< Ezekiel 43 >

1 Lẹ́yìn náà ọkùnrin náà mú mi gba ti ẹnu-ọ̀nà tí ó dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn,
Hathnukkhu, kanîtholah kangvawi e takhang koe lah bout na ceikhai teh,
2 mo sì ri ògo Ọlọ́run Israẹli ń bọ láti ìhà ìlà-oòrùn. Ohùn rẹ̀ dàbí híhó omi, ìtànṣán ògo rẹ̀ sì bo ilẹ̀.
khenhaw! Isarel Cathut bawilennae teh kanîtho lahoi a tho. A pawlawk teh tui moikapap e pawlawk patetlah ao teh, talai heh a bawilennae hoi pheng a ang.
3 Ó sì dàbí ìran tí mo rí, gẹ́gẹ́ bí ìran tí mo rí nígbà tí mo wá láti pa ìlú náà run; ìran náà sì dà bí ìran tí mo rí lẹ́bàá odò Kebari, mo sì dojú mi bolẹ̀.
A kamnuenae ka hmu teh, a kamnuenae teh, khopui raphoe hanelah ka tho e hoi Kebar tui teng e ka hmu e patetlah kamnuenae lah ao teh pakhup lah ka rawp
4 Ògo Olúwa gba ọ̀nà tí o dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn wọ inú ilé Ọlọ́run wá.
Kanîtholah kangvawi e takhang koe e bawkim thung vah, BAWIPA e bawilennae teh a kâen.
5 Mo ni ìrusókè ẹ̀mí, ó sì mú mi lọ inú ilé ìdájọ́, sì kíyèsi ògo Olúwa kún inú ilé Ọlọ́run.
Muitha ni na tawm teh, athung patuen e thongma koe lah na kâenkhai. Khenhaw! BAWIPA bawilennae hoi bawkim dawk akawi.
6 Nígbà tí ọkùnrin náà dúró ní ẹ̀gbẹ́ mi, mo gbọ́ ẹnìkan tí ó bá mi sọ̀rọ̀ láti inú ilé Ọlọ́run.
Hahoi tami buet touh kaie teng a kangdue lahun nah tami buet touh ni na pato e ka thai teh,
7 Ó sì wí pé, “Ọmọ ènìyàn, èyí yìí ni ibi ìgúnwà mi àti ibi tí ó wà fún àtẹ́lẹsẹ̀ mi. Ibi yìí ni èmi yóò máa gbé ní àárín àwọn ọmọ Israẹli títí láéláé. Ilé Israẹli kò ní ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́ mọ́ láéláé àwọn tàbí àwọn ọba wọn nípa àgbèrè àti àwọn ère aláìlẹ́mìí àwọn ọba wọn ní ibi gíga.
kai koevah, tami capa heteheh, ka bawitungkhung ka tahungnae hmuen, ka khok ka toungnae, Isarel catounnaw koevah, a yungyoe totouh khosak nahane hmuen doeh. Ka min kathoung teh Isarel catounnaw ni amamouh thoseh, a siangpahrangnaw thoseh, ka kâyawtnaw thoseh, siangpahrangnaw e ro pakawpnae hmuenrasang a sak awh teh, khin sak awh mahoeh toe.
8 Nígbà tí wọ́n ba gbé ìloro ilé wọn kángun sí ìloro ilé mi àti ìlẹ̀kùn wọn sì ẹ̀gbẹ́ ìlẹ̀kùn mi, pẹ̀lú ògiri nìkan ní àárín èmi pẹ̀lú wọn, wọ́n ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́ pẹ̀lú ìwà ìríra wọn. Nígbà náà ni mo pa wọ́n run ní ìbínú mi.
Takhang a kâennaw pâhung e teh, kaie takhang kâennae koe a sak awh teh, ahnimae takhang a pâhungnae hah kaie takhang pâhungnae teng a hruek awh teh, ahnimouh hoi kaimanaw rahak vah, tapang buet touh ao sak teh, a sak awh e naw ni ka min kathoung a khin sak awh. Hatdawkvah, ka lungkhueknae hoi ahnimouh ka raphoe han.
9 Nísinsin yìí jẹ́ kí wọn mú ìwà àgbèrè wọn àti àwọn ère aláìlẹ́mìí àwọn ọba wọn kúrò ni iwájú mi, èmi yóò sì gbé àárín wọn láéláé.
A kâyonae hoi ahnimae siangpahrang e ro hah, kai koehoi kahlatpoung lah a tâkhawng awh naseh, kai hi ahnimouh koe a yungyoe kho ka sak han.
10 “Ọmọ ènìyàn, ṣàpèjúwe ilé Ọlọ́run náà fún àwọn ènìyàn Israẹli kí ojú ẹ̀ṣẹ̀ wọn, lè tì wọ́n sì jẹ́ kí wọn wo àwòrán ilé náà,
Nang tami capa, Isarel imthung koevah, bawkim hah patue, a payonnae naw hah a kayakhai awh nahanelah, im e oangnae hah bangnue sin awh naseh.
