< Ezra 10 >

1 Nígbà tí Esra ń gbàdúrà tí ó sì ń jẹ́wọ́, ti ó ń sọkún ti ó sì ń gbárayílẹ̀ níwájú ilé Ọlọ́run, ogunlọ́gọ̀ àwọn ọmọ Israẹli ọkùnrin, obìnrin àti àwọn ọmọdé pagbo yí i ká. Àwọn náà ń sọkún kíkorò.
Esela da Debolo midadia beguduli, dinanawane Isala: ili dunu ilia wadela: i hou fofada: nanu, amalu Isala: ili fi gilisisu bagade amo dunu, uda amola mano da guba: le sisiga: le ha: giwane didigia: lalu.
2 Nígbà náà ni Ṣekaniah ọmọ Jehieli, ọ̀kan lára ìran Elamu, sọ fún Esra pé, “Àwa ti jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Ọlọ́run wa nípa fífẹ́ àwọn obìnrin àjèjì láàrín àwọn ènìyàn tí ó wà yí wa ká. Ṣùgbọ́n síbẹ̀ náà, ìrètí sì wà fún Israẹli
Amalalu, Sieganaia (Yihaiele egefe amola Ilame fi dunu) da Esela ema amane sia: i, “Ninia da Godema dafawaneyale dawa: su yolesi dagoi. Bai ninia da ga fi uda lasu hou hamosu. Be Gode da Isala: ili dunu hame fisimu.
3 Nísìnsinyìí, ẹ jẹ́ kí a dá májẹ̀mú níwájú Ọlọ́run wa láti lé àwọn obìnrin yìí àti àwọn ọmọ wọn lọ. Gẹ́gẹ́ bí ìmọ̀ràn Esra olúwa mi àti ti àwọn tí ó bẹ̀rù àṣẹ Olúwa Ọlọ́run wa. Ẹ jẹ́ kí a ṣe gẹ́gẹ́ bí òfin.
Waha, ninia da Godema dafawaneyale ilegele sia: mu da defea, amo ninia da amo uda amola ilia mano fisiagamu da defea. Di amola eno dunu da Gode Ea Sema amoga noga: le fa: no bobogesa. Amaiba: le, ninia da dilia sia: defele hamomu. Ninia Gode Ea sema amola hamoma: ne sia: i amoma noga: le fa: no bobogemu.
4 Dìde, nítorí, ọ̀rọ̀ tìrẹ ni èyí. Gbogbo wà yóò wá pẹ̀lú rẹ, mú ọkàn le kí o sì ṣe é.”
Be di fawane da amo hou olelema. Ninia da dia baligia aligili fuligala: mu. Amaiba: le, amo defele masa: ne hamoma.
5 Nígbà náà ni Esra dìde, ó sì fi àwọn aṣíwájú àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi àti gbogbo Israẹli sí abẹ́ ìbúra, láti ṣe ohun tí wọ́n dá lábàá. Wọ́n sì búra.
Amaiba: le, Esela da amo hou hamoi. Ea hamoma: ne sia: beba: le, gobele salasu ouligisu huluane, Lifai fi ouligisu dunu huluane amola dunu eno huluane da Gode Ea Dioba: le, Sieganaia ea sia: i amo defele ilegele hamomu sia: i.
6 Nígbà náà ni Esra padà sẹ́yìn kúrò níwájú ilé Ọlọ́run, ó sì lọ sí iyàrá Jehohanani ọmọ Eliaṣibu. Nígbà tí ó wà níbẹ̀, kò jẹ oúnjẹ bẹ́ẹ̀ ni kò sì mu omi, nítorí ó sì ń káàánú fún àìṣòótọ́ àwọn ìgbèkùn.
Amalalu Esela da Debolo midadi fisili asili, Ilaiasibi egefe Yihouha: ina: ne amo ea diasu ganodini golili sa: ili, mugululi asi buhagi dunu ilia wadela: i hou dawa: beba: le, amo gasia ha: i amola hano mae nawane dinanu.
7 Ìkéde kan jáde lọ jákèjádò Juda àti Jerusalẹmu fún gbogbo àwọn ìgbèkùn láti péjọ sí Jerusalẹmu.
Ilia da Yelusaleme amola Yuda soge huluane amoga, sia: amane lalaba lai, mugululi asi buhagi dunu huluane da Yelusalemega gegedoma: ne sia: si.
