< Ezekiel 4 >

1 “Nísinsin yìí, ìwọ ọmọ ènìyàn, mú amọ̀ ṣíṣù kan, gbé e sí iwájú rẹ, kí o sì ya àwòrán ìlú Jerusalẹmu sí orí rẹ̀.
Kami capa, kangphaek daek amlai long to la ah, na hma ah suem ah loe, a nuiah Jerusalem, vangpui krang to soi ah;
2 Kí o sì dó tì í, kí o sì mọ ilé ìṣọ́ tì í, kí o sì mọ odi tì í, kí o sì gbé ogun sí i, kí o sì to òòlù yí i ká.
vangpui to takui ah, misa buephaih im to sah ah loe, sipae to thungah; misatuh kaminawk to pakhueng ah loe, a taengah thing abumnawk to suem boih ah.
3 Kí o sì fi àwo irin kan ṣe ògiri láàrín rẹ̀ àti ìlú yìí, kí o sì kọjú sí i, a ó sì dó tì í, ìwọ yóò sì dó tì í. Èyí yóò jẹ́ àmì fún ilé Israẹli.
To pacoengah nangmah hoi vangpui salakah, sum sipae to thung ah; na mikhmai vangpui bangah anghae hmah, to tiah na takui baktih toengah, vang pui takui khoephaih to om tih. Hae loe Israel imthung takoh hanah angmathaih ah om tih.
4 “Lẹ́yìn èyí, lọ fi ẹ̀gbẹ́ òsì dùbúlẹ̀, kí o sì gbé ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli lé orí ara rẹ. Iye ọjọ́ tí ìwọ bá fi sùn náà ni ìwọ yóò fi ru ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Banqoi bangah angqoi ah loe, angsong ah, a nuiah Isarael imthung takoh zaehaih to amtii ah; to tiah nang songhaih ni zetto nihcae zaehaih to na phaw tih.
5 Nítorí mo fi iye ọdún tí wọ́n fi ṣẹ̀ fún ọ gẹ́gẹ́ bí iye ọjọ́ tí ìwọ yóò lò. Nítorí náà, ìwọ yóò ru ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli fún irinwó ọjọ́ ó dín mẹ́wàá.
Ani nambat baktih toengah, nihcae zaehaih saningnawk to na nuiah kam tik boeh; to pongah ni cumvai thum, qui takawtto thung, Israel imthung takoh zaehaih to na phaw tih.
6 “Tí o bá parí èyí, tún fi ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún dùbúlẹ̀ kí o sì ru ẹ̀ṣẹ̀ ilé Juda fún ogójì ọjọ́, nítorí pé ọjọ́ kan ló dúró fún ọdún kan.
To tiah na sak pacoengah, bantang bangah angqoi ah loe, angsong let ah, vaihi loe Judah imthung takoh zaehaih to ni qui palito thung na phaw tih; nang hanah nito hae saningto ah kang suek pae.
7 Ìwọ dojúkọ ìgbógunti Jerusalẹmu, na ọwọ́ rẹ sí i, kí o sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ìlú náà.
To tiah na takui ih Jerusalem to anghae thui ah, ban payangh loe, vangpui misa haih lok to thui ah.
8 Èmi yóò dè ọ́ ní okùn dé bi pé ìwọ kò ní í le yírapadà láti ìhà ọ̀tún sí ìhà òsì títí tí ọjọ́ ìgbóguntì rẹ yóò fi pé.
Khenah, na takuihaih ni boeng ai karoek to, hae bang hoi ho bangah nang qoi thaih han ai ah, qui hoiah kang taoeng han.
9 “Mú alikama, ọkà bàbà àti barle, erèé àti lẹntili, jéró àti ẹwẹ; fi àwọn nǹkan wọ̀nyí ṣe àkàrà tí ìwọ yóò máa jẹ nígbà tí ìwọ bá dùbúlẹ̀ fún irinwó ọjọ́ ó dín mẹ́wàá.
