< Ezekiel 38 >

1 Ọrọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Na rĩrĩ, kiugo kĩa Jehova nĩkĩanginyĩrĩire, ngĩĩrwo atĩrĩ:
2 “Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ sí Gogu, ti ilẹ̀ Magogu; olórí ọmọ-aládé, Meṣeki, àti Tubali sọtẹ́lẹ̀ ní ìlòdì sí i
“Mũrũ wa mũndũ, erekeria ũthiũ waku harĩ Gogu wa kũu bũrũri wa Magogu, ũcio mũnene wa anene a Mesheki na Tubali; mũrathĩre ũhoro wa kũmũũkĩrĩra,
3 kí ó sì wí pé, ‘Èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Èmi lòdì sí ọ, ìwọ Gogu, olórí ọmọ-aládé, Meṣeki àti Tubali.
ũmwĩre atĩrĩ: ‘Mwathani Jehova ekuuga ũũ: Nĩngũgũũkĩrĩra, wee Gogu, mũnene wa anene a Mesheki na Tubali.
4 Èmi yóò yí ọ kiri, èmi yóò sì fi ìwọ̀ kọ́ ọ ní ẹnu, èmi yóò sì fà ọ́ jáde pẹ̀lú gbogbo ọmọ-ogun rẹ, àwọn ẹṣin àti àwọn agẹṣinjagun nínú ìhámọ́ra, àti ìpéjọ ńlá pẹ̀lú asà ogun ńlá àti kéékèèké, gbogbo wọn ń fi idà wọn.
Nĩngakũhũgũra, ngwĩkĩre ndwano thĩa-inĩ ciaku, na ngũrute na nja hamwe na mbũtũ ciaku ciothe cia ita: nĩcio mbarathi ciaku, na andũ aku arĩa mathiiaga mahaicĩte mbarathi meeohete indo cia mbaara, na kĩrĩndĩ kĩnene kĩrĩ na ngo iria nene na iria nini, othe makĩhiũragia hiũ ciao cia njora.
5 Persia, Kuṣi àti Puti yóò wà pẹ̀lú wọn, gbogbo wọn yóò wà pẹ̀lú asà àti ìṣíborí wọn
Nao andũ a Perisia, na Kushi, na Putu magaakorwo hamwe nao, othe manyiitĩte ngo na magekĩra ngũbia cia kĩgera,
6 Gomeri náà pẹ̀lú gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, àti Beti-Togarma láti jìnnàjìnnà àríwá pẹ̀lú gbogbo àwọn ọ̀wọ́ ogun rẹ̀—ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè pẹ̀lú rẹ̀.
o na Gomeri na thigari ciakuo ciothe, o na andũ a Bethi Togarima moimĩte kũraya mwena wa gathigathini marĩ na mbũtũ cia ita ciakuo ciothe, o ndũrĩrĩ icio nyingĩ irĩ hamwe nawe.
7 “‘Múra sílẹ̀, múra tán, kí ìwọ àti gbogbo ìjọ náà péjọpọ̀ pẹ̀lú rẹ, kí o sì pàṣẹ fún wọn.
“‘Wĩthagathage; wĩhaarĩrie, wee mwene hamwe na kĩrĩndĩ kĩrĩa gĩothe gĩgũthiũrũrũkĩirie, nawe ũgĩathe.
8 Lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́, àwa yóò bẹ̀ ọ wò; ní ọdún ìkẹyìn ìwọ yóò dó ti ilẹ̀ tí a ti gbà padà lọ́wọ́ idà, tí àwọn ènìyàn wọn kórajọ pọ̀ láti ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè sí àwọn òkè gíga ti Israẹli, tí ó ti di ahoro fún ìgbà pípẹ́. A ti mú wọn jáde láti ọ̀dọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè, nísinsin yìí gbogbo wọn ń gbé ní àìléwu.
Thuutha wa matukũ maingĩ, nĩmũgetwo mũthiĩ ita-inĩ. Mĩaka-inĩ ya thuutha nĩmũgatharĩkĩra bũrũri ũgaakorwo ũhonoketio kuuma mbaara-inĩ, ũrĩa andũ aguo maacookanĩrĩirio kuuma ndũrĩrĩ-inĩ nyingĩ magĩtwarwo irĩma-inĩ icio cia bũrũri wa Isiraeli, kũrĩa gũtũũrĩte gũkirĩte ihooru. Acio marutĩtwo ndũrĩrĩ-inĩ icio, na rĩu acio othe maikaraga na thayũ.
9 Ìwọ àti ọ̀wọ́ ogun rẹ àti ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè pẹ̀lú rẹ yóò gòkè, ẹ̀yin yóò tẹ̀síwájú bí ìjì; ìwọ yóò dàbí ìkùùkuu tí ó bo ilẹ̀ mọ́lẹ̀.
