< Ezekiel 36 >

1 “Ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ sí àwọn òkè gíga Israẹli kí o sì wí pé, ‘Ẹ̀yin òkè gíga Israẹli gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
O ana’ondatio, Itokio ami’ty hoe o vohi’ Israeleo: O ry vohi’ Israeleo, janjiño ty tsara’ Iehovà.
2 Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Àwọn ọ̀tá sọ nípa yín pé, “Háà! Àwọn ibi gíga ìgbàanì ti di ohun ìní wa.”’
Hoe ty nafè’ Iehovà Talè: Kanao nanao ty hoe ty ama’o i rafelahiy: Hede! fa amantika o haboañe haehaeo;
3 Nítorí náà, sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì wí pé, ‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Nítorí pé wọn sọ ọ di ahoro, tí wọn sì ń dọdẹ rẹ ní gbogbo ọ̀nà kí ìwọ kí ó lè di ìní fún àwọn orílẹ̀-èdè tí ó kù, àti ohun ti àwọn ènìyàn ń sọ ọ̀rọ̀ ìríra àti ìdíbàjẹ́ sí,
Le itokio ami’ty hoe: Hoe ty nafè’ Iehovà Talè: Amy t’ie nampangoakoahe’ iereo naho nagedra’ iereo añ’ ila’o iaby soa te ho fanaña’ o kilakila’ ndatio, naho fa rinambem-pivimbim-pitolom-bolañe vaho nifosae’ ondatio;
4 nítorí náà, ẹ̀yin òkè gíga Israẹli gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè, èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí fún àwọn òkè gíga àti àwọn òkè kéékèèké, fún àfonífojì ńlá àti àfonífojì kéékèèké, fún àwọn ibi ìsọdahoro ìparun àti fún àwọn ìlú tí a ti kọ̀sílẹ̀ tí a ti kó tí àwọn orílẹ̀-èdè tí ó kù ní àyíká sì fi ṣe ẹlẹ́yà,
ie amy zao, ry vohi’ Israele, janjiño ty tsara’ Iehovà Talè: Hoe t’Iehovà Talè amo vohitseo naho amo haboañeo, amo sakao, amo vavataneo, amo mangoakoakeo naho amo tane babangoañeo vaho amo rova naforintseñeo, ie fitsindroha’ o sehangan-kilakila’ ondaty mañohok’ azeo,
5 èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Ní ìgbóná ọkàn ní mo sọ̀rọ̀ sí àwọn kèfèrí yòókù, àti sí Edomu, nítorí pẹ̀lú ìbínú àti ìjowú ní ọkàn wọn ni wọ́n sọ ilé mi di ohun ìní wọn, kí wọn kí o lè kó pápá oko tútù rẹ̀.’
aa le inao ty nafè’ Iehovà Talè: Toe nivolañeko ami’ty afom-piforoforoam-pamarahiako o kilakila’ondaty ila’eo naho i Edome iaby, o nitavañe i taney ho aze an-kafalean-troke iabio, ami’ty firengevoham-pañiria’e, hanifike aze añe ho tsindrokeo.
6 Nítorí náà, sọtẹ́lẹ̀ nípa ilẹ̀ Israẹli náà kí o sì sọ sí àwọn òkè gíga náà àti àwọn òkè kéékèèké, sí àwọn àfonífojì ńlá àti sí àwọn àfonífojì kéékèèké, ‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi sọ̀rọ̀ nínú ìrunú owú mi nítorí pé ìwọ ti jìyà ìfiṣẹ̀sín àwọn orílẹ̀-èdè.
Aa le mitokia mb’an-tane’ Israele naho misaontsia amo vohitseo naho amo haboañeo naho amo sakao vaho amo vavataneo, ty hoe: Inao ty nafè’ Iehovà Talè: Ingo te nivolañe am-parahy naho foroforo iraho ty amy hasalarañe nifeaha’o vave,
7 Nítorí náà, èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi ṣe ìbúra nípa nína ọwọ́ mi sókè pé; àwọn orílẹ̀-èdè àyíká rẹ náà yóò jìyà ìfiṣẹ̀sín.
aa le hoe ty nafè’ Iehovà Talè: Fa nañonjon-tsirañe Raho, toe hivave ty hasalara’e o kilakila’ndaty mañohok’ anahareoo.
8 “‘Ṣùgbọ́n ìwọ, òkè gíga Israẹli, yóò mú ẹ̀ka àti èso fún àwọn ènìyàn mi Israẹli, nítorí wọn yóò wá sílé ní àìpẹ́ yìí.
Inahareo ka, ry vohi’ Israeleo, habarabijo’ areo o tsampa’o naho o voka’eo le mamokara ho am’ondatiko Israeleo, ie antitotse te hitotsak’eo.
