< Ezekiel 45 >

1 “‘Nígbà ti ẹ̀yin bá pín ilẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ogún, ẹ gbọdọ̀ gbé ìpín ilẹ̀ kan kalẹ̀ fún Olúwa gẹ́gẹ́ bí ibi mímọ́, ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ni gígùn àti ogún ẹgbẹ̀rún ìgbọ̀nwọ́ ni ìbú; gbogbo agbègbè rẹ̀ yíká ni yóò jẹ́ mímọ́.
Taham khethaih phoisa to vah moe, long to qawk ah nam zet o naah, thoemto ciimcai long to Angraeng khaeah tangqum ah paek oh; to ahmuen loe cung sing hnet sang pangato sawk ueloe, cung sang hato kawk tih. To ahmuen taengnawk boih to kaciim ah suem oh.
2 Lára inú èyí, ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta yóò jẹ́ ti ibi mímọ́ ní gígùn, pẹ̀lú ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ní ìbú, ní igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin yíká, àti àádọ́ta ìgbọ̀nwọ́ fún gbangba rẹ̀ yíká.
To ahmuen thungah kasawk dong cumvai pangato, kakawk dong cumvai pangato, ahnuk ahma kangvan takii palito kaom im hmuen to hmuenciim ah suem oh; to ahmuen taeng boih doeh dong qui pangato thung ciimcai ah suem oh.
3 Ní agbègbè ibi mímọ́, wọn ya ibi kan sọ́tọ̀ kí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ní gígùn àti ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ní ìbú. Ní inú rẹ ni ilẹ̀ ti a yà sọ́tọ̀ fún Olúwa yóò wà, ìyẹn Ibi Mímọ́ Jùlọ.
To ahmuen thungah kasawk dong sang pumphae pangato, kakawk dong sang hato kaom ahmuen to tah oh; to ahmuen loe hmuenciim hoi Ciimcai Koek ahmuen ah om tih.
4 Yóò jẹ́ ibi mímọ́ lára ilẹ̀ náà fún àwọn àlùfáà, tí ó ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ ní ibi mímọ́ àti àwọn tí ó súnmọ́ àlùfáà ní iwájú Olúwa. Ibẹ̀ yóò jẹ ibi tí yóò wà fún ilé gbígbé wọn, bákan náà ni yóò jẹ́ ibi mímọ́ fún ilé Olúwa.
Thoemto long hmuenciim loe Angraeng hma ah toksak han akun, hmuenciim ah toksah qaimanawk hanah om tih; to ahmuen loe nihcae imsakhaih ahmuen hoi hmuenciim ohhaih ahmuen ah om tih.
5 Agbègbè kan tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ní gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ní ìbú yóò jẹ́ ti àwọn ọmọ Lefi, tí ó ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ nínú tẹmpili, gẹ́gẹ́ bi ìní wọn fún ìlú wọn láti máa gbé ibẹ̀.
Kasawk dong sang pumphae pangato, kakawk dong sang hato kaom long ahmuen loe, tempul thung toksah Levinawk ohhaih imkhaan pumphaeto sakhaih ahmuen ah om tih.
6 “‘Ìwọ yóò fi ìlú náà ti agbègbè rẹ̀ jẹ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún ìgbọ̀nwọ́ ni ìbú àti ẹgbẹ̀rún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ní gígùn, papọ̀ mọ́ ibi mímọ́ fún àwọn ilé Israẹli gẹ́gẹ́ bí ìní: yóò jẹ́ ti gbogbo ilé Israẹli.
Kakawk dong sang pangato, kasawk dong sang pumphae pangato kaom, tangqum ah paek ih hmuenciim hoi kangbet ahmuen to, vangpui sakhaih ahmuen ah om ueloe, Israel imthung takohnawk boih mah om o haih tih.
7 “‘Àwọn ọmọ-aládé ni yóò bá ibi mímọ́ pààlà ní ẹ̀gbẹ́ kọ̀ọ̀kan agbègbè tí ó jẹ ibi mímọ́ àti ohun tí ó jẹ́ ti ìlú. Yóò fẹ̀ sẹ́yìn sí ìhà ìwọ̀-oòrùn láti apá ìwọ̀-oòrùn àti si ìlà-oòrùn, láti apá ìlà-oòrùn, gígùn rẹ̀ yóò jẹ́ láti ìwọ̀-oòrùn sí ààlà ìlà-oòrùn, ti ìṣe déédé rẹ̀ yóò jẹ́ ti ọ̀kan lára àwọn ìpín ẹ̀yà.
Tangqum ah paek ih hmuenciim hoi vangpui ahmuen, maeto bang hoi maeto bang khoek to, kaciim ahmuen hoiah vangpui angzithaih ramri ahnuk bang boih, ni angyae bang ih ahmuen boih loe angraeng ohhaih ahmuen ah om tih; sawkhaih bang ah niduem bang hoi ni angzae bang khoek to, Israel acaeng maeto ih ramri hoi angbet tih.