11 tí ojú gbogbo ohun tí wọn ti ṣe bá tì wọ́n, jẹ́ kí wọ́n mọ̀ àwòrán ilé Ọlọ́run náà bí wọ́n ṣe tò ó lẹ́sẹẹsẹ, àbájáde àti àbáwọlé rẹ̀ gbogbo àwòrán àti gbogbo òfin àti ìlànà rẹ̀. Kọ ìwọ̀nyí sílẹ̀ ní iwájú wọn kí wọn kí ó lè jẹ́ olóòtítọ́ si àwòrán rẹ̀, kí wọ́n sì tẹ̀lé gbogbo òfin rẹ̀.
A sak awh e pueng kayakkhai awh pawiteh, bawkim e oang, tâconae hoi kâennaw a hnonae hoi a khetyawtnae naw hah pâtue haw, ahnimae mithmu vah, thut haw, phunglawk poe e pueng a hnonae naw hah a pâkuem awh vaiteh, a tarawi thai awh nahan,
12 “Èyí yìí ní òfin ilé Ọlọ́run náà. Gbogbo àyíká lórí òkè gíga ní yóò jẹ́ ibi mímọ́ jùlọ. Bí èyí ni òfin tẹmpili náà.
Hetheh bawkim hanelah kâlawk doeh atengpam pueng hoi monsom e naw. hmuen kathoung poung e naw doeh, khenhaw! hetheh bawkim e kâlawk hah doeh.
13 “Ìwọ̀nyí ni wíwọ̀n pẹpẹ ìrúbọ ní gígùn ìgbọ̀nwọ́, ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ni jíjìn, ó sì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ni ìbú, igun rẹ̀ yípo àti etí rẹ̀ jẹ́ ìbú àtẹ́lẹwọ́ kan. Èyí yìí sì ni gíga pẹpẹ ìrúbọ náà.
Khoungroe a saw e padawng toteh, hetheh khoungroe a lennae (dong touh tie hah dong touh hoi kutsampha to touh e doeh), a kamhungnae teh dong touh a rasang, dong touh a kaw, arai petkâkalup lah khap touh ka kaw e hoi a yep teh cum sak lah ao.
14 Láti ìsàlẹ̀ rẹ̀ ni ilẹ̀ títí dé ìsàlẹ̀ igun rẹ̀, ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ méjì ni gíga o sì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ní ìbú. Láti igun rẹ̀ ní ìsàlẹ̀ títí dé igun rẹ̀ ti òkè tí ó yípo pẹpẹ jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rin ní gíga, igun náà sì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ní ìbú.
Khoungroe a rasang e teh, a rahim lae a pâhungnae koehoi, avanlah totouh dong hni touh, a kaw e dong touh, kathoengca hrawtnae hoi kalen e hrawtnae totouh dong pali touh a pha teh, dong touh a kaw.
15 Ibi ìdáná pẹpẹ ìrúbọ náà jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rin ní gíga, ìwo mẹ́rẹ̀ẹ̀rin sì yọrí jáde sókè láti ibi ìdáná.
Khoungroe a rasang e hai dong pali touh a pha teh, ki pali touh a kangdue.
16 Ibi ìdáná pẹpẹ náà jẹ́ igun mẹ́rin mẹ́rin lọ́gbọọgba, ìgbọ̀nwọ́ méjìlá ní gígùn, o sì jẹ ìgbọ̀nwọ́ méjìlá ní ìbú.
Khoungroe teh a takin pali touh a pha teh, ayung dong hrahlaikahni, adangka dong hrahlaikahni a pha.
17 Igun ni apá òkè náà jẹ́ igun mẹ́rin lọ́gbọọgba, ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rìnlá ní gígùn, ó sì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rìnlá ní ìbú, pẹ̀lú etí tí ó jẹ́ ìdajì ìgbọ̀nwọ́, ìsàlẹ̀ rẹ̀ jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan yípo. Àtẹ̀gùn pẹpẹ ìrúbọ náà dojúkọ ìlà-oòrùn.”
A rahim lae a pâhungnae hai takin pali touh a pha, ayung dong hlaipali, adangka dong hlaipali touh a pha. Petkâkalup lah a kaw e khap touh, a hetnae khoungroe petkâkalup lah dong touh a tâco teh a luennae lam teh kanîtholah a kangvawi hanelah a o, telah a ti.
18 Lẹ́yìn náà, ó sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Ìwọ̀nyí yóò jẹ́ òfin fún ìrúbọ ẹbọ sísun àti wíwọ̀n ẹ̀jẹ̀ sórí pẹpẹ nígbà tí a bá mọ pẹpẹ tán.