8 Ẹnikẹ́ni tí ó ba kọ̀ láti jáde wá láàrín ọjọ́ mẹ́ta yóò pàdánù ohun ìní rẹ̀ ní ìbámu pẹ̀lú ìpinnu àwọn ìjòyè àti àwọn àgbàgbà, àti pé a ó lé òun fúnra rẹ̀ jáde kúrò láàrín ìpéjọpọ̀ àwọn ìgbèkùn.
Amo da Isala: ili ouligisu dunu ilia sia: i. Eso udiana aligili, nowa dunu da hame masea, ea liligi huluane enoga lai dagoi ba: mu, amola e da Isala: ili fi amoga fadegai dagoi ba: mu.
9 Láàrín ọjọ́ mẹ́ta náà, gbogbo àwọn ọkùnrin Juda àti Benjamini tí péjọ sí Jerusalẹmu. Ní ogúnjọ́ oṣù kẹsànán, gbogbo àwọn ènìyàn jókòó sí ìta gbangba iwájú ilé Ọlọ́run, wọ́n wà nínú ìbànújẹ́ ńlá nítorí ọ̀ràn yìí, àti nítorí òjò púpọ̀ tó tì rọ̀.
Eso udiana mae aligili, oubi sesege amola eso 20 amoga, dunu huluane Yuda soge amola Bediamini soge amo ganodini esalu da Yelusalemega gegedole, Debolo gagoi amo ganodini gilisili esalebe ba: i. Gibu bagadewane dasu amola dunu huluane da yagugui. Bai ilia da gibuga anegagi amola gilisisu bai da bagadeba: le, ilia da beda: i.
10 Nígbà náà ni àlùfáà Esra dìde, ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ti ṣe àìṣòótọ́, ẹ ti fẹ́ obìnrin àjèjì, ẹ ti dá kún ẹ̀bi Israẹli.
Gobele salasu dunu Esela da wale gadole, ilima amane sia: i, “Dilia da dafawaneyale hame dawa: su hou hamoi dagoi. Dilia da ga fi uda lai dagoiba: le, Isala: ili fi amo ganodini wadela: i hou bagade dialebe ba: sa.
11 Nísinsin yìí, ẹ jẹ́wọ́ níwájú Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba yín, kí ẹ sì ṣe ìfẹ́ rẹ̀. Ẹ ya ara yín sọ́tọ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn tí ó yí i yín ká àti láàrín àwọn ìyàwó àjèjì yín.”
Amaiba: le, waha dilia wadela: i hou amo dilia aowalalia Hina Godema fofada: ma! Amasea, E da dilima hahawane ba: mu. Dilia ga fi dunu dilia soge ganodini esala ilima afafama. Amola dilia ga fi uda huluane fisiagama!”
12 Àpéjọpọ̀ ènìyàn náà sì dáhùn lóhùn rara pé, ohun tí ó sọ dára! A gbọdọ̀ ṣe bí o ti wí.
Dunu huluane da ha: giwane wele sia: i, amane, “Ninia da dia hamoma: ne sia: i defele hamomu!”
13 Ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀ ni ó wà ni ibi yìí síbẹ̀ àkókò òjò ni; àwa kò sì lè dúró ní ìta. Yàtọ̀ sí èyí, a kò le è yanjú ọ̀rọ̀ yìí láàrín ọjọ́ kan tàbí ọjọ́ méjì, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wa pọ̀ jọjọ lórí àwọn nǹkan wọ̀nyí.
Be ilia da eno amane sia: i, “Dunu gilisi da bagadedafa amola gibu bagade daha. Ninia da udigili hamega gadili lelemu da hamedei. Ninia da dunu bagohame amo wadela: i hou hamoi dagoi. Amaiba: le, eso afaega o adunaga hahamomu da hamedei.
14 Jẹ́ kí àwọn ìjòyè wa ṣojú fún gbogbo ìjọ ènìyàn, lẹ́yìn náà, jẹ́ kí ẹnìkọ̀ọ̀kan nínú àwọn ìlú wa tí ó ti fẹ́ obìnrin àjèjì wá ní àsìkò tí a yàn, pẹ̀lú àwọn àgbàgbà àti àwọn onídàájọ́ ìlú kọ̀ọ̀kan, títí ìbínú gíga Ọlọ́run wa lórí ọ̀rọ̀ yìí yóò fi kúrò ní orí wa.
