< Ezekiel 4 >
1 “Nísinsin yìí, ìwọ ọmọ ènìyàn, mú amọ̀ ṣíṣù kan, gbé e sí iwájú rẹ, kí o sì ya àwòrán ìlú Jerusalẹmu sí orí rẹ̀.
Gode da amane sia: i, “Dunu egefe! Laga osoboga hamoi igi (baligi) lale, dia midadi ligisima. Amo da: iya Yelusaleme moilai bai bagade ea fedege ilegesu dedema.
2 Kí o sì dó tì í, kí o sì mọ ilé ìṣọ́ tì í, kí o sì mọ odi tì í, kí o sì gbé ogun sí i, kí o sì to òòlù yí i ká.
Eno dunu da Yelusaleme amoma doagala: mu. Amo olelema: ne, laga osoboga hamoi igi amoga ilegele, gegesu adobo amola gegemusa: moi gasagala: su, amola ha wa: i fisisu, amola logo gagili sali damana ifa damuiga dousosu, amo Yelusaleme sisiga: le, ilegele dedema.
3 Kí o sì fi àwo irin kan ṣe ògiri láàrín rẹ̀ àti ìlú yìí, kí o sì kọjú sí i, a ó sì dó tì í, ìwọ yóò sì dó tì í. Èyí yóò jẹ́ àmì fún ilé Israẹli.
Gula yaeya lale, amoga dia ilegele dedei amo di ga: le, dogoa bugisima. Ilegele dedei amoma ba: le gusulisima. Fedege agoane, di da Yelusaleme moilai bai bagade amoma doagala: lala. Amo da Isala: ili fi ilima dawa: digima: ne fedegele olelesa.
4 “Lẹ́yìn èyí, lọ fi ẹ̀gbẹ́ òsì dùbúlẹ̀, kí o sì gbé ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli lé orí ara rẹ. Iye ọjọ́ tí ìwọ bá fi sùn náà ni ìwọ yóò fi ru ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
5 Nítorí mo fi iye ọdún tí wọ́n fi ṣẹ̀ fún ọ gẹ́gẹ́ bí iye ọjọ́ tí ìwọ yóò lò. Nítorí náà, ìwọ yóò ru ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli fún irinwó ọjọ́ ó dín mẹ́wàá.
Amasea, dia fofadini diasa: ima. Na da di se nabima: ne, Isala: ili fi ilia wadela: i hou dabe dima imunu. Di da eso 390 agoane mae delegili, se nabawane fofadinimusu dialumu. Bai ilia wadela: i hou hamobeba: le, di da se nabimu. Na dima se imunu agoane ilegei. Na da dima eso 390 amoga se imunu. Be Isala: ili fi ilima Na da ode 390 amoga se imunu.
6 “Tí o bá parí èyí, tún fi ẹ̀gbẹ́ ọ̀tún dùbúlẹ̀ kí o sì ru ẹ̀ṣẹ̀ ilé Juda fún ogójì ọjọ́, nítorí pé ọjọ́ kan ló dúró fún ọdún kan.
Amo hou dagosea, di bu lobodafadini delegima. Amogai diala, Yuda dunu ilia wadela: i hou dabe lama: ne, eso 40 agoane dialoma. Bai Na da Yuda fi dunu ilima ode 40 amoga se ima: ne ilegei dagoi.
7 Ìwọ dojúkọ ìgbógunti Jerusalẹmu, na ọwọ́ rẹ sí i, kí o sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa ìlú náà.
Yelusaleme amoma doagala: be amo noga: le sosodolaloma. Yelusaleme amoma ougiwane lobo usunawele sia: ne igugulaloma. Na da Yelusaleme fi ilima se imunu, amo gasa fili olelelaloma.
8 Èmi yóò dè ọ́ ní okùn dé bi pé ìwọ kò ní í le yírapadà láti ìhà ọ̀tún sí ìhà òsì títí tí ọjọ́ ìgbóguntì rẹ yóò fi pé.
Na da di mae delegima: ne, la: gilisili dialeawane, Yelusaleme amoma doagala: su baligisia fawane yolesimu.