8 Ilẹ̀ yìí ni yóò jẹ́ ìpín rẹ̀ ní Israẹli. Àwọn ọmọ-aládé mìíràn kò ní rẹ́ àwọn ènìyàn mi jẹ mọ́, ṣùgbọ́n wọn yóò jẹ́ kí àwọn ilé Israẹli gba ilẹ̀ wọn gẹ́gẹ́ bi ẹ̀yà wọn.
To long ahmuen loe angraeng mah Israel prae thungah tawnh ih ahmuen ah om tih; Kai ih kaminawk mah kai ih ukkung angraengnawk to pacaekthlaek o mak ai boeh; angmacae ih acaeng baktih toengah, kanghmat long ahmuen loe Israel imthung takoh hanah paek oh.
9 “‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Ẹ̀yin ti rìn jìnnà tó, ẹ̀yin ọmọ-aládé tí Israẹli! Ẹ fi ìwà ipá àti ìrẹ́jẹ yín sílẹ̀ kí ẹ̀yin sì ṣe èyí tí ó tọ́ àti èyí tí ó yẹ. Ẹ dáwọ́ gbígbà ní ọwọ́ àwọn ènìyàn mi dúró, ni Olúwa Ọlọ́run wí.
Angraeng Sithaw mah hae tiah thuih; Aw Israel angraengnawk, khawt lai nasoe; tha patohhaih hoi hmuenmae lomhaihnawk to toengh oh loe, kamsoem hoi katoeng hmuennawk to sah oh, kai ih kaminawk pacaekthlaekhaih to toengh o lai ah, tiah Angraeng Sithaw mah thuih.
10 Kí ẹ̀yin kì ó lo òsùwọ̀n tó tọ́ àti efa títọ́ àti bati títọ́.
Kangvan kazit tahhaih, kangvan ephah, kangvan bath to patoh oh.
11 Efa àti bati gbọdọ̀ jẹ́ bákan náà, kí bati tí ó gba ìdámẹ́wàá homeri, àti efa ìdámẹ́wàá homeri: Homeri ni kí ó jẹ́ òsùwọ̀n tí ẹ̀yin yóò lò fún méjèèjì.
Ephah hoi bath loe azithaih dan angvan han oh, homer hato thungah maeto loe bath maeto ah om ueloe, homer hato thungah maeto loe ephah maeto ah om toeng tih; homer loe hmuen tahhaih ah om tih.
12 Ṣékélì ní kí o gba ogún gera. Ogún ṣékélì pẹ̀lú ṣékélì pẹ̀lú ṣékélì mẹ́ẹ̀ẹ́dógún yóò jẹ́ mina kan.
Shekel maeto naah gerah pumphaeto om tih; shekel hato kazit, shekel pumphae pangato kazit, shekel hathlai pangato kazit nawnto tacuu naah, maneh maeto om tih.
13 “‘Èyí yìí ni ẹ̀bùn pàtàkì tí ẹ gbọdọ̀ ṣe: efa kẹfà láti inú homeri ọkà kọ̀ọ̀kan àti efa kẹfà láti inú homeri barle kọ̀ọ̀kan.
Hmuenmae paek naah hae tiah paek oh; canghum hoi barli cang to, homer maeto naah ephah tarukto thungah maeto na paek o han oh:
14 Ìpín òróró tí a júwe, tí a fi bati wọ́n, ni ìdámẹ́wàá bati láti inú kórì (èyí tí ó gba ìdámẹ́wàá bati tàbí homeri kan, fún ìdámẹ́wàá bati jẹ́ bákan náà sì homeri kan).
situi tahhaih daan loe, kor maeto naah bath hato thungah maeto paek oh, kor maeto naah bath hato, to tih ai boeh loe homer maeto oh; bath hato naah homer maeto oh:
15 Bákan náà ni ọ̀dọ́-àgùntàn kan láti inú agbo ẹran, láti inú igba, láti inú pápá oko tútù Israẹli, fún ọrẹ ẹbọ jíjẹ, àti fún ọrẹ ẹbọ sísun, àti fún ọrẹ ẹbọ ìdúpẹ́ láti ṣe ìwẹ̀nùmọ́ fún àwọn ènìyàn, ní Olúwa Olódùmarè wí.
Israel prae thung tui kahoih ahmuen ih qam kacaa tuu khongkha thung ih tuu cumvai hnetto thungah maeto paek han angaih; hae hmuennawk loe cang hoi angbawnhaih, hmai angbawnhaih, angdaeh angbawnhaih, mikhmai sak angbawnhaih ah patoh han oh, tiah Angraeng Sithaw mah thuih.
16 Gbogbo ènìyàn ni ilẹ̀ náà ni yóò kópa nínú ẹ̀bùn pàtàkì fún ìlò àwọn ọmọ-aládé ni Israẹli.
Hae baktih tangqum hae prae thungah kaom kaminawk boih mah Israel ukkung angraeng hanah paek o tih.