9 Èmi ń ṣe àníyàn fún ọ, èmi yóò sì fi rere wọ̀ ọ́; àwa yóò tu ọ́, àwa yóò sì gbìn ọ́,
Ingo fa Mpiama’ areo iraho, naho hitolihako le ho trabaheñe vaho tongiseñe,
10 èmi yóò sì sọ iye àwọn ènìyàn di púpọ̀ nínú rẹ àti gbogbo ilé Israẹli. Àwọn ìlú yóò di ibùgbé, a yóò sì tún àwọn ibi ìparun kọ́.
le hampitomboeko ama’ areo t’ondaty, i hene anjomba’ Israeley, eka ie iaby; vaho songa himoneñañe o rovao, le hamboareñe o haran-koakeo.
11 Èmi yóò sọ iye ènìyàn àti ẹran dì púpọ̀ nínú yín, wọn yóò sì so èso, wọn yóò sì di púpọ̀ yanturu. Èmi yóò mú kí àwọn ènìyàn máa gbé nínú rẹ bí ti àtẹ̀yìnwá, èmi yóò sì mú kí o ṣe rere ju ìgbà àtijọ́ lọ. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ pé èmi ni Olúwa.
Hampitomboeko ama’areo ty ondaty naho hare, hiraorao naho hangetseketseke; naho hampimoneñako manahake i tama’areo haehaey, naho hanoeko soa te am-pifotora’ areo, vaho ho fohi’ areo te Izaho Iehovà.
12 Èmi yóò mú kí àwọn ènìyàn, àní àwọn ènìyàn Israẹli, rìn lórí rẹ̀. Wọn yóò gbà ọ́, ìwọ yóò sì di ogún ìní wọn; ìwọ kì yóò sì gba àwọn ọmọ wọn lọ́wọ́ wọn mọ́.
Hampañaveloeko ama’ areo t’indaty, toe ondatiko Israeleo, le ho fanaña’ iareo, ho lova’ iareo vaho tsy hampirovete’o anake ka henane zay.
13 “‘Èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Nítorí pé àwọn ènìyàn sọ fún ọ pé, “Ìwọ pa àwọn ènìyàn run, ìwọ sì gba àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè lọ́wọ́ wọn,”
Inao ty nafè’ Iehovà Talè: Amy t’ie manao ty hoe; Mampibotseke ondaty irehe vaho nampihontofe’o o fifehea’oo,
14 nítorí náà ìwọ kì yóò pa àwọn ènìyàn run tàbí mú kì orílẹ̀-èdè di aláìlọ́mọ mọ́, ni Olúwa Olódùmarè wí.
aa le tsy hampibotseke ondaty ka irehe, vaho tsy hampandalà’o ana-dahy ka o fifehea’oo, hoe t’Iehovà Talè.
15 Èmi kì yóò mú ki ó gbọ́ ọ̀rọ̀ ẹ̀gàn láti ọ̀dọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè mọ́, ìwọ kì yóò jìyà ọ̀rọ̀ ìfiṣẹ̀sín láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn tàbí mú kí orílẹ̀-èdè rẹ ṣubú, ni Olúwa Olódùmarè wí.’”
Mbore tsy hampijineko azo ka ty hasalara’ o kilakila’ ndatio naho tsy ho vavè’o ty inje’ ondatio vaho tsy hampitsikapie’o ka o fifehea’oo, hoe t’Iehovà Talè.
16 Síwájú sí i ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Niheo amako indraike ty tsara’ Iehovà manao ty hoe,
17 “Ọmọ ènìyàn, nígbà tí àwọn ènìyàn Israẹli ń gbé ní ilẹ̀ wọn, wọ́n bà á jẹ́ nípa ìwà àti ìṣe wọn. Ìwà wọn dàbí nǹkan àkókò àwọn obìnrin ni ojú mi.
O ana’ ondatio, Fa nileore’ o sata’eo naho ty fitoloña’ iareo i anjomba’ Israele mimoneñe an-tane’ iareoy; niatrek’ ahy hoe fandeoran’ ampela am-piambolañe ty sata’ iareo.
18 Nítorí náà mo tú ìbínú mi jáde sórí wọn nítorí wọn ti ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ àti nítorí pé wọ́n ti fi ère wọn ba a jẹ́.
Aa le nadoako am’ iereo ty fifomboko ty amo lio nampiorihe’ iereo an-taneo, naho o samposampo nanivà’ iareo azeo;
19 Mo tú wọn ká sí àárín àwọn orílẹ̀-èdè, a sì fọ́n wọn ká sí àwọn ìlú; mo ṣe ìdájọ́ wọn gẹ́gẹ́ bí ìwà àti ìṣe wọn.
le nabaratsako amo kilakila’ ondatio vaho niparaitak’ amo fifeheañeo; o sata’iareoo naho o fitoloña’iareoo ty nizakako iareo.
