< Ezra 10 >
1 Nígbà tí Esra ń gbàdúrà tí ó sì ń jẹ́wọ́, ti ó ń sọkún ti ó sì ń gbárayílẹ̀ níwájú ilé Ọlọ́run, ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ Israẹli ọkùnrin, obìnrin àti àwọn ọmọdé pagbo yí i ká. Àwọn náà ń sọkún kíkorò.
Kwathi uEzra esakhuleka esavuma, ekhala inyembezi eziwisela phansi phambi kwendlu kaNkulunkulu, kwabuthana kuye ibandla elikhulu kakhulu lamadoda labesifazana labantwana, livela kuIsrayeli, ngoba abantu bakhala inyembezi ngokukhala okukhulu.
2 Nígbà náà ni Ṣekaniah ọmọ Jehieli, ọ̀kan lára ìran Elamu, sọ fún Esra pé, “Àwa ti jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Ọlọ́run wa nípa fífẹ́ àwọn obìnrin àjèjì láàrín àwọn ènìyàn tí ó wà yí wa ká. Ṣùgbọ́n síbẹ̀ náà, ìrètí sì wà fún Israẹli
UShekaniya indodana kaJehiyeli owamadodana kaElamu wasephendula wathi kuEzra: Thina siphambukile kuNkulunkulu wethu, sathatha abafazi bezizweni abavela ezizweni zelizwe; kodwa khathesi kukhona ithemba koIsrayeli mayelana lalokhu.
3 Nísìnsinyìí, ẹ jẹ́ kí a dá májẹ̀mú níwájú Ọlọ́run wa láti lé àwọn obìnrin yìí àti àwọn ọmọ wọn lọ. Gẹ́gẹ́ bí ìmọ̀ràn Esra olúwa mi àti ti àwọn tí ó bẹ̀rù àṣẹ Olúwa Ọlọ́run wa. Ẹ jẹ́ kí a ṣe gẹ́gẹ́ bí òfin.
Ngakho-ke asenze isivumelwano loNkulunkulu wethu ukuze sikhuphe bonke abafazi lokuzelwe yibo ngokweseluleko senkosi yami lesabathuthumela emlayweni kaNkulunkulu wethu; kakwenziwe-ke ngokomlayo.
4 Dìde, nítorí, ọ̀rọ̀ tìrẹ ni èyí. Gbogbo wà yóò wá pẹ̀lú rẹ, mú ọkàn le kí o sì ṣe é.”
Sukuma, ngoba udaba luphezu kwakho, lathi silawe. Qina, wenze.
5 Nígbà náà ni Esra dìde, ó sì fi àwọn aṣíwájú àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi àti gbogbo Israẹli sí abẹ́ ìbúra, láti ṣe ohun tí wọ́n dá lábàá. Wọ́n sì búra.
Wasesukuma uEzra, wafungisa induna zabapristi, amaLevi, loIsrayeli wonke, ukuthi benze ngokwalelilizwi. Basebefunga.
6 Nígbà náà ni Esra padà sẹ́yìn kúrò níwájú ilé Ọlọ́run, ó sì lọ sí iyàrá Jehohanani ọmọ Eliaṣibu. Nígbà tí ó wà níbẹ̀, kò jẹ oúnjẹ bẹ́ẹ̀ ni kò sì mu omi, nítorí ó sì ń káàánú fún àìṣòótọ́ àwọn ìgbèkùn.
UEzra wasesukuma esuka phambi kwendlu kaNkulunkulu, waya endlini kaJehohanani indodana kaEliyashibi; wathi efika lapho kadlanga sinkwa kanathanga manzi, ngoba elilela ububi babathunjiweyo.
7 Ìkéde kan jáde lọ jákèjádò Juda àti Jerusalẹmu fún gbogbo àwọn ìgbèkùn láti péjọ sí Jerusalẹmu.
