< Ezekiel 6 >
1 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá wí pé,
Kiugo kĩa Jehova nĩkĩanginyĩrĩire, ngĩĩrwo atĩrĩ,
2 “Ọmọ ènìyàn, dojúkọ àwọn òkè Israẹli; kí o sì sọtẹ́lẹ̀ lòdì sí wọn
“Mũrũ wa mũndũ, ngʼethera irĩma cia Isiraeli; cirathĩre ũhoro wa gũciũkĩrĩra,
3 wí pé, ‘Ẹ̀yin òkè Israẹli, ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè. Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí sí ẹ̀yin òkè ńlá àti àwọn òkè kéékèèké, sí àwọn odò ṣíṣàn àti sí àfonífojì, èmi yóò mú idà wa sórí yín, èmí yóò sì pa ibi gíga yín run.
ũciĩre atĩrĩ: ‘Inyuĩ irĩma cia Isiraeli, iguai kiugo kĩa Mwathani Jehova. Ũũ nĩguo Mwathani Jehova ekwĩra irĩma na tũrĩma, na mĩkuru na cianda: Niĩ ngirie kũmũũkĩrĩra na rũhiũ rwa njora, na nyanange kũndũ kwanyu kũrĩa gũtũũgĩru.
4 Èmi yóò wó pẹpẹ yín lulẹ̀, èmi yóò sì fọ́ pẹpẹ tùràrí yín túútúú; èmi yóò sì pa àwọn ènìyàn yín síwájú àwọn òrìṣà wọn.
Igongona cianyu nĩikamomorwo, na igongona cianyu cia gũcinĩrwo ũbumba ihehenjwo; na nĩngooragĩra andũ anyu hau mbere ya mĩhianano ĩyo yanyu.
5 Èmi yóò tẹ́ òkú àwọn ará Israẹli síwájú òrìṣà wọn, èmi yóò sì fọ́n egungun wọn yí pẹpẹ wọn ká.
Nĩngaragania ciimba cia andũ a Isiraeli hau mbere ya mĩhianano ĩyo yao, na nĩngahurunja mahĩndĩ manyu gũthiũrũrũkĩria igongona cianyu.
6 Gbogbo ibi tí ẹ ń gbé àti àwọn ibi gíga yín ni yóò di píparun, gbogbo pẹpẹ yín ni yóò di ahoro, àwọn òrìṣà yín yóò di fífọ́ túútúú, àwọn pẹpẹ tùràrí yín ni a ó gé lulẹ̀, gbogbo iṣẹ́ yín yóò parẹ́.
Kũndũ kũrĩa guothe mũtũũraga, matũũra macio nĩmakanangwo, na kũndũ kũrĩa gũtũũgĩru kũmomorwo, nĩguo igongona cianyu ithũkio na cianangwo, nayo mĩhianano yanyu ĩhehenjwo na yũnũhwo, o na igongona cianyu cia gũcinĩrwo ũbumba imomorwo, na kĩrĩa mũthondekete kĩniinwo.
7 Àwọn ènìyàn yín yóò ṣubú láàrín yín, ẹ ó sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
Andũ anyu nĩmakooragĩrwo gatagatĩ-inĩ kanyu, na inyuĩ nĩmũkamenya atĩ niĩ nĩ niĩ Jehova.
8 “‘Ṣùgbọ́n èmi yóò dá àwọn kan sí nítorí pé díẹ̀ nínú yín ni yóò bọ́ lọ́wọ́ idà, nígbà tí a bá fọ́n yín ká sí gbogbo ilẹ̀ àti orílẹ̀-èdè.
“‘No rĩrĩ, nĩ kũrĩ amwe ngaatigia, nĩgũkorwo amwe anyu nĩmakahonoka kũũragwo na rũhiũ rwa njora rĩrĩa mũgaakorwo mũhurunjũkĩire mabũrũri-inĩ na ndũrĩrĩ-inĩ.
9 Àwọn ti ó bọ́ nínú yin yóò sì rántí mi láàrín àwọn orílẹ̀-èdè níbi tí wọn yóò dìwọ́n ní ìgbèkùn lọ, nítorí wọ́n yóò máa rántí mi bí wọ́n ti bà mí lọ́kàn jẹ́ nípa àgbèrè wọn, tí ó yà wọ́n kúrò lọ́dọ̀ mi àti nípa ojú wọn tí ó ṣàfẹ́rí àwọn òrìṣà. Wọn yóò sì ṣú ara wọn nítorí ìwà ibi tí wọ́n ti hù nípa gbogbo ìríra wọn.
