< Ezekiel 9 >

1 Mo gbọ́ ti ó kígbe ní ohùn rara pé, “Mú àwọn olùṣọ́ ìlú súnmọ́ itòsí, kí olúkúlùkù wọn mú ohun ìjà olóró lọ́wọ́.”
Апой а стригат ку глас таре ла урекиле меле: „Апропияци-вэ, вой, каре требуе сэ педепсиць четатя, фиекаре ку унялта луй де нимичире ын мынэ!”
2 Lójú ẹsẹ̀ ni ọkùnrin mẹ́fà jáde láti ẹnu-ọ̀nà òkè tó kọjú sí ìhà àríwá, olúkúlùkù pẹ̀lú ohun ìjà olóró lọ́wọ́ wọn. Ọkùnrin kan tó wọ aṣọ funfun gbòò wa láàrín wọn, pẹ̀lú ohun ìkọ̀wé lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀. Gbogbo wọn sì dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ pẹpẹ idẹ.
Ши ятэ кэ ау венит шасе оамень де пе друмул порций де сус динспре мязэноапте, фиекаре ку унялта луй де нимичире ын мынэ. Ын мижлокул лор ера ун ом ымбрэкат ынтр-о хайнэ де ин ши ку о кэлимарэ ла брыу. Ау венит ши с-ау ашезат лынгэ алтарул де арамэ.
3 Ògo Ọlọ́run Israẹli sì gòkè kúrò lórí kérúbù, níbi tó wà tẹ́lẹ̀ lọ sí ibi ìloro tẹmpili. Nígbà náà ni Olúwa pe ọkùnrin tó wọ aṣọ funfun náà tí ó sì ní ohun ìkọ̀wé lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀.
Слава Думнезеулуй луй Исраел с-а ридикат де пе херувимул пе каре ера ши с-а ындрептат спре прагул касей, ши Ел а кемат пе омул ачела каре ера ымбрэкат ку хайна де ин ши каре авя кэлимара ла брыу.
4 Ó sì sọ fún un pé, “La àárín ìlú Jerusalẹmu já, kí ìwọ sì fi àmì síwájú orí gbogbo àwọn tó ń kẹ́dùn, tó sì ń sọkún nítorí ohun ìríra tí wọn ń ṣe láàrín rẹ̀.”
Домнул й-а зис: „Тречь прин мижлокул четэций, прин мижлокул Иерусалимулуй, ши фэ ун семн пе фрунтя оаменилор каре суспинэ ши ӂем дин причина тутурор урычунилор каре се сэвыршеск аколо.”
5 Bí mo ṣe ń fetí sí èyí, O tún sọ fún àwọn yòókù pé, “Tẹ̀lé ọkùnrin náà lọ sí àárín ìlú láti pa láì dá sí àti láì ṣàánú rárá.
Яр челорлалць ле-а зис ын аузул меу: „Тречець дупэ ел ын четате ши ловиць; окюл востру сэ фие фэрэ милэ ши сэ ну вэ ындураць!
6 Ẹ pa arúgbó àti ọ̀dọ́mọkùnrin, ẹ pa ọlọ́mọge, obìnrin àti ọmọ kéékèèké, ṣùgbọ́n ẹ má ṣe fi ọwọ́ kan àwọn tó ní àmì. Ẹ bẹ̀rẹ̀ láti ibi mímọ́.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn àgbàgbà tó wà níwájú tẹmpili.
Учидець ши нимичиць пе бэтрынь, пе тинерь, пе фечоаре, пе копий ши пе фемей, дар сэ ну вэ атинӂець де ничунул дин чей че ау семнул пе фрунте! Ынчепець ынсэ ку Локашул Меу чел Сфынт!” Ей ау ынчепут ку бэтрыний каре ерау ынаинтя Темплулуй.
7 Nígbà náà lo sọ fún wọn pé, “Ẹ sọ tẹmpili náà di àìmọ́, kí òkú sì kún àgbàlá náà. Ẹ lọ!” Wọ́n jáde síta, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí í pa ènìyàn láàrín ìlú.
Ши Ел ле-а зис: „Спуркаць каса ши умплець курциле ку морць!… Ешиць!…” Ей ау ешит ши ау ынчепут сэ учидэ ын четате.
8 Èmi nìkan ló ṣẹ́kù nígbà tí wọ́n lọ pa àwọn ènìyàn, mo dójú mi bolẹ̀, mo kígbe pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè! Ìwọ yóò ha pa ìyókù Israẹli nípa dída ìbínú gbígbóná rẹ sórí Jerusalẹmu?”
Пе кынд учидяу ей астфел ши еу стэтям ынкэ сингур аколо, ам кэзут ку фаца ла пэмынт ши ам стригат: „Ах, Доамне Думнезеуле, врей сэ нимичешть оаре тот че а май рэмас дин Исраел, вэрсынду-Ць урӂия асупра Иерусалимулуй?”
9 Ó dá mi lóhùn pé, “Ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli àti Juda pọ gidigidi; ilé wọn kún fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀ àti àìṣòótọ́. Wọ́n ní, ‘Olúwa tí kọ ilẹ̀ náà sílẹ̀; Olúwa kò sì rí wa.’
Ел мь-а рэспунс: „Нелеӂюиря касей луй Исраел ши Иуда есте маре, песте мэсурэ де маре! Цара есте плинэ де оморурь ши четатя есте плинэ де недрептате, кэч ей зик: ‘Домнул а пэрэсит цара ши Домнул ну веде нимик!’
10 Nítorí náà, èmi kò ní wò wọ́n pẹ̀lú àánú, èmi kò sì ní dá wọn sí, ṣùgbọ́n Èmi yóò dá ohun tí wọ́n ti ṣe padà sórí wọn.”
Де ачея ши Еу вой фи фэрэ милэ ши ну Мэ вой ындура, чи вой фаче сэ кадэ асупра капулуй лор фаптеле лор.”
11 Ọkùnrin tí ó wọ aṣọ ọ̀gbọ̀, tí ó ní ìwo tàdáwà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ ròyìn pé, “Mo ti ṣe gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti pàṣẹ fún mi.”
Ши ятэ кэ омул чел ымбрэкат ын хайна де ин ши каре авя кэлимара ла брыу а адус урмэторул рэспунс: „Ам фэкут че мь-ай порунчит!”

< Ezekiel 9 >