Basebesenza isimemezelo sedlule koJuda leJerusalema kubo bonke abantwana bokuthunjwa ukuthi babuthane eJerusalema,
8 Ẹnikẹ́ni tí ó ba kọ̀ láti jáde wá láàrín ọjọ́ mẹ́ta yóò pàdánù ohun ìní rẹ̀ ní ìbámu pẹ̀lú ìpinnu àwọn ìjòyè àti àwọn àgbàgbà, àti pé a ó lé òun fúnra rẹ̀ jáde kúrò láàrín ìpéjọpọ̀ àwọn ìgbèkùn.
lokuthi loba ngubani ongafikanga ngensuku ezintathu, ngokweseluleko seziphathamandla labadala, impahla yakhe yonke izadliwa, yena ehlukaniswe lebandla labathunjiweyo.
9 Láàrín ọjọ́ mẹ́ta náà, gbogbo àwọn ọkùnrin Juda àti Benjamini tí péjọ sí Jerusalẹmu. Ní ogúnjọ́ oṣù kẹsànán, gbogbo àwọn ènìyàn jókòó sí ìta gbangba iwájú ilé Ọlọ́run, wọ́n wà nínú ìbànújẹ́ ńlá nítorí ọ̀ràn yìí, àti nítorí òjò púpọ̀ tó tì rọ̀.
Wonke amadoda akoJuda loBhenjamini asebuthana eJerusalema ngensuku ezintathu. Kwakuyinyanga yesificamunwemunye ngolwamatshumi amabili lwenyanga. Bonke abantu basebehlala egumeni lendlu kaNkulunkulu beqhaqhazela ngenxa yaloludaba langenxa yezulu elikhulu.
10 Nígbà náà ni àlùfáà Esra dìde, ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ti ṣe àìṣòótọ́, ẹ ti fẹ́ obìnrin àjèjì, ẹ ti dá kún ẹ̀bi Israẹli.
UEzra umpristi wasukuma wathi kibo: Lina liphambukile lathatha abafazi bezizweni, ukwandisa isiphambeko sikaIsrayeli.
11 Nísinsin yìí, ẹ jẹ́wọ́ níwájú Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba yín, kí ẹ sì ṣe ìfẹ́ rẹ̀. Ẹ ya ara yín sọ́tọ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn tí ó yí i yín ká àti láàrín àwọn ìyàwó àjèjì yín.”
Ngakho-ke yenzani uvumo eNkosini uNkulunkulu waboyihlo, lenze intando yayo, lizehlukanise lezizwe zelizwe, lakubafazi bezizweni.
12 Àpéjọpọ̀ ènìyàn náà sì dáhùn lóhùn rara pé, ohun tí ó sọ dára! A gbọdọ̀ ṣe bí o ti wí.
Ibandla lonke laseliphendula lathi ngelizwi elikhulu: Njengamazwi akho, ngokunjalo kuphezu kwethu ukuthi sikwenze.
13 Ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ ni ó wà ni ibi yìí síbẹ̀ àkókò òjò ni; àwa kò sì lè dúró ní ìta. Yàtọ̀ sí èyí, a kò le è yanjú ọ̀rọ̀ yìí láàrín ọjọ́ kan tàbí ọjọ́ méjì, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa pọ̀ jọjọ lórí àwọn nǹkan wọ̀nyí.
Kodwa abantu banengi, njalo kuyisikhathi sezulu elinengi, njalo singeme phandle. Futhi kakusimsebenzi wosuku olulodwa njalo hatshi owezimbili, ngoba sibanengi esiphambukileyo kuloludaba.
14 Jẹ́ kí àwọn ìjòyè wa ṣojú fún gbogbo ìjọ ènìyàn, lẹ́yìn náà, jẹ́ kí ẹnìkọ̀ọ̀kan nínú àwọn ìlú wa tí ó ti fẹ́ obìnrin àjèjì wá ní àsìkò tí a yàn, pẹ̀lú àwọn àgbàgbà àti àwọn onídàájọ́ ìlú kọ̀ọ̀kan, títí ìbínú gíga Ọlọ́run wa lórí ọ̀rọ̀ yìí yóò fi kúrò ní orí wa.