Ninia ouligisu dunu da Yelusalemega esalu amo hou ouligimu da defea. Amasea, eso afae ilegemu da defea. Amoga, nowa dunu da ga fi uda lai galea, e amola ea moilai ouligisu dunu amola fofada: su dunu gilisili misunu da defea. Amasea, Gode da amo ninia wadela: i hou hamobeba: le ougisa, amo E da yolesimu.”
15 Jonatani ọmọ Asaheli àti Jahseiah ọmọ Tikfa nìkan pẹ̀lú àtìlẹ́yìn Meṣullamu àti Ṣabbetai ará Lefi, ni wọ́n tako àbá yìí.
Dunu huluane ilia da amo hou da defea sia: i. Be A: sahele egefe Yonada: ne, Digifa egefe Yasiaia, Misiala: me amola Sia: bidai (Lifai dunu), ilia da hame fuligala: su.
16 Nígbà náà ni àwọn ìgbèkùn ṣe gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe fi ẹnu kò sí. Àlùfáà Esra yan àwọn ọkùnrin tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé, ẹnìkọ̀ọ̀kan láti ìdílé kọ̀ọ̀kan, gbogbo wọn ni a sì mọ̀ pẹ̀lú orúkọ wọn. Ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kẹwàá, wọ́n jókòó láti ṣe àyẹ̀wò àwọn ẹjọ́ náà,
Be mugululi asi buhagi dunu huluane da amo hou fuligala: beba: le, gobele salasu dunu Esela da fi ouligisu dunu mogili ilegele, ilia dio dedei dagoi. Eso age oubi nabuane amoga, ilia da amo hou muni abodesu.
17 ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní ni wọn parí pẹ̀lú àwọn ènìyàn tí wọ́n fẹ́ àwọn obìnrin àjèjì.
Oubi udiana fa: no amoga ilia da dunu huluane amo da ga fi uda lai, amo ilia hou abodei.
18 Lára ìran àwọn àlùfáà àwọn wọ̀nyí fẹ́ àwọn obìnrin àjèjì. Nínú ìran Jeṣua ọmọ Josadaki, àti àwọn arákùnrin rẹ: Maaseiah, Elieseri, Jaribi àti Gedaliah.
Dunu da ga fi uda lai amo ilia dio da hagudu dedei. Gobele salasu dunu da ga fi uda lai ilia fi dio da Yosiua amola ea yolalali (Yihosada: ge egefe) fi. Amo dunu ilia ga fi uda lai ilia dio da Ma: iasiai, Eleisa, Ya: ilibe amola Gedalaia.
19 Gbogbo wọn ni wọ́n ṣe ìpinnu láti lé àwọn ìyàwó wọn lọ, wọ́n sì fi àgbò kan láàrín agbo ẹran lélẹ̀ fún ẹ̀bi wọn gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹ̀ṣẹ̀.
Amo dunu ilia uda fisiagamusa: sia: i, amalu ilia sibi gawali Godema gobele salasu hamoi, ilia wadela: i hou dodofema: ne. Eno dunu da ga fi uda lai amo ilia fi dio amola ilia dio da hagudu dedei diala: -
20 Nínú ìran Immeri: Hanani àti Sebadiah.
Ime fi...Hana: inai amola Sebadaia.
21 Nínú ìran Harimu: Maaseiah, Elijah, Ṣemaiah, Jehieli àti Ussiah.
Ha: ilime fi...Ma: iasiai, Ilaidia, Siema: iya, Yihaiele amola Asaia.
22 Nínú ìran Paṣuri: Elioenai, Maaseiah, Iṣmaeli, Netaneli, Josabadi àti Eleasa.
Ba: sie fi...Eliounai, Ma: iasisi, Isiama: iele, Nida: niele, Yosaba: de amola Elasa.
23 Lára àwọn ọmọ Lefi: Josabadi, Ṣimei, Kelaiah (èyí tí í ṣe Kelita), Petahiah, Juda àti Elieseri.
Lifai fi dunu...Yosaba: de, Simiai, Gila: iya (eno dio da Gelida), Bedahaia, Yuda amola Eleisa.
