< Ezekiel 43 >

1 Lẹ́yìn náà ọkùnrin náà mú mi gba ti ẹnu-ọ̀nà tí ó dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn,
Te phoeiah kai te vongka taengla n'caeh puei. Vongka te khothoeng longpuei la mael.
2 mo sì ri ògo Ọlọ́run Israẹli ń bọ láti ìhà ìlà-oòrùn. Ohùn rẹ̀ dàbí híhó omi, ìtànṣán ògo rẹ̀ sì bo ilẹ̀.
Te vaengah Israel Pathen kah thangpomnah tah khothoeng longpuei lamloh tarha ha thoeng. A ol te tui yet ol bangla lo tih diklai te a thangpomnah neh a tue.
3 Ó sì dàbí ìran tí mo rí, gẹ́gẹ́ bí ìran tí mo rí nígbà tí mo wá láti pa ìlú náà run; ìran náà sì dà bí ìran tí mo rí lẹ́bàá odò Kebari, mo sì dojú mi bolẹ̀.
Mueimae pakhat te a mueimae phek ka hmuh. Khopuei phae ham kai taengla ha pawk vaengkah ka hmuh mueimae phek la om. Mangthui khaw Kebar tuiva kah ka hmuh mueimae bangla om tih ka maelhmai te ka buenglueng.
4 Ògo Olúwa gba ọ̀nà tí o dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn wọ inú ilé Ọlọ́run wá.
Te vaengah BOEIPA kah thangpomnah tah khothoeng longpuei lamloh a hmai vongka longah imkhui la kun.
5 Mo ni ìrusókè ẹ̀mí, ó sì mú mi lọ inú ilé ìdájọ́, sì kíyèsi ògo Olúwa kún inú ilé Ọlọ́run.
Te phoeiah Mueihla loh kai te m'pom tih vongtung khui la kai te n'khuen. Te vaengah im te BOEIPA kah thangpomnah neh tarha bae.
6 Nígbà tí ọkùnrin náà dúró ní ẹ̀gbẹ́ mi, mo gbọ́ ẹnìkan tí ó bá mi sọ̀rọ̀ láti inú ilé Ọlọ́run.
Te vaengah im lamloh kai m'voek te ka yaak tih kai taengah aka pai hlang pakhat om.
7 Ó sì wí pé, “Ọmọ ènìyàn, èyí yìí ni ibi ìgúnwà mi àti ibi tí ó wà fún àtẹ́lẹsẹ̀ mi. Ibi yìí ni èmi yóò máa gbé ní àárín àwọn ọmọ Israẹli títí láéláé. Ilé Israẹli kò ní ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́ mọ́ láéláé àwọn tàbí àwọn ọba wọn nípa àgbèrè àti àwọn ère aláìlẹ́mìí àwọn ọba wọn ní ibi gíga.
Te phoeiah kai taengah, “Hlang capa aw, he he ka ngolkhoel hmuen neh ka kho kah khopha hmuen ni. Israel ca rhoek lakli ah kumhal duela kho ka sak pahoi vetih ka ming cim te amih Israel imkhui neh a manghai rhoek loh a pumyoihnah nen khaw a hmuensang kah a manghai rhok nen khaw poeih uh voel mahpawh.
8 Nígbà tí wọ́n ba gbé ìloro ilé wọn kángun sí ìloro ilé mi àti ìlẹ̀kùn wọn sì ẹ̀gbẹ́ ìlẹ̀kùn mi, pẹ̀lú ògiri nìkan ní àárín èmi pẹ̀lú wọn, wọ́n ba orúkọ mímọ́ mi jẹ́ pẹ̀lú ìwà ìríra wọn. Nígbà náà ni mo pa wọ́n run ní ìbínú mi.
A cingkhaa te ka cingkhaa taengah, a rhungsut te ka rhungsut taengah a khueh uh tih kai laklo neh amih laklo ah pangbueng ni a om coeng. Ka ming cim he amamih kah tueilaehkoi a saii uh neh a poeih uh. Te dongah ni ka thintoek ah amih te ka thup.
9 Nísinsin yìí jẹ́ kí wọn mú ìwà àgbèrè wọn àti àwọn ère aláìlẹ́mìí àwọn ọba wọn kúrò ni iwájú mi, èmi yóò sì gbé àárín wọn láéláé.
Amih kah pumyoihnah neh a manghai rhok te kai lamloh lakhla laeh saeh. Te daengah ni amih lakli ah kumhal duela kho ka sak eh.
10 “Ọmọ ènìyàn, ṣàpèjúwe ilé Ọlọ́run náà fún àwọn ènìyàn Israẹli kí ojú ẹ̀ṣẹ̀ wọn, lè tì wọ́n sì jẹ́ kí wọn wo àwòrán ilé náà,
Nang hlang capa aw, Israel imkhui taengah im kawng te puen pah. Te daengah ni amamih kah thaesainah dongah a hmaithae uh vetih a cungkuemnah nen khaw a nueh u eh.