Ata dip, barli dip, peh, peh kathim, maket hoi tunhnawk to la ah, laom maeto thungah atok ah loe, takaw to sah ah; panak bang hoi nang songhaih ni, cumvai thum, qui takawtto karoek to takaw to buh ah caa ah.
10 Wọn òsùwọ̀n ogún ṣékélì oúnjẹ tí ìwọ yóò máa jẹ lójoojúmọ́ kí o sì máa jẹ ẹ́ ní àkókò tí a ti yà sọ́tọ̀.
To takaw to tah ah loe, nito naah shekel pumto caa ah; atue phak naah caa ah.
11 Bákan náà, wọn ìdámẹ́fà omi, kí ìwọ ó sì máa mú ní àkókò tí a yà sọ́tọ̀.
To tiah tui to tah pacoengah, pailang hin vai tarukto ah tapraek ah loe, nae ah; atue phak naah nae ah.
12 Ìwọ yóò sì jẹ ẹ́ bí àkàrà barle; dín in ní ojú àwọn ènìyàn, ìgbẹ́ ènìyàn ni kí o fi dáná rẹ.”
Barli cang hoi sak ih takaw to buh ah caa ah; Kaminawk mikhnuk ah, kami aek kazaek hoiah takaw to hmai pahai ah, tiah ang naa.
13 Olúwa sọ pé, “Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli yóò jẹ oúnjẹ àìmọ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí èmi yóò lé wọn lọ.”
Angraeng mah, Israel kaminawk ka haek ih prae, Gentel kaminawk salakah angmacae mah amhnongsak ih ciimcai ai buh to caa o tih, tiah thuih.
14 Nígbà náà ni mo wí pé, “Háà! Kò rí bẹ́ẹ̀ Olúwa Olódùmarè! Láti ìgbà èwe mi di ìsinsin yìí èmi kò tí ì sọ ara mi di aláìmọ́ rí. Èmi kò tí ì jẹ ohun tó kú fúnra rẹ̀ tàbí èyí tí ẹranko búburú fàya pẹ́rẹpẹ̀rẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹran àìmọ́ kan kò tí ì wọ ẹnu mi rí.”
To naah kai mah, Angraeng Sithaw, khenah, ka hinghaih kam hnongsak ai vop, thendoeng nathuem hoi vaihi khoek to, angmah koeh ah kadueh moi, to tih ai boeh loe moi kasan mah kaek ih moi to ka caa vai ai vop; panuet kathok moi roe ka pakha thungah akun vai ai vop, tiah ka naa.
15 Nígbà náà ló wí fún mi pé, “Wò ó, Èmi ó fún ọ ní ìgbẹ́ màlúù dípò ìgbẹ́ ènìyàn. Èmi yóò mú ki ó dín àkàrà rẹ lórí ìgbẹ́ màlúù dípò ìgbẹ́ ènìyàn.”
To pacoengah anih mah, Khenah, kami ih aek na ai maitaw aek to kang paek, maitaw aek hoiah takaw to pahai ah, tiah ang naa.
16 Ó sì tún sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, èmi yóò dáwọ́ ìpèsè oúnjẹ dúró ní Jerusalẹmu. Ní pípín ni àwọn ènìyàn yóò máa pín oúnjẹ jẹ pẹ̀lú ìfọkànsọ́nà bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni wọn yóò máa mu omi pẹ̀lú ìdààmú,
To pacoengah anih mah kai khaeah, Kami capa, khenah, Jerusalem comhaih takaw to ka boengsak ving han; kaminawk mah buh to tah o ueloe, mawnhaih hoiah caa o tih; tui doeh tah o ueloe, dawnraihaih hoiah nae o tih,
17 nítorí pé oúnjẹ àti omi yóò wọ́n. Wọn yóò máa wo ara wọn pẹ̀lú ìyanu, èmi yóò sì jẹ́ kí wọ́n ṣọ̀fọ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
takaw hoi tui khahaih to om tih, maeto hoi maeto dawnraihaih hoiah om o ueloe, angmacae zaehaih pongah dueh o boih tih.

< Ezekiel 4 >