Wee hamwe na mbũtũ ciaku ciothe cia ita na ndũrĩrĩ icio nyingĩ mũrĩ nacio nĩmũkambata, mũmaguthũkĩre ta kĩhuhũkanio; mũgaatuĩka ta itu rĩhumbĩrĩte bũrũri.
10 “‘Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Ní ọjọ́ náà èrò kan yóò wá sọ́kàn rẹ, ìwọ yóò sì pète ìlànà búburú.
“‘Mwathani Jehova ekuuga ũũ: Mũthenya ũcio wee nĩũkagĩa na meciiria, nawe nĩũgathugunda ũndũ mũũru.
11 Ìwọ yóò wí pé, “Èmi yóò gbé ogun ti ilẹ̀ àwọn tí a kò fi odi yíká, Èmi yóò gbé ogun ti àwọn ènìyàn àlàáfíà tí a kò funra sí gbogbo wọn ń gbé ní àìsí odi, ní àìsí ẹnu-ọ̀nà òde àti àsígbè-irin.
Nawe nĩũkoiga atĩrĩ, “Nĩngũtharĩkĩra bũrũri ũrĩa wa matũũra matarĩ mairigĩre; nĩngũhithũkĩra andũ marĩ na thayũ na matarekũũa ũndũ, arĩa othe maikaraga matũũra matarĩ mairigĩre, na matarĩ ihingo na mĩgĩĩko.
12 Èmi yóò mú ohun ọdẹ, èmi yóò sì kó ìkógun, èmi yóò sì yí ọwọ́ mi padà sí ibi ìwólulẹ̀ ti a ti tún kọ́, àwọn ènìyàn tí a kójọpọ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè, tí ó ní ọrọ̀ nínú ẹran ọ̀sìn àti ẹrú, tí ó ń gbé ní àárín gbùngbùn ilẹ̀ náà.”
Nĩngũtaha, na ndunyane, o na njũkĩrĩre matũũra marĩa maanangĩtwo na magacooka gũtũũrwo, na njũkĩrĩre andũ arĩa marĩ kuo arĩa monganĩtio kuuma ndũrĩrĩ-inĩ, andũ marĩ na ũtonga wa mahiũ, na wa indo, nao matũũrĩte gatagatĩ ka bũrũri ũcio.”
13 Ṣeba, Dedani àti àwọn oníṣòwò Tarṣiṣi àti gbogbo àwọn ọmọ kìnnìún wọn, yóò sọ fún un yín pé, “Ṣé ẹ̀yin wá fún ìkógun? Ṣé ẹ̀yin ti kó àwọn ogun yín jọ pọ̀ fún ìkógun, láti kó fàdákà àti wúrà lọ, láti kó ẹran ọ̀sìn àti ẹrú àti láti gba ọ̀pọ̀ ìkógun?”’”
Andũ a Sheba, na a Dedani, na onjorithia a Tarishishi na matũũra mothe makuo magaakũũria atĩrĩ, “Ũũkĩte gũtaha indo? Ũnganĩtie kĩrĩndĩ gĩaku mũũke mũtunyane indo, na mũkuue betha na thahabu, na mũkuue mahiũ na indo, o na mũtahe indo nyingĩ mũno?”’
14 “Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì sọ fún Gogu: ‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Ní ọjọ́ náà, nígbà tí àwọn ènìyàn mi Israẹli ń gbé ní àìléwu, ìwọ kì yóò ha ṣe àkíyèsí rẹ̀?
“Nĩ ũndũ ũcio, mũrũ wa mũndũ, ratha ũhoro wĩre Gogu atĩrĩ: ‘Mwathani Jehova ekuuga ũũ: Ihinda rĩu, rĩrĩa andũ akwa Isiraeli magaakorwo maikarĩte marĩ na thayũ-rĩ, githĩ o nawe ndũkarĩmenya?
15 Ìwọ yóò wá láti ààyè rẹ ní jìnnàjìnnà àríwá, ìwọ àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè pẹ̀lú rẹ, gbogbo wọn yóò sì gun ẹṣin ẹgbẹ́ ńlá, jagunjagun alágbára.
Nĩũkoima gwaku kũndũ kũraya, o kũu mwena wa gathigathini, wee mũrĩ hamwe na ndũrĩrĩ nyingĩ, othe mahaicĩte mbarathi, marĩ kĩrĩndĩ kĩingĩ, mbũtũ ya ita ĩrĩ hinya.
16 Ìwọ yóò tẹ̀síwájú ní ìlòdì sí àwọn Israẹli ènìyàn mi gẹ́gẹ́ bí ìkùùkuu tí ó bo ilẹ̀. Ni àwọn ọjọ́ tí ń bọ̀, ìwọ Gogu, èmi yóò mú ọ wá ní ìlòdì sí ilẹ̀ mi, kí àwọn orílẹ̀-èdè lè mọ̀ mi nígbà tí mo bá fi ara hàn ni mímọ́ láti ọ̀dọ̀ rẹ ní ojú wọn.