11 tí ojú gbogbo ohun tí wọn ti ṣe bá tì wọ́n, jẹ́ kí wọ́n mọ̀ àwòrán ilé Ọlọ́run náà bí wọ́n ṣe tò ó lẹ́sẹẹsẹ, àbájáde àti àbáwọlé rẹ̀ gbogbo àwòrán àti gbogbo òfin àti ìlànà rẹ̀. Kọ ìwọ̀nyí sílẹ̀ ní iwájú wọn kí wọn kí ó lè jẹ́ olóòtítọ́ si àwòrán rẹ̀, kí wọ́n sì tẹ̀lé gbogbo òfin rẹ̀.
Im kah a khui a lam a saii uh boeih te a hmai a thae uh atah a hmuenmol khaw, a thoengnah neh a kunnah khaw, a khui a lam boeih neh a khosing boeih khaw, ka khui ka lam boeih neh a khui a lam khaw, a olkhueng cungkuem dongkah a olkhueng khaw amih te ming sak. Amih mikhmuh ah daek lamtah a khui a lam boeih ngaithuen uh saeh. Te daengah ni a khosing boeih te a vai uh eh.
12 “Èyí yìí ní òfin ilé Ọlọ́run náà. Gbogbo àyíká lórí òkè gíga ní yóò jẹ́ ibi mímọ́ jùlọ. Bí èyí ni òfin tẹmpili náà.
He tah tlang som im kah olkhueng ni. A khorhi kaep, kaep boeih tah cim rhoela cim. He he im kah olkhueng ni ne.
13 “Ìwọ̀nyí ni wíwọ̀n pẹpẹ ìrúbọ ní gígùn ìgbọ̀nwọ́, ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ni jíjìn, ó sì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ni ìbú, igun rẹ̀ yípo àti etí rẹ̀ jẹ́ ìbú àtẹ́lẹwọ́ kan. Èyí yìí sì ni gíga pẹpẹ ìrúbọ náà.
He rhoek he a dong la a dong vaengkah hmueihtuk cungnueh coeng ni. [Te te dong khat neh kutsom pakhat lo]. Tungngol dong khat lo tih a daang dong khat neh a rhi hmoi ah khap at phueih om. He tah hmueihtuk dongkah sawn bong ni.
14 Láti ìsàlẹ̀ rẹ̀ ni ilẹ̀ títí dé ìsàlẹ̀ igun rẹ̀, ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ méjì ni gíga o sì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ní ìbú. Láti igun rẹ̀ ní ìsàlẹ̀ títí dé igun rẹ̀ ti òkè tí ó yípo pẹpẹ jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rin ní gíga, igun náà sì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan ní ìbú.
Diklai tungngol lamloh tungkha hmui hil dong nit neh a daang dong khat lo. Tungkha ca lamloh tungkha puei duela dong li neh a daang dong khat lo.
15 Ibi ìdáná pẹpẹ ìrúbọ náà jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rin ní gíga, ìwo mẹ́rẹ̀ẹ̀rin sì yọrí jáde sókè láti ibi ìdáná.
Hmueihtuk tlang te hmueihtuk lamloh dong li hil a ki pali la cawn hang.
16 Ibi ìdáná pẹpẹ náà jẹ́ igun mẹ́rin mẹ́rin lọ́gbọọgba, ìgbọ̀nwọ́ méjìlá ní gígùn, o sì jẹ ìgbọ̀nwọ́ méjìlá ní ìbú.
Hmueihtuk te a yun hlai nit, a daang hlai nit neh a vae pali la hniboeng bangla om.
17 Igun ni apá òkè náà jẹ́ igun mẹ́rin lọ́gbọọgba, ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rìnlá ní gígùn, ó sì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́rìnlá ní ìbú, pẹ̀lú etí tí ó jẹ́ ìdajì ìgbọ̀nwọ́, ìsàlẹ̀ rẹ̀ jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ kan yípo. Àtẹ̀gùn pẹpẹ ìrúbọ náà dojúkọ ìlà-oòrùn.”
Tungkha te a yun hlai li neh a daang hlai li lo saeh. A vae pali neh a rhi taengah dong kaek neh a tungngol te a kaepvai duela dong khat lo. A tangtlaeng te khothoeng la hooi saeh,” a ti.
18 Lẹ́yìn náà, ó sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Ìwọ̀nyí yóò jẹ́ òfin fún ìrúbọ ẹbọ sísun àti wíwọ̀n ẹ̀jẹ̀ sórí pẹpẹ nígbà tí a bá mọ pẹpẹ tán.
