< Ezekiel 8 >

1 Ní ọjọ́ karùn-ún, oṣù kẹfà ọdún kẹfà bí mo ṣe jókòó nílé mi pẹ̀lú àwọn àgbàgbà Juda níwájú mi, ọwọ́ Olúwa Olódùmarè bà lé mi níbẹ̀.
A šeste godine, šestoga mjeseca, dana petoga, kad sjeðah u svojoj kuæi i starješine Judine sjeðahu preda mnom, pade ondje na me ruka Gospoda Gospoda.
2 Nígbà tí mo wò, mo rí ohun kan tí ó jọ ènìyàn. Láti ibi ìbàdí rẹ lọ sísàlẹ̀ dàbí iná, láti ibi ìbàdí yìí sókè sì mọ́lẹ̀ bí idẹ tó ń kọ mọ̀nà.
I vidjeh, a to oblik na oèi kao oganj, od bedara mu dolje bješe oganj, a od bedara gore bješe kao svjetlost, kao jaka svjetlost.
3 Ó na ohun tó dàbí ọwọ́ jáde, ó fi gba mi ní irun orí mú, Ẹ̀mí sì gbé mi sókè sí agbede-méjì ayé àti ọ̀run, ó sì mú mi lọ rí ìran Ọlọ́run, mo sì lọ sí Jerusalẹmu, ṣí ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀nà òde àríwá níbi tí ère owú tí ó ń mú ni bínú wá níwájú mi.
I pruži kao ruku, i uhvati me za kosu na glavi, i podiže me duh meðu nebo i zemlju, i odnese me u Jerusalim u utvari Božjoj na vrata unutrašnja koja gledaju na sjever, gdje stajaše idol od revnosti, koji draži na revnost.
4 Sì kíyèsi i, ògo Ọlọ́run Israẹli wà níbẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìran ti mo rí ni pẹ̀tẹ́lẹ̀.
I gle, ondje bješe slava Boga Izrailjeva na oèi kao ona što je vidjeh u polju.
5 Ó sì sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, gbójú sókè sí ìhà àríwá.” Èmi náà sì gbójú sókè sí ìhà àríwá mo sì rí ère tí ó ń mú ni jowú ní ẹnu-ọ̀nà ibi pẹpẹ.
I reèe mi: sine èovjeèji, podigni oèi svoje k sjeveru. I podigoh oèi svoje k sjeveru, i gle, sa sjevera na vratima oltarskim bijaše onaj idol od revnosti na ulasku.
6 Ó sì wí fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, ṣé o rí ohun tí wọ́n ń ṣe ohun ìríra ńlá tí ilé Israẹli ń ṣe, láti lé mi jìnnà réré sí ibi mímọ́ mi? Ṣùgbọ́n ìwọ yóò tún rí àwọn ìríra ńlá tó tóbi jù èyí lọ.”
Potom mi reèe: sine èovjeèji, vidiš li što ti rade? velike gadove koje tu èini dom Izrailjev da otidem daleko od svetinje svoje? Ali æeš još vidjeti veæih gadova.
7 Ó mú mi wá sí ẹnu-ọ̀nà àgbàlá. Mo wò ó, mo sì rí ihò kan lẹ́gbẹ̀ẹ́ ògiri.
I odvede me na vrata od trijema, i pogledah, a to jedna rupa u zidu.
8 Nígbà náà ló sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, gbẹ́ inú ògiri náà,” nígbà tí mo sì gbẹ́ inú ògiri, mo rí ìlẹ̀kùn kan.
A on mi reèe: sine èovjeèji, prokopaj ovaj zid. I prokopah zid, a to jedna vrata.
9 Ó sì wí fún mi pé, “Wọlé kí ìwọ kí ó rí ohun ìríra búburú tí wọ́n ń ṣe níbẹ̀.”
Tada mi reèe: uði i vidi opake gadove koje èine tu.
10 Mo wọlé, mo sì rí àwòrán oríṣìíríṣìí ẹranko tí ń fà nílẹ̀ àti àwọn ẹranko ìríra àti gbogbo òrìṣà ilẹ̀ Israẹli tí wọ́n yà sára ògiri.
I ušav vidjeh, i gle, svakojake životinje što gamižu i svakojaki gadni skotovi, i svi gadni bogovi doma Izrailjeva bijahu napisani po zidu svuda unaokolo.