24 Nínú àwọn akọrin: Eliaṣibu. Nínú àwọn aṣọ́nà: Ṣallumu, Telemu àti Uri.
Gesami Hea: su fi...Ilaiasibi Debolo sosodo aligisu fi...Sia: lame, Dileme amola Uli
25 Àti lára àwọn ọmọ Israẹli tókù. Nínú ìran Paroṣi: Ramiah, Issiah, Malkiah, Mijamini, Eleasari, Malkiah àti Benaiah.
Eno dunu amo da ga fi uda lai da amo, Ba: ilose fi...Lamaia, Isaia, Ma: lagaia, Midiamini, Elia: isa, Ma: lagaia amola Bina: ia
26 Nínú ìran Elamu: Mattaniah, Sekariah, Jehieli, Abdi, Jerimoti àti Elijah.
Ilame fi...Ma: danaia, Segalia, Yihaiele, A:badai, Yelemode amola Ilaidia
27 Nínú àwọn ìran Sattu: Elioenai, Eliaṣibu, Mattaniah, Jerimoti, Sabadi àti Asisa.
Sa: du fi...Eliounai, Iliasibi, Ma: danaia, Yelemode, Sa: iba: de amola Asaisa
28 Nínú àwọn ìran Bebai: Jehohanani, Hananiah, Sabbai àti Atlai.
Biba: iai fi...Yihoha: ina: ne, Ha: nanaia, Sa: ba: yai amola A: dalai
29 Nínú àwọn ìran Bani: Meṣullamu, Malluki, Adaiah, Jaṣubu, Ṣeali àti Jerimoti.
Ba: inai fi...Misiala: me, Ma: lage, Ada: iya, Ya: isiabe, Sia: le amola Yelemode
30 Nínú àwọn Pahati-Moabu: Adma, Kelali, Benaiah, Maaseiah, Mattaniah, Besaleli, Binnui àti Manase.
Ba: iha: de Moua: be fi...A: dana, Gila: le, Bina: ia, Ma: iasiai, Ma: danaia, Bisa: liele, Binuai amola Ma: na: se
31 Nínú àwọn ìran Harimu: Elieseri, Iṣiah, Malkiah àti Ṣemaiah, Simeoni,
32 Benjamini, Malluki àti Ṣemariah.
Ha: ilime fi...Eleisa, Isiya, Ma: lagaia, Siema: iya, Simiane, Bediamini, Ma: lage amola Siemalaiya
33 Nínú àwọn ìran Haṣumu: Mattenai, Mattatta, Sabadi, Elifaleti, Jeremai, Manase àti Ṣimei.
Ha: isiame fi...Ma: dina: yai, Ma: dada, Sa: iba: de, Ilifelede, Yelemai, Ma: na: se amola Simiai
34 Nínú àwọn ìran Bani: Maadai, Amramu, Ueli,
Ba: inai fi...Ma: yada: yai, A:mala: me, Iuele, Bina: ya, Bidiya, Giluhi, Fana: ya, Melimode, Ilaiasibi, Ma: danaia, Ma: dena: yai amola Ya: ya: su.
35 Benaiah, Bediah, Keluhi
36 Faniah, Meremoti, Eliaṣibu,
37 Mattaniah, Mattenai àti Jaasu.
38 Àti Bani, àti Binnui: Ṣimei,
Binuai fi...Simiai, Sielemaia, Na: ida: ne, Ada: iya, Ma: gana: dibai, Sia: isiai, Siala: yai, Asa: iliele, Sielemaia, Siemalaiya, Sia: lame, A:malaia amola Yousefe
39 Ṣelemiah, Natani, Adaiah,
40 Maknadebai, Sasai, Ṣarai,
41 Asareeli, Ṣelemiah, Ṣemariah,
42 Ṣallumu, Amariah àti Josẹfu.
43 Nínú àwọn ìran Nebo: Jeieli, Mattitiah, Sabadi, Sebina, Jaddai, Joẹli àti Benaiah.
Nibou fi...Yiayele, Ma: didaia, Sa: iba: de, Sibaina, Ya: dai, Youele amola Bina: ia
44 Gbogbo àwọn wọ̀nyí ló fẹ́ obìnrin àjèjì, àwọn mìíràn nínú wọn sì bi ọmọ ní ipasẹ̀ àwọn ìyàwó wọ̀nyí.
Amo dunu huluane da ga fi uda lai dagoi. Ilia da amo uda fisiagale, amo uda amola ilia mano ga asunasi. Sia: ama dagoi

< Ezra 10 >