< Ezekiel 6 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá wí pé,
Angraeng ih lok kai khaeah angzoh,
2 “Ọmọ ènìyàn, dojúkọ àwọn òkè Israẹli; kí o sì sọtẹ́lẹ̀ lòdì sí wọn
kami capa, Israel maenawk bangah angqoi ah loe, nihcae misahaih lok to taphong ah;
3 wí pé, ‘Ẹ̀yin òkè Israẹli, ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè. Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí sí ẹ̀yin òkè ńlá àti àwọn òkè kéékèèké, sí àwọn odò ṣíṣàn àti sí àfonífojì, èmi yóò mú idà wa sórí yín, èmí yóò sì pa ibi gíga yín run.
Aw Israel maenawk, Angraeng Sithaw ih lok to tahngai oh; Angraeng Sithaw mah maenawk, maesomnawk, vapuinawk hoi azawnnawk khaeah hae tiah lokthuih; khenah, Kai mah roe, nangcae khaeah sumsen to ka sin moe, nangcae ih hmuensangnawk to ka phraek han.
4 Èmi yóò wó pẹpẹ yín lulẹ̀, èmi yóò sì fọ́ pẹpẹ tùràrí yín túútúú; èmi yóò sì pa àwọn ènìyàn yín síwájú àwọn òrìṣà wọn.
Na hmaicamnawk loe angqai krangah om tih, krangnawk to amro tih; na sak o ih krangnawk hmaa ah nangmah ih kaminawk to ka hum han.
5 Èmi yóò tẹ́ òkú àwọn ará Israẹli síwájú òrìṣà wọn, èmi yóò sì fọ́n egungun wọn yí pẹpẹ wọn ká.
Israel kaminawk ih qok to na sak o ih krangnawk hmaa ah ka pasongh moe, na huhnawk doeh na hmaicam taengah ka haeh han.
6 Gbogbo ibi tí ẹ ń gbé àti àwọn ibi gíga yín ni yóò di píparun, gbogbo pẹpẹ yín ni yóò di ahoro, àwọn òrìṣà yín yóò di fífọ́ túútúú, àwọn pẹpẹ tùràrí yín ni a ó gé lulẹ̀, gbogbo iṣẹ́ yín yóò parẹ́.
Na oh o haih vangpuinawk loe amro boih tih, hmuensangnawk doeh angqai krang tih boeh; na hmaicamnawk doeh amro tih, na bok o ih krangnawk loe koi phaeng ueloe, anghmaa tih, na sak o cop ih krangnawk to koi boih ueloe, na sak o ih hmuenawk doeh anghmaa boih tih boeh.
7 Àwọn ènìyàn yín yóò ṣubú láàrín yín, ẹ ó sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
Na prae thungah nangmah ih kaminawk to hum o boih tih, to naah Kai loe Angraeng ni, tiah na panoek o tih.
8 “‘Ṣùgbọ́n èmi yóò dá àwọn kan sí nítorí pé díẹ̀ nínú yín ni yóò bọ́ lọ́wọ́ idà, nígbà tí a bá fọ́n yín ká sí gbogbo ilẹ̀ àti orílẹ̀-èdè.
Toe anghmat kaminawk loe ka pathlung han, thoemto kaminawk loe sumsen hoiah loih o ueloe, prae congca kaminawk salakah anghaeh o phang tih.
9 Àwọn ti ó bọ́ nínú yin yóò sì rántí mi láàrín àwọn orílẹ̀-èdè níbi tí wọn yóò dìwọ́n ní ìgbèkùn lọ, nítorí wọ́n yóò máa rántí mi bí wọ́n ti bà mí lọ́kàn jẹ́ nípa àgbèrè wọn, tí ó yà wọ́n kúrò lọ́dọ̀ mi àti nípa ojú wọn tí ó ṣàfẹ́rí àwọn òrìṣà. Wọn yóò sì ṣú ara wọn nítorí ìwà ibi tí wọ́n ti hù nípa gbogbo ìríra wọn.
Kai khae hoi amkhraeng, zaesak koehhaih palungthinnawk, krang bokhaih hoi zaesak koehhaih miknawk to kam rosak naah loe, kaloih kaminawk mah misong ah a oh o haih prae hoiah kai to panoek o tih; panuet kathok hmuen to a sak o pongah angmacae hoi angmacae to panuet o tih.
10 Wọn yóò sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa; àti pé kì í ṣe lásán ni mo ń lérí pé èmi yóò mú ìdààmú bá wọn.
Kai loe Angraeng ni, tiah nihcae mah panoek o ueloe, nihcae nuiah kasae phaksak han ka thuih ih lok doeh ka thui rumram ai, tito nihcae mah panoek o tih.
11 “‘Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí, Pàtẹ́wọ́ kí o tún fẹsẹ̀ janlẹ̀, kí o wá kígbe síta pé, “Ó ṣe!” Ilé Israẹli yóò ṣubú nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn nítorí gbogbo ìwà ìríra búburú tí wọ́n hù. Wọn yóò ṣubú nípa idà àti ìyàn.
Angraeng Sithaw mah, Ezekiel, Israel kaminawk mah sak o ih kahoih ai panuet kathok hmuen pongah, Alas, tiah dawnraihaih lok to thui ah! Ban atumh ah loe, khok hoiah tacu ah; nihcae loe sumsen, khokhahaih, kasae nathaih hoiah dueh o tih boeh.
12 Ẹni tó wà lókèèrè yóò kú pẹ̀lú àjàkálẹ̀-ààrùn, àti ẹni tó wà nítòsí yóò ṣubú pẹ̀lú idà, ìyàn ni yóò pa ẹni tó bá ṣẹ́kù sílẹ̀. Báyìí ni èmi yóò ṣe mú ìbínú gbígbóná mi wá sórí wọn.
Kangthla ah kaom kami loe kasae nathaih hoiah dueh o ueloe, anghnai ah kaom kami loe sumsen hoiah dueh o tih; takui khoep ih kami hoi anghmat kami loe khokhahaih hoiah dueh o tih: to tiah palung ka phuihaih nihcae nuiah ka koepsak han.
13 Wọn yóò sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa, nígbà tí òkú àwọn ènìyàn wọn bá wà níbẹ̀ láàrín òrìṣà wọn yí pẹpẹ wọn ká, lórí àwọn òkè gíga gbogbo, àti lórí góńgó òkè àti lábẹ́ igi tútù àti lábẹ́ igi óákù, níbi tí wọ́n ti ń fi tùràrí olóòórùn dídùn rú ẹbọ sí gbogbo òrìṣà wọn.
Angmacae hmaicam taeng ih krangnawk salakah, maesangnawk hoi maenawk nui boih ah, thing tahlip boih ah, aqam kabuk thing tlim boih ah, a bok o ih krangnawk hanah hmuihoih thlaek ih ahmuen ah, angmacae ih kami hum o naah ni, Kai loe Angraeng ni, tiah na panoek o tih.
14 Èmi yóò na ọwọ́ mi jáde sí wọn láti mú kí ilẹ̀ náà ṣòfò, kí ó sì dahoro dé aṣálẹ̀ ìhà Dibila—ní gbogbo ibùgbé wọn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
Nihcae nuiah ban ka payuengh moe, prae to ka pongsak sut han, ue, praezaek hoiah nihcae ohhaih ahmuen, Diblah karoek to angqai krang ah ka suek naah, to naah nihcae mah Kai loe Angraeng ni, tiah panoek o tih, tiah ang naa.

< Ezekiel 6 >