Nĩũgathiĩ na mbere na gũũkĩrĩra andũ akwa a Isiraeli ũtariĩ ta itu rĩhumbĩrĩte bũrũri. Matukũ-inĩ marĩa magooka, wee Gogu-rĩ, nĩngagũtwara ũgookĩrĩre bũrũri wakwa, nĩguo ndũrĩrĩ ikaamenya rĩrĩa ngeyonania kũhĩtũkĩra harĩwe atĩ ndĩ mũtheru maitho-inĩ mao.
17 “‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Ìwọ ha kọ́ ni mo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ ní ìgbà ìṣáájú láti ẹnu àwọn wòlíì ìránṣẹ́ mi ti Israẹli? Ní ìgbà náà wọ́n sọtẹ́lẹ̀ fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún pé èmi yóò mú ọ lòdì sí wọn.
“‘Mwathani Jehova ekuuga ũũ: Githĩ wee tiwe ndaaririe ũhoro waku matukũ-inĩ ma mbere, ngĩaria na anabii a Isiraeli, o acio ndungata ciakwa? Ihinda-inĩ rĩu nĩmarathire ũhoro mĩaka mĩingĩ, makiuga atĩ nĩngagũtwara ũkamookĩrĩre.
18 Èyí ni ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ náà, nígbà tí Gogu bá kọlu ilẹ̀ Israẹli, gbígbóná ìbínú mi yóò ru sókè, ni Olúwa Olódùmarè wí.
Ũũ nĩguo gũkaahaana ihinda-inĩ rĩu: Rĩrĩa Gogu agaatharĩkĩra bũrũri wa Isiraeli, marakara makwa mahiũ nĩmakarahũrwo, ũguo nĩguo Mwathani Jehova ekuuga.
19 Ní ìtara mi àti ní gbígbóná ìbínú mi, mo tẹnumọ́ ọn pé; ní àsìkò náà ilẹ̀ mímì tí ó lágbára ní ilẹ̀ Israẹli yóò ṣẹlẹ̀.
Nguuga ndĩ na kĩyo kĩnene na mangʼũrĩ mahiũ ta mwaki atĩ ihinda rĩu nĩgũkagĩa gĩthingithia kĩnene kũu bũrũri-inĩ wa Isiraeli.
20 Ẹja inú Òkun, àwọn ẹyẹ òfúrufú, àwọn ẹranko igbó, àti gbogbo ẹ̀dá tí ó ń rìn lórí ilẹ̀ yóò wárìrì fún ìfarahàn mi. A yóò yí òkè gíga po, àwọn bèbè òkúta ni àwa yóò fọ́ sí wẹ́wẹ́, gbogbo ògiri ni yóò wó palẹ̀.
Thamaki cia iria-inĩ, na nyoni cia rĩera-inĩ, na nyamũ cia gĩthaka, na kanyamũ o gothe karĩa gathiiagĩra thĩ, o na andũ othe arĩa marĩ gũkũ thĩ nĩmakainaina maanyona. Irĩma nĩikangʼaũranio, na hurũrũka nĩikaragana, o na rũthingo o ruothe nĩrũkamomoka.
21 Èmi yóò fa idà yọ ni ìlòdì sí Gogu ní orí gbogbo àwọn òkè gíga mi ni Olúwa Olódùmarè wí. Idà gbogbo ènìyàn yóò lòdì sí arákùnrin rẹ̀.
Nĩngarehithia rũhiũ rwa njora rũũkĩrĩre Gogu kũu irĩma-inĩ ciakwa ciothe, ũguo nĩguo Mwathani Jehova ekuuga. Naruo rũhiũ rwa njora rwa o mũndũ nĩrũgookĩrĩra mũrũ wa ithe.
22 Èmi yóò gbé ìdájọ́ mi jáde lórí rẹ̀ pẹ̀lú ìyọnu àti ìtàjẹ̀ sílẹ̀, Èmi yóò dá àgbàrá òjò, òkúta yìnyín àti imí-ọjọ́ tí ń jó lé e lórí àti lórí ọ̀wọ́ ogun àti lórí ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè pẹ̀lú rẹ̀.
Nĩngatuĩra Gogu ciira, ndĩmũrehere mũthiro na ũiti wa thakame; nĩngoiria mbura nene mũno, ndĩmuurĩrie we mwene na thigari ciake, o na ndũrĩrĩ icio nyingĩ irĩ hamwe nake, ndĩmoirĩrie mbura ya mbembe na ũbiriti.
23 Nítorí náà, Èmi yóò fi títóbi mi àti ìjẹ́-mímọ́ mi hàn, Èmi yóò sì fi ara mi hàn ní ojú ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’
Ũguo nĩguo ngoonania ũnene o na ũtheru wakwa, na ndũme menyeke maitho-inĩ ma ndũrĩrĩ nyingĩ. Hĩndĩ ĩyo nĩmakamenya atĩ niĩ nĩ niĩ Jehova.’

< Ezekiel 38 >