< Ezekiel 44 >
1 Lẹ́yìn náà ni ọkùnrin náà mú mi padà lọ sí ibi mímọ́, èyí tí ó kọjú sí ìhà ìlà-oòrùn, ó sì wà ní títì.
Amo dunu da na gadili logo ga: su amo da Debolo sogebi amoga gusudili diala, amoga oule asi. Logo da ga: i dagoi ba: i.
2 Olúwa sọ fún mi, “Ẹnu-ọ̀nà yìí ni kí ó wà ní títì. A kò gbọdọ̀ ṣí i sílẹ̀; kò sí ẹni tí o gbọdọ̀ gba ibẹ̀ wọlé. Ó gbọdọ̀ wà ní títì nítorí pé Olúwa Ọlọ́run Israẹli tí gbà ibẹ̀ wọlé.
Hina Gode da nama amane sia: i, “Amo logo ga: su da ga: iwane dialu, hamedafa doasimu. Osobo bagade dunu da amoga hamedafa golili masunu. Bai Na, Isala: ili fi ilia Hina Gode, da amodili golili sa: i. E da ga: iwane dialoma: mu.
3 Ọmọ-aládé fúnra rẹ̀ ní o lè jókòó ní ẹnu-ọ̀nà náà kí o sì jẹun níwájú Olúwa. Ó gbọdọ̀ gba ọ̀nà ìloro ẹnu-ọ̀nà wọlé kí ó sì gba ibẹ̀ jáde.”
Be Isala: ili Ouligisu da amoga Na midadi hadigi ha: i manusa: masunu da defea. E da ganodini sesei logo holei amoga golili sa: imu, amola amoga gadili masunu.”
4 Lẹ́yìn náà, ọkùnrin náà mú mi gba ẹnu-ọ̀nà àríwá lọ sí iwájú ilé Ọlọ́run. Mo wò ó mo sì rí ògo Olúwa tí ó kún inú ilé Olúwa, mo sì dojúkọ ilẹ̀.
Amalalu, amo dunu da na oule ga (north) logo holeiga golili sa: ili, Debolo midadi amoga oule asi. Na ba: laloba, Hina Gode Ea Debolo Diasu da Gode Ea nenemigi Hadigi amoga nabai ba: i. Na da osoboga odagi guduli gala: la sa: i.
5 Olúwa sì sọ fún mì pé, “Ọmọ ènìyàn, wò dáradára, fetísílẹ̀ dáradára kí o sì fiyèsí ohun gbogbo tí mo sọ fún ọ nípa òfin lórí ilé Olúwa náà. Fiyèsí ẹnu-ọ̀nà ilé Ọlọ́run náà àti gbogbo àbájáde ibi mímọ́.
Hina Gode da nama amane sia: i, “Dunu egefe! Dia ba: mu amola nabimu liligi huluane noga: le dawa: mu. Na da dima Debolo Diasu ouligisu hou amola sema huluane dima olelemu. Dunu mogili da Debolo Diasu ganodini sa: ili, gadili masunu da defea. Be mogili eno da hamedafa sa: imu. Amo mogi aduna noga: le dio lama.
6 Sọ fún ọlọ̀tẹ̀ ilé Israẹli pé, ‘Èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Ìwà ìríra rẹ tí tó gẹ́ẹ́, ìwọ ilé Israẹli!
Amo Isala: ili lelesu dunu ilima amane adoma, ‘Na, Ouligisudafa Hina Gode, da ilia wadela: idafa hou bagade higabeba: le, ilia logo wahadafa hedofamu.
7 Ní àfikún pẹ̀lú gbogbo àwọn ìwà ìríra rẹ tí ó kù, ìwọ mú àwọn àjèjì aláìkọlà àyà àti ara wá sí inú ibi mímọ́ mi, ní lílo ilé mi ní ìlòkulò nígbà tí ìwọ fi oúnjẹ fún mi, ọ̀rá àti ẹ̀jẹ̀, ìwọ sì ba májẹ̀mú mi jẹ́.
Gobele salasu dunu ilia da sefe amola maga: me Nama imunusa: gobele salaloba, ilia da gadofo hame damui ga fi dunu, amo Na Debolo Diasu ganodini golili sa: ima: ne logo doasiba: le, Na Debolo Diasu gugunufi dagoi. Amaiwane, Na fi dunu da wadela: idafa hamobeba: le, ilia da Na gousa: su fi dagoi.
8 Dípò kí ìwọ pa òfin mi mọ́, ìwọ fi àwọn mìíràn sí ibi mímọ́ mi.
Ilia da Na Debolo Diasu sema ouligisu hou fisili, ga fi dunu amo ouligima: ne, logo doasi.’
