au fost duşi în captivitate.
9 Láàrín ọjọ́ mẹ́ta náà, gbogbo àwọn ọkùnrin Juda àti Benjamini tí péjọ sí Jerusalẹmu. Ní ogúnjọ́ oṣù kẹsànán, gbogbo àwọn ènìyàn jókòó sí ìta gbangba iwájú ilé Ọlọ́run, wọ́n wà nínú ìbànújẹ́ ńlá nítorí ọ̀ràn yìí, àti nítorí òjò púpọ̀ tó tì rọ̀.
Atunci toţi bărbaţii lui Iuda şi ai lui Beniamin s-au adunat la Ierusalim în trei zile. Era luna a noua, în a douăzecea zi a lunii; şi tot poporul şedea în strada casei lui Dumnezeu, tremurând din cauza acestui lucru şi din cauza ploii mari.
10 Nígbà náà ni àlùfáà Esra dìde, ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ti ṣe àìṣòótọ́, ẹ ti fẹ́ obìnrin àjèjì, ẹ ti dá kún ẹ̀bi Israẹli.
Şi preotul Ezra a stat în picioare şi le-a spus: Aţi încălcat legea şi aţi luat soţii străine, ca să măriţi fărădelegea lui Israel.
11 Nísinsin yìí, ẹ jẹ́wọ́ níwájú Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba yín, kí ẹ sì ṣe ìfẹ́ rẹ̀. Ẹ ya ara yín sọ́tọ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn tí ó yí i yín ká àti láàrín àwọn ìyàwó àjèjì yín.”
De aceea acum, mărturisiți DOMNULUI Dumnezeul părinţilor voştri şi faceţi voia lui; şi separaţi-vă de poporul ţării şi de soţiile străine.
12 Àpéjọpọ̀ ènìyàn náà sì dáhùn lóhùn rara pé, ohun tí ó sọ dára! A gbọdọ̀ ṣe bí o ti wí.
Atunci toată adunarea a răspuns şi a zis cu voce tare: Precum ai spus, astfel trebuie să facem.
13 Ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ ni ó wà ni ibi yìí síbẹ̀ àkókò òjò ni; àwa kò sì lè dúró ní ìta. Yàtọ̀ sí èyí, a kò le è yanjú ọ̀rọ̀ yìí láàrín ọjọ́ kan tàbí ọjọ́ méjì, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa pọ̀ jọjọ lórí àwọn nǹkan wọ̀nyí.
Dar poporul este mult şi este un timp de multă ploaie şi nu putem sta în picioare afară, nici nu este aceasta o lucrare de o zi sau două: pentru că suntem mulţi care am încălcat legea în acest lucru.
14 Jẹ́ kí àwọn ìjòyè wa ṣojú fún gbogbo ìjọ ènìyàn, lẹ́yìn náà, jẹ́ kí ẹnìkọ̀ọ̀kan nínú àwọn ìlú wa tí ó ti fẹ́ obìnrin àjèjì wá ní àsìkò tí a yàn, pẹ̀lú àwọn àgbàgbà àti àwọn onídàájọ́ ìlú kọ̀ọ̀kan, títí ìbínú gíga Ọlọ́run wa lórí ọ̀rọ̀ yìí yóò fi kúrò ní orí wa.
Să se ridice acum în picioare conducătorii noştri ai întregii adunări şi toţi câţi au luat soţii străine în cetăţile noastre să vină la timpuri hotărâte şi cu ei bătrânii fiecărei cetăţi şi judecătorii ei, până când furia înverşunată a Dumnezeului nostru pentru acest lucru se va întoarce de la noi.
15 Jonatani ọmọ Asaheli àti Jahseiah ọmọ Tikfa nìkan pẹ̀lú àtìlẹ́yìn Meṣullamu àti Ṣabbetai ará Lefi, ni wọ́n tako àbá yìí.
Numai Ionatan fiul lui Asael şi Iahzia fiul lui Ticva au fost folosiţi în aceasta; şi Meşulam şi Şabtai levitul i-au ajutat.
16 Nígbà náà ni àwọn ìgbèkùn ṣe gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe fi ẹnu kò sí. Àlùfáà Esra yan àwọn ọkùnrin tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé, ẹnìkọ̀ọ̀kan láti ìdílé kọ̀ọ̀kan, gbogbo wọn ni a sì mọ̀ pẹ̀lú orúkọ wọn. Ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kẹwàá, wọ́n jókòó láti ṣe àyẹ̀wò àwọn ẹjọ́ náà,
Şi copiii captivităţii au făcut astfel. Şi preotul Ezra, cu unii dintre mai marii dintre părinţi, după casa părinţilor lor şi toţi dintre ei după numele lor, au fost separaţi şi au şezut jos în ziua întâi a lunii a zecea pentru a examina acest lucru.
17 ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní ni wọn parí pẹ̀lú àwọn ènìyàn tí wọ́n fẹ́ àwọn obìnrin àjèjì.
Şi au terminat cu toţi bărbaţii care luaseră soţii străine, până în ziua întâi a lunii întâi.
18 Lára ìran àwọn àlùfáà àwọn wọ̀nyí fẹ́ àwọn obìnrin àjèjì. Nínú ìran Jeṣua ọmọ Josadaki, àti àwọn arákùnrin rẹ: Maaseiah, Elieseri, Jaribi àti Gedaliah.
Şi printre fiii preoţilor au fost găsiţi unii care luaseră soţii străine: mai ales, dintre fiii lui Ieşua fiul lui Ioţadac şi fraţii săi; Maaseia şi Eliezer şi Iarib şi Ghedalia.