9 “Mú alikama, ọkà bàbà àti barle, erèé àti lẹntili, jéró àti ẹwẹ; fi àwọn nǹkan wọ̀nyí ṣe àkàrà tí ìwọ yóò máa jẹ nígbà tí ìwọ bá dùbúlẹ̀ fún irinwó ọjọ́ ó dín mẹ́wàá.
Waha di da widi, bali, da: iyene, da: iyene agoai eno, amola agoai eno fage, amo lale, gilisili bibiagone, agi ga: gi hamoma. Di da eso 390 amoga, dia lobo fofadini musu dialawane, amo fawane nanoma.
10 Wọn òsùwọ̀n ogún ṣékélì oúnjẹ tí ìwọ yóò máa jẹ lójoojúmọ́ kí o sì máa jẹ ẹ́ ní àkókò tí a ti yà sọ́tọ̀.
Na da di moma: ne, agi 230 gala: me fawane ilegei.
11 Bákan náà, wọn ìdámẹ́fà omi, kí ìwọ ó sì máa mú ní àkókò tí a yà sọ́tọ̀.
Amola di da hano fonobahadi fawane manu galebe. Di da eso afae ganodini faigelei nabai aduna fawane manu.
12 Ìwọ yóò sì jẹ ẹ́ bí àkàrà barle; dín in ní ojú àwọn ènìyàn, ìgbẹ́ ènìyàn ni kí o fi dáná rẹ.”
Di da dunu iga hafoga: i amoga lalu didili, amo da: iya agi gobele, dunu huluane ba: ma: ne moma.”
13 Olúwa sọ pé, “Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli yóò jẹ oúnjẹ àìmọ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí èmi yóò lé wọn lọ.”
Hina Gode da amane sia: i, “Amo da dawa: digima: ne agoane olelemusa: hamoi. Na da Isala: ili fi dunu ga fifi asi gala sogega afagogosea, ilia da sema ha: i nasu manu.”
14 Nígbà náà ni mo wí pé, “Háà! Kò rí bẹ́ẹ̀ Olúwa Olódùmarè! Láti ìgbà èwe mi di ìsinsin yìí èmi kò tí ì sọ ara mi di aláìmọ́ rí. Èmi kò tí ì jẹ ohun tó kú fúnra rẹ̀ tàbí èyí tí ẹranko búburú fàya pẹ́rẹpẹ̀rẹ. Bẹ́ẹ̀ ni ẹran àìmọ́ kan kò tí ì wọ ẹnu mi rí.”
Be na da bu adole i, “Hina Gode Ouligisudafa! Hame mabu! Na da wadela: i ledo hou hamedafa hamosu. Na goi hadiga ganini, na da ohe hi udigili bogoi o ea samaga fai amo ea hu na da hamedafa nasu. Na da sema ledo hamoi ha: i manu hamedafa nasu.”
15 Nígbà náà ló wí fún mi pé, “Wò ó, Èmi ó fún ọ ní ìgbẹ́ màlúù dípò ìgbẹ́ ènìyàn. Èmi yóò mú ki ó dín àkàrà rẹ lórí ìgbẹ́ màlúù dípò ìgbẹ́ ènìyàn.”
Amaiba: le, Gode da amane sia: i, “Amai galea, di da amo hou bu fisili, bulamagau iga, amoga lalu didili, dia agi gobema: ne Na da ilegesa.”
16 Ó sì tún sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, èmi yóò dáwọ́ ìpèsè oúnjẹ dúró ní Jerusalẹmu. Ní pípín ni àwọn ènìyàn yóò máa pín oúnjẹ jẹ pẹ̀lú ìfọkànsọ́nà bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni wọn yóò máa mu omi pẹ̀lú ìdààmú,
Amola E da eno amane sia: i, “Dunu egefe! Na da Yelusaleme dunu ilia ha: i nasu logo hedofamu. Ilia da ha: i manu amola hano fonobahadi fawane enoenoi amoma iabeba: le, ilia da da: i dione amola heawini se nabawane esalumu.
17 nítorí pé oúnjẹ àti omi yóò wọ́n. Wọn yóò máa wo ara wọn pẹ̀lú ìyanu, èmi yóò sì jẹ́ kí wọ́n ṣọ̀fọ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Ilia agi amola hano amola ebelei dagoi ba: mu. Ilia baligiliwane se nabimu. Ilia wadela: i hou hamobeba: le, geloga: gia: mu.”