9 Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Àjèjì aláìkọlà àyà àti ara kò gbọdọ̀ wọ ibi mímọ́ mi, àti pẹ̀lú àwọn àjèjì tí ń gbé ní àárín àwọn ọmọ Israẹli.
Na, Ouligisudafa Hina Gode, da gasa bagade sia: sa, ‘Gadofo hame damui ga fi dunu, amola Na sia: hame nabasu dunu da Na Debolo Diasu ganodini hamedafa golili sa: imu. Amolawane, ga fi dunu da ea fi fisili, Isala: ili fi ganodini esaloma: ne masea, amo dunu amola da Na Debolo Diasu ganodini hamedafa golili sa: imu.’”
10 “‘Àwọn Lefi tí wọn rìn jìnnà kúrò lọ́dọ̀ mi nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli ṣìnà, ti wọ́n sì ṣáko kúrò lọ́dọ̀ mi láti tọ àwọn ère wọn lẹ́yìn gbọdọ̀ jèrè ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Hina Gode da nama amane sia: i, “Na da Lifai dunu amo da eno Isala: ili fi dunuma gilisili, Na fisili, ogogole ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadosu, ilima se bidi imunu.
11 Wọn le sìn mi ní ibi mímọ́ mi, kí wọn ṣe ìtọ́jú àwọn ẹnu-ọ̀nà ilé Ọlọ́run, kí wọn sì ṣe ìránṣẹ́ nínú rẹ̀; wọn le pa ẹbọ sísun, ki wọn sì rú ẹbọ fún àwọn ènìyàn, kí wọn sì dúró níwájú àwọn ènìyàn, kí wọ́n sì ṣe ìránṣẹ́ fún wọn.
Ilia da Debolo Diasu ganodini Nama agoane hawa: hamomu. Ilia da logo ga: su ouligimu, amola eno Debolo hawa: hamosu hamomu. Ilia da ohe amo dunu eno da gobele salasu hamoma: ne gaguli maha, amo medole legemu da defea amola dunu fidimusa: hawa: hamomu da defea.
12 Ṣùgbọ́n nítorí pé wọn ṣe ìránṣẹ́ fún wọn níwájú àwọn ère wọn, tí wọn sì mu ilé Israẹli ṣubú sínú ẹ̀ṣẹ̀, nítorí náà, Èmi tí búra nípa nína ọwọ́ sókè pé, wọn gbọdọ̀ jèrè ẹ̀ṣẹ̀ wọn, ní Olúwa Olódùmarè wí.
Be, ilia da ogogosu ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadosu hou ouligiba: le, ilia da Isala: ili dunu wadela: idafa hou hamomusa: oule asi. Amaiba: le, Na, Ouligisudafa Hina Gode, da Na Dioba: le dafawanedafa ilima se bidi imunusa: sia: sa.
13 Wọn kò gbọdọ̀ súnmọ́ ọ̀dọ̀ mi láti ṣe ìránṣẹ́ fún mi, gẹ́gẹ́ bí àlùfáà tàbí súnmọ́ nǹkan kan nínú àwọn ohun mímọ́ mi tàbí ẹbọ mi mímọ́ jùlọ; wọn gbọdọ̀ gba ìtìjú ìwà ìríra wọn.
Ilia da Nama gobele salasu hou hamedafa hamomu. Ilia da hadigi liligi gadenene hamedafa masunu. Ilia da Hadigidafa Momei Sesei amo ganodini hamedafa golili sa: imu. Ilia da wadela: idafa hou hamobeba: le, Na da amo se bidi ilima iaha.
14 Síbẹ̀ èmi yóò mu wọn sí ìtọ́jú ilé Ọlọ́run àti gbogbo iṣẹ́ tí a gbọdọ̀ ṣe níbẹ̀.
Na da ilima Debolo Diasu ganodini fonobahadi loboga hawa: hamosu fawane ilegele iaha.”
15 “‘Ṣùgbọ́n àwọn àlùfáà, tí ó jẹ́ Lefi àti àwọn ìran Sadoku tí fi tọkàntọkàn ṣe iṣẹ́ ibi mímọ́ mi nígbà tí àwọn Israẹli ṣáko lọ kúrò lọ́dọ̀ mi, wọn gbọdọ̀ súnmọ́ iwájú láti ṣe ìránṣẹ́ ní iwájú mi, láti rú ẹbọ ọ̀rá àti ẹ̀jẹ̀, ni Olúwa Olódùmarè wí.
Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: i, “Be Isala: ili fi dunu mogili huluane da Nama baligi fa: beba: le, Lifai fi gobele salasu dunu amo da Sa: idoge egaga fi esala, da Nama mae baligi fa: le, Debolo Diasu ganodini hahawane hawa: hamosu. Amaiba: le, wali, amo dunu fawane da Nama misini, gobele salasu sefe amola maga: me Nama imunusa: misa: ma.
16 Àwọn nìkan ni ó gbọdọ̀ wọ ibi mímọ́ mi; àwọn nìkan ní o gbọdọ̀ súnmọ́ tábìlì mi láti ṣe ìránṣẹ́ ni iwájú mi, ki wọn sì ṣe iṣẹ́ ìsìn mi.
Ilia fawane da Na Debolo Diasu ganodini golili sa: ili, Na oloda amo ouligimu, amola Debolo nodone sia: ne gadosu hou ouligimu.
17 “‘Nígbà ti wọ́n wọ àwọn ẹnu-ọ̀nà àgbàlá ti inú, wọn yóò wọ ẹ̀wù ọ̀gbọ̀, wọn kò gbọdọ̀ wọ aṣọ onírun nígbà tí wọ́n bá ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ ní àwọn ẹnu-ọ̀nà àgbàlá ti inú tàbí ni inú ilé Ọlọ́run.
Ilia da Debolo ganodini dibifufu amoga golili sa: imusa: , logo holeiga heda: sea, ilia ahea: iai abula salawane misunu. Ilia da ganodini dibifufu amola Debolo ganodini hawa: hamosea, ilia da sibi hinabo abula salimu da sema bagade.
18 Wọ́n yóò sì dé fìlà ọ̀gbọ̀ sí orí wọn àti ṣòkòtò ọ̀gbọ̀ sí ìdí wọn. Wọn kò sì gbọdọ̀ wọ ohunkóhun tí yóò mú wọn làágùn.
Ilia da finimu mae masa: ne, ilia da ahea: iai abula habuga amola ahea: iai abula selefa salima: mu. Be bulu mae idiniginisima: mu.
19 Nígbà tí wọ́n bá lọ sì àgbàlá òde níbi tí àwọn ènìyàn wà, wọn gbọdọ̀ bọ́ ẹ̀wù tí wọ́n fi ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́, ki wọn sì fi wọn sílẹ̀ sí àwọn yàrá mímọ́ náà, kí wọn kí ó sì wọ ẹ̀wù mìíràn, wọn kì yóò sì fi ẹ̀wù wọn sọ àwọn ènìyàn di mímọ́.
Ilia da gadili dibifufu (dunu fi da amoga esalebe) amoga masusa: dawa: sea, ilia hidadea ahea: iai abula gisa: le fasili, hadigi sesei amoga ligisimu. Ilia da dunudafa ilima ilia sema abulaga se mae ima: ne, ilia da amogai abula eno salimu.
20 “‘Wọn kò gbọdọ̀ fá irun, wọn kò sì gbọdọ̀ jẹ́ kí irun wọn gùn, ṣùgbọ́n wọn gbọdọ̀ jẹ́ kí irun orí wọn wà ní gígẹ̀.
Gobele salasu dunu da ilia dialuma hinabo hame waga: ma: mu. Amola, ilia dialuma hinabo hame sedagima: mu. Ilia da ilia dialuma hinabo houdafa defele ouligima: ma.
21 Àlùfáà kankan kò gbọdọ̀ mu ọtí nígbà tí ó bá wọ àgbàlá tí inú.
Gobele salasu dunu da ganodini dibifufu amo ganodini golili sa: imusa: dawa: sea, ilia da waini hano hamedafa manu.
22 Wọn ko gbọdọ̀ fẹ́ opó ni ìyàwó, wọn kò sì gbọdọ̀ kọ ìyàwó wọn sílẹ̀, wọ́n lè fẹ́ àwọn ọmọbìnrin ti kò tí i mọ ọkùnrin rí, tí ó sì jẹ́ ìran àwọn ọmọ Israẹli, tàbí kí wọn fẹ́ àwọn opó àlùfáà.
Gobele salasu dunu da fisiagai uda lamu da sema bagade. E da Isala: ili a: fini amo da dunuga hame dawa: digi o gobele salasu dunu eno ea didalo amo fawane lama: mu.
23 Wọn yóò sì fi ìyàtọ̀ tí ó wà láàrín mímọ́ àti àìmọ́ kọ́ àwọn ènìyàn mi, wọn yóò sì fihàn wọ́n bi wọn yóò ṣe dá aláìmọ́ mọ̀ yàtọ̀ sí mímọ́.
Gobele salasu dunu da Na fi dunu ilima liligi da hadigi amola hadigi hame amo ea afafasu hou ilima olelema: mu. Amola liligi da ledo hamoi amola ledo hame, amo ea afafasu hou, ilima olelema: mu.