19 Gbogbo wọn ni wọ́n ṣe ìpinnu láti lé àwọn ìyàwó wọn lọ, wọ́n sì fi àgbò kan láàrín agbo ẹran lélẹ̀ fún ẹ̀bi wọn gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹ̀ṣẹ̀.
Şi ei şi-au dat mâinile că vor pune deoparte pe soţiile lor; şi fiind vinovaţi, ei au oferit un berbec din turmă pentru fărădelegea lor.
20 Nínú ìran Immeri: Hanani àti Sebadiah.
Şi dintre fiii lui Imer: Hanani şi Zebadia.
21 Nínú ìran Harimu: Maaseiah, Elijah, Ṣemaiah, Jehieli àti Ussiah.
Şi dintre fiii lui Harim: Maaseia şi Ilie şi Şemaia şi Iehiel şi Ozia.
22 Nínú ìran Paṣuri: Elioenai, Maaseiah, Iṣmaeli, Netaneli, Josabadi àti Eleasa.
Şi dintre fiii lui Paşhur: Elioenai, Maaseia, Ismael, Netaneel, Iozabad şi Eleasa.
23 Lára àwọn ọmọ Lefi: Josabadi, Ṣimei, Kelaiah (èyí tí í ṣe Kelita), Petahiah, Juda àti Elieseri.
De asemenea dintre leviţi: Iozabad şi Şimei şi Chelaia (acelaşi este Chelita), Petahia, Iuda şi Eliezer.
24 Nínú àwọn akọrin: Eliaṣibu. Nínú àwọn aṣọ́nà: Ṣallumu, Telemu àti Uri.
Dintre cântăreţi de asemenea: Eliaşib; şi dintre portari: Şalum şi Telem şi Uri.
25 Àti lára àwọn ọmọ Israẹli tókù. Nínú ìran Paroṣi: Ramiah, Issiah, Malkiah, Mijamini, Eleasari, Malkiah àti Benaiah.
Mai mult, din Israel; dintre fiii lui Pareoş: Ramia şi Iziia şi Malchia şi Miiamin şi Eleazar şi Malchia şi Benaia.
26 Nínú ìran Elamu: Mattaniah, Sekariah, Jehieli, Abdi, Jerimoti àti Elijah.
Şi dintre fiii lui Elam: Matania, Zaharia şi Iehiel şi Abdi şi Ierimot şi Ilie.
27 Nínú àwọn ìran Sattu: Elioenai, Eliaṣibu, Mattaniah, Jerimoti, Sabadi àti Asisa.
Şi dintre fiii lui Zatu: Elioenai, Eliaşib, Matania şi Ierimot şi Zabad şi Aziza.
28 Nínú àwọn ìran Bebai: Jehohanani, Hananiah, Sabbai àti Atlai.
Şi dintre fiii lui Bebai: Iohanan, Hanania, Zabai şi Atlai.
29 Nínú àwọn ìran Bani: Meṣullamu, Malluki, Adaiah, Jaṣubu, Ṣeali àti Jerimoti.
Şi dintre fiii lui Bani: Meşulam, Maluc şi Adaia, Iaşub şi Şeal şi Ramot.
30 Nínú àwọn Pahati-Moabu: Adma, Kelali, Benaiah, Maaseiah, Mattaniah, Besaleli, Binnui àti Manase.
Şi dintre fiii lui Pahat-Moab: Adna şi Chelal, Benaia, Maaseia, Matania, Beţaleel şi Binui şi Manase.
31 Nínú àwọn ìran Harimu: Elieseri, Iṣiah, Malkiah àti Ṣemaiah, Simeoni,
Şi dintre fiii lui Harim: Eliezer, Işia, Malchia, Şemaia, Simeon,
32 Benjamini, Malluki àti Ṣemariah.
Beniamin, Maluc şi Şemaria.
33 Nínú àwọn ìran Haṣumu: Mattenai, Mattatta, Sabadi, Elifaleti, Jeremai, Manase àti Ṣimei.
Dintre fiii lui Haşum: Matenai, Matata, Zabad, Elifelet, Ieremai, Manase şi Şimei.
34 Nínú àwọn ìran Bani: Maadai, Amramu, Ueli,
Dintre fiii lui Bani: Maadai, Amram şi Uel,
35 Benaiah, Bediah, Keluhi
Benaia, Bedia, Cheluh,
36 Faniah, Meremoti, Eliaṣibu,
Vania, Meremot, Eliaşib,
37 Mattaniah, Mattenai àti Jaasu.
Matania, Matenai şi Iaasau,
38 Àti Bani, àti Binnui: Ṣimei,
Şi Bani şi Binui, Şimei,
39 Ṣelemiah, Natani, Adaiah,
Şi Şelemia şi Natan şi Adaia,
40 Maknadebai, Sasai, Ṣarai,
Macnadebai, Şaşai, Şarai,
41 Asareeli, Ṣelemiah, Ṣemariah,
Azareel şi Şelemia, Şemaria,
42 Ṣallumu, Amariah àti Josẹfu.
Şalum, Amaria şi Iosif.
43 Nínú àwọn ìran Nebo: Jeieli, Mattitiah, Sabadi, Sebina, Jaddai, Joẹli àti Benaiah.
Dintre fiii lui Nebo: Ieiel, Matitia, Zabad, Zebina, Iadau şi Ioel, Benaia.
44 Gbogbo àwọn wọ̀nyí ló fẹ́ obìnrin àjèjì, àwọn mìíràn nínú wọn sì bi ọmọ ní ipasẹ̀ àwọn ìyàwó wọ̀nyí.
Toţi aceştia luaseră soţii străine; şi unii dintre ei au avut soţii prin care au avut copii.

< Ezra 10 >