11 Níwájú wọn ni àádọ́rin ọkùnrin tó jẹ́ àgbàgbà ilé Israẹli dúró sí, Jaaṣaniah ọmọ Ṣafani sì dúró sí àárín wọn. Ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn sì mú àwo tùràrí lọ́wọ́, òórùn sì ń tú jáde.
I pred njima stajaše sedamdeset ljudi izmeðu starješina doma Izrailjeva s Jazanijom sinom Safanovijem, koji stajaše meðu njima, svaki s kadionicom svojom u ruci, i podizaše se gust oblak od kada.
12 Ó sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, ṣé o ti rí ohun tí àwọn àgbàgbà ilé Israẹli ń ṣe nínú òkùnkùn, olúkúlùkù ní yàrá òrìṣà rẹ̀? Wọ́n ní, ‘Olúwa kò rí wa; Olúwa ti kọ̀ ilé náà sílẹ̀.’”
Tada mi reèe: vidiš li, sine èovjeèji, šta èine starješine doma Izrailjeva u mraku svak u svojoj pisanoj klijeti? jer govore: ne vidi nas Gospod, ostavio je Gospod ovu zemlju.
13 Ó tún sọ fún mi pé, “Ìwọ yóò rí wọn tí wọ́n ń ṣe àwọn ohun ìríra tó burú jù bẹ́ẹ̀ lọ.”
Potom mi reèe: još æeš vidjeti veæih gadova koje oni èine.
14 Ó mú mi wá sí ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa tó wà ní ìhà àríwá, mo sì rí àwọn obìnrin tó jókòó, tí wọ́n sí ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa tó wà ní ìhà àríwá, mo sì rí àwọn obìnrin tó jókòó, tí wọ́n sì ń ṣọ̀fọ̀ fún Tamusi.
I odvede me na vrata doma Gospodnjega koja su sa sjevera; i gle, žene sjeðahu i plakahu za Tamuzom.
15 Ó sọ fún mi pé, “Ṣé ìwọ rí báyìí, ọmọ ènìyàn? Ìwọ yóò tún rí ìríra tó ga jù èyí lọ.”
I reèe mi: jesi li vidio, sine èovjeèji? još æeš vidjeti veæih gadova od tijeh.
16 Ó mú mi wá sí ibi àgbàlá ilé Olúwa, ní ẹnu-ọ̀nà tẹmpili Olúwa, láàrín ìloro àti pẹpẹ, ni ìwọ̀n ọkùnrin mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n wà, tí wọ́n kẹ́yìn sí tẹmpili Olúwa tí wọn sì kọjú sí ìlà-oòrùn, wọ́n sì ń foríbalẹ̀ fún oòrùn ní apá ìlà-oòrùn.
I odvede me u trijem unutrašnji doma Gospodnjega; i gle, na ulasku u crkvu Gospodnju izmeðu trijema i oltara bješe oko dvadeset i pet ljudi okrenutijeh leðima k crkvi Gospodnjoj a licem k istoku, i klanjahu se suncu prema istoku.
17 Ó sì wí fún mi, “Ṣé ìwọ ti rí èyí ọmọ ènìyàn? Ǹjẹ́ ohun kékeré ni fún ilé Juda láti ṣe àwọn ohun ìríra tí wọn ń ṣe níbi yìí? Ṣé o tún yẹ kí wọ́n fi ìwà ipá kún ilẹ̀ kí wọn sì máa mú mi bínú ní gbogbo ìgbà? Wò wọn bi wọn ṣe n fi ẹ̀ka wọn sínú inú wọn.
Tada mi reèe: jesi li vidio, sine èovjeèji? malo li je domu Judinu što èine te gadove koje èine ovdje? nego još napuniše zemlju nasilja i okrenuše se da me draže; i eto drže granu pred nosom svojim.
18 Nítorí náà, èmi yóò fi ìbínú bá wọn wí; èmi kò ní i dá wọn sí bẹ́ẹ̀ ni èmi kò sì ní fojú àánú wò wọ́n. Bí wọ́n tilẹ̀ ń pariwo sí mi létí, èmi kò ní fetí sí wọn.”
Zato æu i ja uèiniti u gnjevu, neæe žaliti oko moje, niti æu se smilovati, i kad stanu vikati iza glasa u moje uši, neæu ih uslišiti.

< Ezekiel 8 >