20 Gbogbo ibi tí wọ́n lọ ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè ni wọn ti sọ orúkọ mímọ́ mi di aláìmọ́, nítorí tí a sọ nípa wọn pé, ‘Ìwọ̀nyí ni àwọn ènìyàn Olúwa, síbẹ̀ wọn ní láti fi ilẹ̀ náà sílẹ̀.’
Aa ie nimoak’ amo kilakila’ ndatio, le tiniva’ iareo i añarako masiñey; ie nanoa’ ondatio ty hoe, Ondati’ Iehovà iretoañe, ie fa nienga i tane’ey.
21 Orúkọ mímọ́ mi jẹ́ mi lógún, èyí tí ilé Israẹli sọ di aláìmọ́ ni àárín àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n ti lọ.
Aa le nitretrezeko i añarako masiñe nitivae’ i anjomba’ Israeley amo kilakila’ndaty nañaveloa’eoy.
22 “Nítorí náà, sọ fún ilé Israẹli, ‘Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Kì í ṣe nítorí rẹ, ìwọ ilé Israẹli, ni èmi yóò ṣe ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí, ṣùgbọ́n nítorí orúkọ mímọ́ mi, èyí ti ìwọ ti sọ di aláìmọ́ ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè tí ìwọ ti lọ.
Aa le saontsio ty hoe i anjomba’ Israeley, Inao ty nafè’ Iehovà Talè: Tsy ty ama’ areo ty anoako zao, ry anjomba’ Israeleo, fa ty amy añarako masiñe tiniva’ areo añivo’ o kilakila’ndaty nañaveloa’ areoo.
23 Èmi yóò fi jíjẹ́ mímọ́ orúkọ ńlá mi, èyí tí a ti sọ di aláìmọ́ hàn ni àárín àwọn orílẹ̀-èdè, orúkọ tí ìwọ ti sọ di aláìmọ́ ni àárín wọn. Nígbà náà àwọn orílẹ̀-èdè yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa, ni Olúwa Olódùmarè wí, nígbà tí mo bá fi ara mi hàn ni mímọ́ nípasẹ̀ yín ni iwájú wọn.
Le ho masiñeko i añarako ra’elahiy, i tiniva’ areo añivo’ o kilakila’ ndatioy, i vineta’ areo anteñateña’ iereoy; vaho ho fohi’ o kilakila’ndatio te Izaho Iehovà, hoe t’Iehovà Talè, naho avahe’ areo añatrefam-pihaino’ iareo eo iraho.
24 “‘Nítorí èmi yóò mú yín jáde kúrò ni àwọn orílẹ̀-èdè náà; Èmi yóò ṣà yín jọ kúrò ní gbogbo àwọn ìlú náà; Èmi yóò sì mú yín padà sí ilẹ̀ ẹ̀yin tìkára yín.
Le ho rambeseko amo kilakila’ndatio nahareo, naho hatontoko boak’ amy ze hene fifelehañe, vaho ho enteko mb’an-tane’ areo mb’eo.
25 Èmi yóò wọ́n omi tó mọ́ sí yín lára ẹ̀yin yóò sì mọ́; Èmi yóò sì fọ̀ yín mọ́ kúrò nínú gbogbo ìwà èérí yin gbogbo àti kúrò nínú gbogbo òrìṣà yin.
Le ho fitsezako rano malio, naho halio amo haleora’ areo iabio, vaho ho lioveko amo samposampo’ areoo.
26 Èmi yóò fún yín ni ọkàn tuntun, èmi yóò sì fi ẹ̀mí tuntun sínú yín; Èmi yóò sì mú ọkàn òkúta kúrò nínú yín, èmi yóò sì fi ọkàn ẹran fún yín.
Ho tolo­rako arofo vao nahareo, naho hampizilihako troke vao; naho hafahako am-pañova’ areo ao i troke mamàtoy, vaho ho tolorako arofo nofotse.
27 Èmi yóò fi ẹ̀mí mi sínú yín, èmi yóò sì mú ki ẹ tẹ̀lé àṣẹ mi, kí ẹ sì fiyèsí àti pa òfin mi mọ́.
Aa le hajoko ama’ areo t’i Troko naho hampañoriheko o lilikoo soa te hambena’ areo o fañèkoo, hitoloña’ areo.
28 Ẹ̀yin yóò sì máa gbé ilẹ̀ náà tí mo ti fi fún àwọn baba ńlá yín; ẹ̀yin yóò sì jẹ́ ènìyàn mi èmi yóò sì jẹ́ Ọlọ́run yín.
Le himoneña’ areo i tane natoloko aman-droae’ areoy naho ho ondatiko nahareo vaho ho Andrianañahare’ areo iraho.