17 Yóò jẹ́ ojúṣe ọmọ-aládé láti pèsè ọrẹ ẹbọ sísun, ọrẹ ẹbọ jíjẹ àti ọrẹ ẹbọ mímu níbi àsè gbogbo, ti oṣù tuntun àti ní àwọn ọjọ́ ìsinmi ni gbogbo àjọ̀dún tí a yàn ní ilé Israẹli. Òun yóò pèsè ọrẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, ọrẹ ẹbọ jíjẹ, ọrẹ ẹbọ sísun àti ọrẹ ẹbọ ìdàpọ̀, láti ṣe ètùtù fún ilé Israẹli.
Israel imthung takohnawk mah sak o zong ih khrah kangtha aninawk, Sabbath aninawk, kaminawk amkhuenghaih poih oh naah, zaehoikung mah hmai angbawnhaih, cang angbawnhaih, naek tui angbawnhaihnawk to paek han oh; anih mah zae angbawnhaih, cang angbawnhaih, hmai angbawnhaih, angdaeh angbawnhaih to Israel imthung takoh hanah mikhmai sak angbawnhaih ah sah pae tih.
18 “‘Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kìn-ín-ní ìwọ yóò mú akọ màlúù aláìlábàwọ́n kì o sì sọ ilé Ọlọ́run di mímọ́.
Angraeng Sithaw mah, Khrah tangsuek nito haih naah, coek koi om ai maitaw tae kanawk to la ah loe, hmuenciim to pasae ah.
19 Àlùfáà ni yóò mú díẹ̀ nínú ẹ̀jẹ̀ ọrẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, kí o sì fi si ẹnu ìlẹ̀kùn ilé Ọlọ́run, àti sí ara àwọn ìlẹ̀kùn tí ó wà ní àgbàlá ti inú.
Qaima mah zae angbawnhaih athii to la ueloe, tempul tungnawk, hmaicam takii palito nui hoi athung longhma ih khongkha tungnawk nuiah suem tih.
20 Ìwọ yóò ṣe bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ní ọjọ́ keje oṣù fún àwọn tí ó dá ẹ̀ṣẹ̀ àìmọ̀ọ́mọ̀dá tàbí nínú àìmọ̀kan; nítorí náà, ìwọ yóò ṣe ìwẹ̀nùmọ́ fún ilé Ọlọ́run.
Hmuen sakpazaehaih tawn kami hoi poek ai pui ah zaehaih sah kaminawk hanah, khrah amtonghaih ni sarihto naah sah paeh; to tiah Israel imthung takoh hanah im angdaeh lethaih to sah paeh.
21 “‘Ní ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kìn-ín-ní ní ìwọ yóò ṣe àjọ ìrékọjá, àsè ọjọ́ méje, àsìkò yìí ní ẹ̀yin yóò jẹ àkàrà tí kò ni ìwúkàrà.
Khrah tangsuek ni hathlai palito naah, loihaih poih to om tih, ni sarihto thung sah oh loe, taeh thuh ai ih takaw to caa oh.
22 Ní ọjọ́ náà ní ọmọ-aládé yóò pèsè akọ màlúù gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ fún ara rẹ̀ àti fún gbogbo ènìyàn ni ilẹ̀ náà.
To na niah ukkung angraeng mah, angmah hoi prae kaminawk boih hanah, zae angbawnhaih to maitaw tae maeto hoiah sah tih.
23 Ní ojoojúmọ́ ni àárín ọjọ́ méje àsè ni òun yóò pèsè akọ màlúù méje àti àgbò méje tí kò ní àbùkù gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹbọ sísun sí Olúwa, àti akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
Poihsakhaih ni sarihto thung, anih mah coek koi om ai maitaw tae sarihto, tuu tae sarihto hoiah zae angbawnhaih to ni thokkruek ni sarihto thung sah tih; ni thokkruek zae angbawnhaih ah maeh tae maeto paek tih.
24 Òun yóò sì pèsè efa gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹbọ jíjẹ. Efa kan fún akọ màlúù kọ̀ọ̀kan àti efa kan fún àgbò kọ̀ọ̀kan, pẹ̀lú hínì òróró kan fún efa kan.
Anih mah cang hoi angbawnhaih sak hanah, maitaw tae maeto naah cang ephah maeto, tuu tae maeto naah cang ephah maeto hoi sah pae ueloe, cang ephah maeto hanah situi hint maeto hoi sak pae han angaih.
25 “‘Láàrín ọjọ́ méje àsè náà, tí ó bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù keje, òun yóò tún pèsè ohun kan náà fún ọrẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, ọrẹ ẹbọ sísun, ọrẹ ẹbọ ohun jíjẹ, àti fún òróró.
Khrah sarihto, ni hathlai pangato naah, anih mah zae angbawnhaih, hmai angbawnhaih, cang angbawnhaih, situi angbawnhaih baktih toengah, ni sarihto thung poih to sah tih, tiah thuih.

< Ezekiel 45 >