Ake zime iziphathamandla zethu zebandla lonke, labo bonke abasemizini yethu abathethe abafazi bezizweni beze ngezikhathi ezimisiweyo, njalo kanye labo abadala bomuzi ngomuzi labahluleli bawo, size sidedise ukuvutha kolaka lukaNkulunkulu wethu mayelana laloludaba.
15 Jonatani ọmọ Asaheli àti Jahseiah ọmọ Tikfa nìkan pẹ̀lú àtìlẹ́yìn Meṣullamu àti Ṣabbetai ará Lefi, ni wọ́n tako àbá yìí.
NgoJonathani indodana kaAsaheli loJahazeya indodana kaTikiva kuphela abamelana lalokho; loMeshulamu loShabethayi umLevi babancedisa.
16 Nígbà náà ni àwọn ìgbèkùn ṣe gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe fi ẹnu kò sí. Àlùfáà Esra yan àwọn ọkùnrin tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé, ẹnìkọ̀ọ̀kan láti ìdílé kọ̀ọ̀kan, gbogbo wọn ni a sì mọ̀ pẹ̀lú orúkọ wọn. Ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kẹwàá, wọ́n jókòó láti ṣe àyẹ̀wò àwọn ẹjọ́ náà,
Abantwana bokuthunjwa besebesenza njalo. UEzra umpristi, amadoda, inhloko zaboyise ngendlu yaboyise, labo bonke ngamabizo, basebesehlukaniswa; basebehlala ngosuku lokuqala lwenyanga yetshumi ukuhlola loludaba.
17 ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní ni wọn parí pẹ̀lú àwọn ènìyàn tí wọ́n fẹ́ àwọn obìnrin àjèjì.
Basebeqeda lawo wonke amadoda ayethethe abafazi bezizweni kwaze kwaba lusuku lokuqala lwenyanga yokuqala.
18 Lára ìran àwọn àlùfáà àwọn wọ̀nyí fẹ́ àwọn obìnrin àjèjì. Nínú ìran Jeṣua ọmọ Josadaki, àti àwọn arákùnrin rẹ: Maaseiah, Elieseri, Jaribi àti Gedaliah.
Kwasekutholakala phakathi kwamadodana abapristi ayethethe abafazi bezizweni: Emadodaneni kaJeshuwa indodana kaJozadaki labafowabo: OMahaseya loEliyezeri loJaribi loGedaliya.
19 Gbogbo wọn ni wọ́n ṣe ìpinnu láti lé àwọn ìyàwó wọn lọ, wọ́n sì fi àgbò kan láàrín agbo ẹran lélẹ̀ fún ẹ̀bi wọn gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹ̀ṣẹ̀.
Basebenika isandla sabo ukuthi bazakhupha abafazi babo; ngoba belecala banikela inqama yomhlambi ngecala labo.
20 Nínú ìran Immeri: Hanani àti Sebadiah.
Lemadodaneni kaImeri: OHanani loZebhadiya.
21 Nínú ìran Harimu: Maaseiah, Elijah, Ṣemaiah, Jehieli àti Ussiah.
Lemadodaneni kaHarimi: OMahaseya loEliya loShemaya loJehiyeli loUziya.
22 Nínú ìran Paṣuri: Elioenai, Maaseiah, Iṣmaeli, Netaneli, Josabadi àti Eleasa.
Lemadodaneni kaPashuri: OEliyowenayi, uMahaseya, uIshmayeli, uNethaneli, uJozabadi, loElasa.
23 Lára àwọn ọmọ Lefi: Josabadi, Ṣimei, Kelaiah (èyí tí í ṣe Kelita), Petahiah, Juda àti Elieseri.
LakumaLevi: OJozabadi, loShimeyi, loKelaya onguKelita, uPethahiya, uJuda, loEliyezeri.
24 Nínú àwọn akọrin: Eliaṣibu. Nínú àwọn aṣọ́nà: Ṣallumu, Telemu àti Uri.
Lakubahlabeleli: UEliyashibi. Lakubalindimasango: OShaluma loTelema loUri.
25 Àti lára àwọn ọmọ Israẹli tókù. Nínú ìran Paroṣi: Ramiah, Issiah, Malkiah, Mijamini, Eleasari, Malkiah àti Benaiah.
