< Ezekiel 35 >
Кувынтул Домнулуй мь-а ворбит астфел:
2 “Ọmọ ènìyàn kọjú sí òkè Seiri; sọtẹ́lẹ̀ sí i,
„Фиул омулуй, ынтоарче-те ку фаца спре мунтеле Сеир, пророчеште ымпотрива луй
3 kí o sì sọ wí pé, ‘Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmí lòdì sí ọ, òkè Seiri, Èmi yóò sì na ọwọ́ mi síta ní ìlòdì sí ọ, èmi yóò sì mú kí ó di ahoro.
ши зи: ‘Аша ворбеште Домнул Думнезеу: «Ятэ, ам неказ пе тине, мунтеле Сеирулуй! Ымь ынтинд мына ымпотрива та ши те префак ынтр-о пустиетате ши ынтр-ун пустиу!
4 Èmi yóò pa àwọn ìlú rẹ run, ìwọ yóò sì di ahoro. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
Ыць вой префаче четэциле ын дэрымэтурь, вей ажунӂе о пустиетате, ка сэ штий кэ Еу сунт Домнул!
5 “‘Nítorí ìwọ dá ààbò bo ọ̀tẹ̀ àtayébáyé, tí ìwọ sì fi Israẹli lé idà lọ́wọ́, ní àsìkò ìdààmú wọn, ní àsìkò tí ìjìyà wọn dé góńgó,
Пентру кэ авяй о урэ вешникэ ши ай доборыт ку сабия пе копиий луй Исраел ын зиуа неказулуй лор, ын время кынд нелеӂюиря ера ла кулме,
6 nítorí náà bi mo ti wà láààyè, ni Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò fi ọ kalẹ̀ fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ. Níwọ́n ìgbà tí ìwọ kò ti kórìíra ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ.
де ачея, пе вяца Мя», зиче Домнул Думнезеу, «кэ те вой фаче сынӂе ши те ва урмэри сынӂеле; фииндкэ н-ай урыт сынӂеле, де ачея сынӂеле те ва урмэри.
7 Èmi yóò mú kí òkè Seiri di ahoro; ọ̀fọ̀ gbogbo àwọn tí ó ń lọ tí ó ń bọ̀ ní èmi yóò gé kúrò lára rẹ.
Вой префаче мунтеле Сеир ынтр-о пустиетате ши ынтр-ун пустиу ши вой нимичи ку десэвыршире дин ел ши пе чей че се дук, ши пе чей че се ынторк.
8 Èmi yóò fi àwọn tí a pa kún orí òkè rẹ, àwọn tí a fi idà pa yóò ṣubú ní orí òkè rẹ, àti ní àárín àwọn òkè rẹ.
Ый вой умпле мунций ку морць ши чей учишь де сабие вор кэдя пе дялуриле тале, ын вэиле тале ши ын тоате пухоаеле тале.
9 Èmi yóò mú kí ó di ahoro títí láé, kò ní sí olùgbé ní ìlú rẹ. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
Те вой префаче ын ниште пустиетэць вешниче, четэциле ну-ць вор май фи локуите ши вець шти кэ Еу сунт Домнул.
10 “‘Nítorí tí ìwọ sọ pé, “Àwọn orílẹ̀-èdè àti ilẹ̀ méjì wọ̀nyí yóò jẹ́ tiwa, àwa yóò sì gbà wọ́n ní ìní,” bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, Èmi Olúwa wà níbẹ̀,
Пентру кэ ай зис: ‹Ачесте доуэ нямурь ши ачесте доуэ цэрь вор фи але меле ши ле вом луа ын стэпынире›, мэкар кэ Домнул ера аколо,
11 nítorí náà níwọ̀n ìgbà tí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò hùwà sí ọ ní ìbámu pẹ̀lú ìbínú àti owú tí o fihàn nínú ìkórìíra rẹ sí wọn, èmi yóò fi ara mi hàn ní àárín wọn, nígbà tí mo bá ṣe ìdájọ́ rẹ.
де ачея, пе вяца Мя», зиче Домнул Думнезеу, «кэ Мэ вой пурта ку тине дупэ мыния ши урӂия пе каре ле-ай арэтат ши ту, ын ура та, ымпотрива лор ши Мэ вой фаче куноскут ын мижлокул лор, кынд те вой жудека.
12 Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti gbọ́ gbogbo ohun ẹ̀gàn tí ìwọ ti sọ lòdì sí àwọn òkè Israẹli náà. Ìwọ wí pé, “A sọ wọ́n di ahoro, a sì fi wọ́n fún wa láti run.”
Вей шти ынсэ кэ Еу, Домнул, ам аузит тоате батжокуриле пе каре ле-ай ростит ымпотрива мунцилор луй Исраел кынд ай зис: ‹Сунт пустииць ши не сунт даць ка прадэ!›
13 Ìwọ lérí sí mi, ó sì sọ̀rọ̀ lòdì sí mí láìsí ìdádúró, èmi sì gbọ́ ọ.
В-аць фэлит астфел ымпотрива Мя прин ворбириле воастре ши в-аць ынмулцит кувинтеле ымпотрива Мя: ам аузит!»
14 Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí gbogbo ayé bá ń yọ̀, èmi yóò mú kí ó di ahoro.
Аша ворбеште Домнул Думнезеу: «Кынд тоатэ цара се ва букура, пе тине те вой префаче ынтр-о пустиетате!
15 Nítorí pé ìwọ ń yọ̀ nígbà tí ìní ilé Israẹli di ahoro, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni èmi yóò ṣe hùwà sí ọ. Ìwọ yóò di ahoro, ìwọ òkè Seiri, ìwọ àti gbogbo ará Edomu. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
Дин причина букурией пе каре ай симцит-о кэ моштениря касей луй Исраел ера пустиитэ, ыць вой фаче ши цие ла фел. Вей ажунӂе о пустиетате, мунте ал Сеирулуй, ту ши тот Едомул, ши се ва шти кэ Еу сунт Домнул.»’