Hahoi kai koe vah tami capa Bawipa Jehovah ni hettelah a dei, be a sak toteh, khoungroe hnonae a lamthung teh, hmaisawi thueng nahan e hoi a thi kathek nahane doeh.
19 Ẹ̀yin ní láti mú ọ̀dọ́ akọ màlúù gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìrékọjá fún àwọn àlùfáà, tí ó jẹ́ Lefi, tí ìdílé Sadoku tí ó wá sí agbègbè láti ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ fún mi ní Olúwa Olódùmarè wí.
Levih miphun vaihma Zadok catounnaw dawk hoi thaw na ka tawk pouh hanelah, ouk na kahnaikung koevah, yon thueng nahanelah, maitotan na poe han telah Bawipa Jehovah ni a dei.
20 Ẹ ni láti mú lára ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, kí ẹ sì fi sórí ìwo mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí ó wà lórí pẹpẹ, àti lórí igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí ìjókòó náà àti sí gbogbo etí rẹ̀ yípo, ìwọ yóò sì sọ pẹpẹ di mímọ́, ìwọ yóò sì ṣe ètùtù rẹ̀.
A thi hah na la vaiteh, khoungroe ki pali touh hoi a hrawtnae takin pali touh e hoi petkâtue lah na hluk vaiteh, na thoung sak vaiteh yonthanae na sak pouh han.
21 Ìwọ gbọdọ̀ mú akọ màlúù fún ìrékọjá, ìwọ yóò sì sun ún ní apá ibi tí a sàmì sí ní agbègbè ilé Ọlọ́run ní ìta ibi mímọ́.
Yon thueng nahanelah, maito na la vaiteh, a thoungnae hmuen hloilah Bawk im thung kârakuengnae hmuen koe hmai na sawi han.
22 “Ní ọjọ́ kejì ìwọ yóò fi ewúrẹ́, òbúkọ aláìlábàwọ́n fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, a sì gbọdọ̀ sọ pẹpẹ di mímọ́ gẹ́gẹ́ bí a ti ṣọ́ di mímọ́ pẹ̀lú akọ màlúù.
A hnin pahni dawk, kacueme hmaetan, yon thuengnae lah na poe awh han, khoungroe hah maito thi hoi na thoung sak e patetlah hmae thi hoi na sak han.
23 Nígbà tí ìwọ bá parí ìsọdimímọ́, ìwọ yóò fi ọ̀dọ́ akọ màlúù àti ọ̀dọ́ àgbò aláìlábàwọ́n láti inú agbo fún ìrúbọ.
Hote khoungroe hah na thoung sak hnukkhu toun ka tawn hoeh e maitotanca hoi kacueme hmaetan hah BAWIPA e hmalah na poe han.
24 Ìwọ yóò mú wọn lọ sí iwájú Olúwa, àwọn àlùfáà ni yóò fi iyọ̀ wọ́n wọn, wọn yóò sì fi wọ́n rú ẹbọ sísun sí Olúwa.
Vaihmanaw ni palawi a phuen awh vaiteh, hote satheinaw hah BAWIPA hanelah, hmaisawi thuengnae lah a poe han.
25 “Fún ọjọ́ méje, ìwọ ní láti pèsè akọ ewúrẹ́ kan lójoojúmọ́ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀; ìwọ yóò sì pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù àti àgbò láti inú agbo, méjèèjì yóò sì jẹ́ aláìlábàwọ́n.
Hnin sari touh thung hnintangkuem hmae buet touh hah yon thuengnae lah na hno awh han. Toun kaawm hoeh e maitotanca hoi tutan buet touh hai na hno han.
26 Fún ọjọ́ méje wọn yóò jẹ́ ètùtù fún pẹpẹ, wọn yóò sì sọ ọ́ di mímọ́; nípa bẹ́ẹ̀ wọn yóò yà á sọ́tọ̀.
Hnin sari touh thung khoungroe yonthanae na sak vaiteh na thoungsak han. Nama hoi nama hai vaihma e a hmuen dawk na kâpoe han.
27 Ní ìparí ọjọ́ wọ̀nyí, láti ọjọ́ mẹ́jọ síwájú, àwọn àlùfáà ni yóò gbé àwọn ẹbọ sísun rẹ àti ẹbọ ìdàpọ̀ rẹ̀ kalẹ̀ lórí pẹpẹ. Lẹ́yìn náà, èmi yóò tẹ́wọ́gbà yín ní Olúwa Olódùmarè wí.”
A hnin sari a loumhoehnae a hnin hnin taroe hnin dawk thoseh, hote hnin koehoi vaihmanaw ni thuengnae thoseh, khoungroe van a poe awh han. Hmaisawi thuengnae hoi roum thuengnae naw hah a poe awh vaiteh, nangmanaw kai ni na coe awh han telah Bawipa Jehovah ni a dei telah a ti.

< Ezekiel 43 >