LakuIsrayeli: Emadodaneni kaParoshi: ORamiya loIziya loMalikiya loMijamini loEleyazare loMalikiya loBhenaya.
26 Nínú ìran Elamu: Mattaniah, Sekariah, Jehieli, Abdi, Jerimoti àti Elijah.
Lemadodaneni kaElamu: OMathaniya, uZekhariya, loJehiyeli, loAbidi, loJeremothi, loEliya.
27 Nínú àwọn ìran Sattu: Elioenai, Eliaṣibu, Mattaniah, Jerimoti, Sabadi àti Asisa.
Lemadodaneni kaZathu: OEliyowenayi, uEliyashibi, uMathaniya, loJeremothi, loZabadi, loAziza.
28 Nínú àwọn ìran Bebai: Jehohanani, Hananiah, Sabbai àti Atlai.
Lemadodaneni kaBebayi: OJehohanani, uHananiya, uZabayi, uAthilayi.
29 Nínú àwọn ìran Bani: Meṣullamu, Malluki, Adaiah, Jaṣubu, Ṣeali àti Jerimoti.
Lemadodaneni kaBani: OMeshulamu, uMaluki, loAdaya, uJashubi, loSheyali, loRamothi.
30 Nínú àwọn Pahati-Moabu: Adma, Kelali, Benaiah, Maaseiah, Mattaniah, Besaleli, Binnui àti Manase.
Lemadodaneni kaPahathi-Mowabi: OAdina, loKelali, uBhenaya, uMahaseya, uMathaniya, uBhezaleli, loBinuwi, loManase.
31 Nínú àwọn ìran Harimu: Elieseri, Iṣiah, Malkiah àti Ṣemaiah, Simeoni,
Lamadodana kaHarimi: OEliyezeri, uIshiya, uMalikiya, uShemaya, uShimeyoni,
32 Benjamini, Malluki àti Ṣemariah.
uBhenjamini, uMaluki, uShemariya.
33 Nínú àwọn ìran Haṣumu: Mattenai, Mattatta, Sabadi, Elifaleti, Jeremai, Manase àti Ṣimei.
Emadodaneni kaHashuma: OMathenayi, uMathatha, uZabadi, uElifeleti, uJeremayi, uManase, uShimeyi.
34 Nínú àwọn ìran Bani: Maadai, Amramu, Ueli,
Emadodaneni kaBani: OMahadayi, uAmramu, loUweli,
35 Benaiah, Bediah, Keluhi
uBhenaya, uBedeya, uKeluhi,
36 Faniah, Meremoti, Eliaṣibu,
uVaniya, uMeremothi, uEliyashibi,
37 Mattaniah, Mattenai àti Jaasu.
uMathaniya, uMathenayi, loJahasa,
38 Àti Bani, àti Binnui: Ṣimei,
loBani, loBinuwi, uShimeyi,
39 Ṣelemiah, Natani, Adaiah,
loShelemiya, loNathani, loAdaya,
40 Maknadebai, Sasai, Ṣarai,
uMakinadebayi, uShashayi, uSharayi,
41 Asareeli, Ṣelemiah, Ṣemariah,
uAzareli, uShelemiya, uShemariya,
42 Ṣallumu, Amariah àti Josẹfu.
uShaluma, uAmariya, uJosefa.
43 Nínú àwọn ìran Nebo: Jeieli, Mattitiah, Sabadi, Sebina, Jaddai, Joẹli àti Benaiah.
Lemadodaneni kaNebo: OJeyiyeli, uMathithiya, uZabadi, uZebina, uJadayi, loJoweli, uBhenaya.
44 Gbogbo àwọn wọ̀nyí ló fẹ́ obìnrin àjèjì, àwọn mìíràn nínú wọn sì bi ọmọ ní ipasẹ̀ àwọn ìyàwó wọ̀nyí.
Bonke laba babethethe abafazi bezizweni; njalo kwakukhona phakathi kwabo abafazi ababezele abantwana.