Ningĩ marĩ ndũrĩrĩ-inĩ kũu matwarĩtwo marĩ atahe-rĩ, arĩa makaahonoka nĩmakandirikana. Nĩmakaririkana ũrĩa njiguithĩtio ũũru nĩ ngoro ciao cia ũtharia, iria iihutatĩire, na maitho mao marĩa makoretwo makĩĩrirĩria mĩhianano yao. Nĩmakemena nĩ ũndũ wa waganu ũrĩa mekĩte, na nĩ ũndũ wa ciĩko ciao ciothe irĩ magigi.
10 Wọn yóò sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa; àti pé kì í ṣe lásán ni mo ń lérí pé èmi yóò mú ìdààmú bá wọn.
Nao nĩmakamenya atĩ niĩ nĩ niĩ Jehova; niĩ ndiamamakagia tũhũ ngiuga atĩ nĩngamarehere mũtino ũyũ.
11 “‘Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí, Pàtẹ́wọ́ kí o tún fẹsẹ̀ janlẹ̀, kí o wá kígbe síta pé, “Ó ṣe!” Ilé Israẹli yóò ṣubú nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn nítorí gbogbo ìwà ìríra búburú tí wọ́n hù. Wọn yóò ṣubú nípa idà àti ìyàn.
“‘Mwathani Jehova ekuuga atĩrĩ: Hũũra hĩ, na ũhũũrithie makinya thĩ, uugĩrĩrie uuge atĩrĩ, “Wũi!” Tondũ wa waganu wothe na ciĩko irĩ magigi cia nyũmba ya Isiraeli, nĩgũkorwo nĩmakooragwo na rũhiũ rwa njora, na ngʼaragu, na mũthiro.
12 Ẹni tó wà lókèèrè yóò kú pẹ̀lú àjàkálẹ̀-ààrùn, àti ẹni tó wà nítòsí yóò ṣubú pẹ̀lú idà, ìyàn ni yóò pa ẹni tó bá ṣẹ́kù sílẹ̀. Báyìí ni èmi yóò ṣe mú ìbínú gbígbóná mi wá sórí wọn.
Mũndũ ũrĩa ũtũũraga kũraya akooragwo nĩ mũthiro, nake ũrĩa ũrĩ gũkuhĩ ooragwo na rũhiũ rwa njora, nake ũrĩa ũkaahonoka atigare, akooragwo nĩ ngʼaragu. Ũguo nĩguo ngeeruta mangʼũrĩ makwa nao.
13 Wọn yóò sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa, nígbà tí òkú àwọn ènìyàn wọn bá wà níbẹ̀ láàrín òrìṣà wọn yí pẹpẹ wọn ká, lórí àwọn òkè gíga gbogbo, àti lórí góńgó òkè àti lábẹ́ igi tútù àti lábẹ́ igi óákù, níbi tí wọ́n ti ń fi tùràrí olóòórùn dídùn rú ẹbọ sí gbogbo òrìṣà wọn.
Nao nĩmakamenya atĩ niĩ nĩ niĩ Jehova, rĩrĩa andũ magaakorwo moragĩtwo marĩ gatagatĩ-inĩ ka mĩhianano ĩyo yao mathiũrũrũkĩirie igongona ciao, na handũ hothe hatũũgĩru, na tũcũmbĩrĩ tuothe twa irĩma, na rungu rwa mũtĩ o wothe waraganĩtie honge, na rungu rwa mũgandi o wothe mũruru, kũndũ guothe kũrĩa maarutagĩra mĩhianano yao mahuti manungi wega.
14 Èmi yóò na ọwọ́ mi jáde sí wọn láti mú kí ilẹ̀ náà ṣòfò, kí ó sì dahoro dé aṣálẹ̀ ìhà Dibila—ní gbogbo ibùgbé wọn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
Na niĩ nĩngamatambũrũkĩria guoko ndĩmookĩrĩre, na ndũme bũrũri wanangĩke ũtiganĩrio, kuuma werũ-inĩ ũcio nginya Dibila, kũndũ guothe kũrĩa matũũrĩte. Hĩndĩ ĩyo nĩmakamenya atĩ niĩ nĩ niĩ Jehova.’”