24 “‘Nínú èyíkéyìí èdè-àìyedè, àwọn àlùfáà ní yóò dúró gẹ́gẹ́ bí onídàájọ́ gẹ́gẹ́ bí òfin mi. Wọ́n ní láti pa àwọn òfin àti àṣẹ mi mọ́ ní gbogbo àjọ̀dún tí a yàn, wọn sì gbọdọ̀ ya ọjọ́ ìsinmi mi ní mímọ́.
Na dunu da eagene fofada: musa: sia: ga gegesea, gobele salasu dunu da Na malei defele amoga fofada: ma: mu. Ilia da Na lolo nasu gilisisu amo Na sema amola Na malei defele, noga: le ouligima: mu. Amola ilia Sa: bade eso amola ode amola da hadigiba: le, amo noga: le ouligima: mu.
25 “‘Àlùfáà kò gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nípa sísún mọ́ òkú ènìyàn; ṣùgbọ́n ti òkú ènìyàn yẹn bá jẹ́ baba tàbí ìyá rẹ̀, àbúrò rẹ̀ ọkùnrin tàbí àbúrò rẹ̀ obìnrin ti kò i ti lọ́kọ, nígbà náà o le sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́.
Gobele salasu dunu da bogoi da: i hodo digili ba: mu da sema bagade. Be e da eda o ame o ea mano o yolali o dalusi gawa hame fi, amo fawane digili ba: mu da defea.
26 Lẹ́yìn ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀, ki òun kí ó dúró fún ọjọ́ méje.
Amo digili ba: lalu, e da bu sema foloai dagoi hamosea, e da eso fesu ouesalea,
27 Ní ọjọ́ ti yóò wọ àgbàlá ti inú ni ibi mímọ́ láti ṣe ìránṣẹ́ ibi mímọ́, ni kí òun kí ó rú ọrẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ ni Olúwa Olódùmarè wí.
e da Debolo ganodini dibifufu amo ganodini golili dasea, ea hou foloama: ne, amola bu Debolo Diasu ganodini hawa: hamomusa: logo doasima: ne, gobele salasu ima: mu.
28 “‘Èmi ni yóò jẹ́ ogún kan ṣoṣo tí àwọn àlùfáà yóò ní. Ẹ kì yóò fún wọn ni ìpín kankan ní Israẹli, Èmi ni yóò jẹ́ ìní wọn.
Na da Isala: ili dunu ilia da iligaga fi ilima ima: ne, soge amola diasu amola liligi noga: iwane iasu. Be Na da gobele salasu fi ilima liligi eno hame, be ilia gobele salasu ouligisu hou fawane ilima i. Ilia da Isala: ili soge amo ganodini, soge hame gagumu. Na da ilia hanai gumima: ne defele esala.
29 Wọn yóò jẹ ọrẹ ẹbọ jíjẹ, ọrẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti ọrẹ ẹbọ ìrékọjá; gbogbo ohun tí a bá yà sọ́tọ̀ fún Olúwa ni Israẹli ni yóò jẹ́ tiwọn.
Gagoma gobele salimusa: iasu, (Hina Godema Gala: ine Iasu) amola gobele salasu ha: i manu amo da wadela: i hou dodofemusa: iaha, (Wadela: i Hou Gogolema: ne Olofoma: ne Iasu) amola Dabe Ima: ne Iasu, amo da gobele salasu dunu ilia ha: i manu ba: mu. Amola adi liligi Isala: ili dunu da Nama imunusa: modale ligiagai, amo huluane gobele salasu dunu da lama: mu.
30 Èyí tí ó dára jùlọ nínú gbogbo àkọ́so èso àti ọrẹ yín yóò jẹ́ ti àwọn àlùfáà. Ẹ ó sì fi àkọ́pò ìyẹ̀fun yín fún wọn kí ìbùkún lè wà lórí gbogbo ilé yín.
Gobele salasu dunu da bisili ifabia dadami amola bisili liligi huluane Nama iabe amo lama: mu. Eso huluane dunu da agi ga: gi gobesea, ilia da bisili moloi gobebe afae gobele salasu dunu ilima imunu. Amasea, Na da ilia fi diasua amo hahawane dogolegele hamomu.
31 Àwọn àlùfáà kì yóò jẹ́ ohunkóhun bí i ẹyẹ tàbí ẹranko, tí ó ti kú fúnra rẹ̀ tàbí èyí ti ẹranko ńlá fàya.
Gobele salasu dunu da sio o ohe fi udigili bogoi amola edadoga medole legei, amo manu da sema bagade.”