29 Èmi yóò sì gbà yín kúrò nínú gbogbo ìwà àìmọ́ yín. Èmi yóò pèsè ọkà, èmi yóò sì mú kí ó pọ̀ yanturu, èmi kì yóò sì mú ìyàn wá sí orí yín.
Ho votsorako amo haleora’ areoo; naho ho tokaveko i ampembay hamokara’e vaho tsy halamako ama’ areo ty hasalikoañe.
30 Èmi yóò sọ èso àwọn igi yín àti ohun ọ̀gbìn oko yín di púpọ̀, nítorí kí ẹ̀yin kí ó má ṣe jìyà ìdójútì mọ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè náà nítorí ìyàn.
Hampiregoregoeko ka o voan-kataeo, naho ty havokara’ o tetekeo, tsy hinjè’ ty kerè ka nahareo añivo’ o kilakila’ ndatio.
31 Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò rántí àwọn ọ̀nà búburú àti àwọn ìwà ìkà yín, ẹ̀yin yóò sì kórìíra ara yín fún ẹ̀ṣẹ̀ yín, ìwà tí kò bójúmu.
Ho tiahi’ areo amy zao o sata-rati’ areoo naho o fitoloñañe tsy vokatseo, vaho ho heje’ areo vintañe am-pahaoniña’ areo eo ty fiai’ areo ty amo hakeo naho haloloa’ areoo.
32 Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀ pé ń kò ṣe nǹkan wọ̀nyí nítorí yín, ni Olúwa Olódùmarè wí. Jẹ kí ojú kí ó tì yín, kí ẹ sì gba ẹ̀tẹ́ nítorí ìwà yín ẹ̀yin ilé Israẹli!
Tsy ty ama’ areo ty anoako izay, hoe t’Iehovà Talè, maharendreha; mimeñara naho misalara amo sata’ areoo, ry anjomba’ Israeleo.
33 “‘Èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Ní ọjọ́ tí mo wẹ̀ yín kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ yín gbogbo, èmi yóò ṣe àtúnṣe àwọn ìlú yín, wọn yóò sì ṣe àtúnkọ́ ìwólulẹ̀.
Hoe ty nafè’ Iehovà Talè: amy andro nañaliovako anahareo amo fonga tahi’ areooy, fa hampimoneñako o rovao, vaho hamboareñe o tane hoakeo.
34 Ilẹ̀ ahoro náà ní àwa yóò tún kọ́ ti kì yóò wà ní ahoro lójú àwọn tí ó ń gba ibẹ̀ kọjá mọ́.
Ho rokafeñe i tane bangiñey, ie napoke ho ratraratra amo mpiary azeo;
35 Wọn yóò sọ wí pé, “Ilẹ̀ yìí tí ó ti wà ní ahoro tẹ́lẹ̀ ti dàbí ọgbà Edeni; àwọn ìlú tí ó wà ní wíwó lulẹ̀, ahoro tí a ti parun, ni àwa yóò mọdi sí tí yóò sì wà fún gbígbé ni ìsinsin yìí.”
ie nanoeñe ty hoe: Nihambañe an-tane Edene ty tane liolio toy taolo; vaho ni-fatratse i rova mangoakoake naho bangiñe reroañe.
36 Nígbà náà àwọn orílẹ̀-èdè tí ó wà ní àyíká yín tí ó kù yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti tún àwọn ohun tí ó bàjẹ́ kọ́, mo sì ti tún ohun tí ó di ìṣòfo gbìn. Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀, èmi yóò sì ṣe e?’
Le ho fohi’ o kilakila’ ndaty nengañe mañohok’ anahareoo te Izaho Iehovà ty namboatse o niantoo, vaho nambole i niliolioy; Izaho Iehovà ty nitaroñe, Izaho ty hitoloñe.
37 “Èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè sọ: Lẹ́ẹ̀kan sí i èmi yóò yí sí ilé Israẹli, èmi yóò sì ṣe èyí fún wọn. Èmi yóò mú kí àwọn ènìyàn yín pọ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ bí àgùntàn,
Hoe ty nafè’ Iehovà Talè: Izay ty hitsoeha’ i anjomba’ Israeley t’ie hitoloñe, le ho maroeko hoe lia-raike.
38 kí ó pọ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ bí ọ̀wọ́ ẹran fún ìrúbọ ní Jerusalẹmu ní àsìkò àjọ̀dún tí a yàn. Ìlú ti a parun yóò wá kún fún agbo àwọn ènìyàn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.”
Manahake o añondry miavakeo, o añondry an-tsabadidam-pitalahoa’ Ierosalaimeo, ty hanitsifañe lia-rai’ ondaty o rova hoakeo; vaho ho fohi’ iareo te Izaho Iehovà.

< Ezekiel 36 >