Te phoeiah kai taengah, “Hlang capa aw, ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. A soah hmueihhlutnah khuen ham neh a soah thii haeh ham hmueihtuk kah khosing he amah a saii khohnin ah coeng.
19 Ẹ̀yin ní láti mú ọ̀dọ́ akọ màlúù gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìrékọjá fún àwọn àlùfáà, tí ó jẹ́ Lefi, tí ìdílé Sadoku tí ó wá sí agbègbè láti ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ fún mi ní Olúwa Olódùmarè wí.
Te dongah Levi khosoih rhoek taengah pae kuekluek laeh. Amih Zadok tiingan lamloh ka taengah ha yoei uh. He tah ka Boeipa Yahovah kah olphong ni. Vaitotal te kai aka bong la, saelhung ca te boirhaem la om saeh.
20 Ẹ ni láti mú lára ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, kí ẹ sì fi sórí ìwo mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí ó wà lórí pẹpẹ, àti lórí igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí ìjókòó náà àti sí gbogbo etí rẹ̀ yípo, ìwọ yóò sì sọ pẹpẹ di mímọ́, ìwọ yóò sì ṣe ètùtù rẹ̀.
A thii te lo lamtah a ki pali dongah khaw, tungkha bangkil pali dongah khaw, a rhi kaepvai ah hluk. Te dongah te te cim sak lamtah dawth kuekluek.
21 Ìwọ gbọdọ̀ mú akọ màlúù fún ìrékọjá, ìwọ yóò sì sun ún ní apá ibi tí a sàmì sí ní agbègbè ilé Ọlọ́run ní ìta ibi mímọ́.
Vaitotal te boirhaem la khuen lamtah rhokso voel kah im hloeh ah hoeh.
22 “Ní ọjọ́ kejì ìwọ yóò fi ewúrẹ́, òbúkọ aláìlábàwọ́n fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, a sì gbọdọ̀ sọ pẹpẹ di mímọ́ gẹ́gẹ́ bí a ti ṣọ́ di mímọ́ pẹ̀lú akọ màlúù.
A hnin bae ah maae ca hmabuet te boirhaem la khuen. Te vaengah hmueihtuk te vaitotal neh a ciim uh bangla ciim uh saeh.
23 Nígbà tí ìwọ bá parí ìsọdimímọ́, ìwọ yóò fi ọ̀dọ́ akọ màlúù àti ọ̀dọ́ àgbò aláìlábàwọ́n láti inú agbo fún ìrúbọ.
Na ciim bawt bawt ah saelhung ca khuikah vaitotal hmabuet neh boiva khui lamloh tutal hmabuet te na nawn ni.
24 Ìwọ yóò mú wọn lọ sí iwájú Olúwa, àwọn àlùfáà ni yóò fi iyọ̀ wọ́n wọn, wọn yóò sì fi wọ́n rú ẹbọ sísun sí Olúwa.
Te te BOEIPA mikhmuh la khuen lamtah khosoih rhoek loh lungkaeh phul thil saeh. Te phoeiah BOEIPA taengah hmueihhlutnah la khuen saeh.
25 “Fún ọjọ́ méje, ìwọ ní láti pèsè akọ ewúrẹ́ kan lójoojúmọ́ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀; ìwọ yóò sì pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù àti àgbò láti inú agbo, méjèèjì yóò sì jẹ́ aláìlábàwọ́n.
Hnin rhih khuiah saii lamtah, hnin at dongkah boirhaem la maae khaw, saelhung ca khuikah tah vaitotal khaw, boiva khuikah tah tutal khaw a hmabuet te nawn uh saeh.
26 Fún ọjọ́ méje wọn yóò jẹ́ ètùtù fún pẹpẹ, wọn yóò sì sọ ọ́ di mímọ́; nípa bẹ́ẹ̀ wọn yóò yà á sọ́tọ̀.
Hnin rhih khuiah hmueihtuk te dawth uh saeh lamtah caihcil uh saeh. Te daengah ni a kut, a kut ah a cung u eh.
27 Ní ìparí ọjọ́ wọ̀nyí, láti ọjọ́ mẹ́jọ síwájú, àwọn àlùfáà ni yóò gbé àwọn ẹbọ sísun rẹ àti ẹbọ ìdàpọ̀ rẹ̀ kalẹ̀ lórí pẹpẹ. Lẹ́yìn náà, èmi yóò tẹ́wọ́gbà yín ní Olúwa Olódùmarè wí.”
Khohnin te cup tih hnin rhet dongla ana om ni. Te phoeiah tah nangmih kah hmueihhlutnah neh rhoepnah te khosoih rhoek loh hmueihtuk dongla khueh uh saeh lamtah nangmih te kan moeithen bitni. He tah ka Boeipa Yahovah kah olphong ni,” a ti.

< Ezekiel 43 >