< Ezekiel 35 >
Og Herrens ord kom til mig, og det lød så:
2 “Ọmọ ènìyàn kọjú sí òkè Seiri; sọtẹ́lẹ̀ sí i,
Menneskesønn! Vend ditt åsyn mot Se'ir-fjellet og spå mot det!
3 kí o sì sọ wí pé, ‘Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmí lòdì sí ọ, òkè Seiri, Èmi yóò sì na ọwọ́ mi síta ní ìlòdì sí ọ, èmi yóò sì mú kí ó di ahoro.
Og du skal si til det: Så sier Herren, Israels Gud: Se, jeg kommer over dig, du Se'ir-fjell, og jeg vil rekke ut min hånd mot dig og gjøre dig til en ørken, en ødemark.
4 Èmi yóò pa àwọn ìlú rẹ run, ìwọ yóò sì di ahoro. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
Dine byer vil jeg gjøre til grushoper, og du selv skal bli til en ørken, og du skal kjenne at jeg er Herren.
5 “‘Nítorí ìwọ dá ààbò bo ọ̀tẹ̀ àtayébáyé, tí ìwọ sì fi Israẹli lé idà lọ́wọ́, ní àsìkò ìdààmú wọn, ní àsìkò tí ìjìyà wọn dé góńgó,
Fordi du bærer på et evig fiendskap og overgav Israels barn i sverdets vold - i deres ulykkes tid, da den misgjerning skjedde som førte til undergang,
6 nítorí náà bi mo ti wà láààyè, ni Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò fi ọ kalẹ̀ fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ. Níwọ́n ìgbà tí ìwọ kò ti kórìíra ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ.
derfor, så sant jeg lever, sier Herren, Israels Gud, vil jeg gjøre dig til blod, og blod skal forfølge dig; fordi du ikke har hatet blod, skal blod forfølge dig.
7 Èmi yóò mú kí òkè Seiri di ahoro; ọ̀fọ̀ gbogbo àwọn tí ó ń lọ tí ó ń bọ̀ ní èmi yóò gé kúrò lára rẹ.
Jeg vil gjøre Se'ir-fjellet til en ørken, en ødemark, og utrydde av det både den som drar frem, og den som drar tilbake.
8 Èmi yóò fi àwọn tí a pa kún orí òkè rẹ, àwọn tí a fi idà pa yóò ṣubú ní orí òkè rẹ, àti ní àárín àwọn òkè rẹ.
Jeg vil fylle dets fjell med dets drepte menn; på dine hauger og i dine daler og i alle dine bekker skal det falle menn som er drept ved sverd.
9 Èmi yóò mú kí ó di ahoro títí láé, kò ní sí olùgbé ní ìlú rẹ. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
Til evige ørkener vil jeg gjøre dig, og dine byer skal ikke reise sig igjen, og I skal kjenne at jeg er Herren.
10 “‘Nítorí tí ìwọ sọ pé, “Àwọn orílẹ̀-èdè àti ilẹ̀ méjì wọ̀nyí yóò jẹ́ tiwa, àwa yóò sì gbà wọ́n ní ìní,” bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, Èmi Olúwa wà níbẹ̀,
Fordi du sa: De to folk og de to land skal bli mine, og vi vil ta dem i eie, enda Herren har vært der,
11 nítorí náà níwọ̀n ìgbà tí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò hùwà sí ọ ní ìbámu pẹ̀lú ìbínú àti owú tí o fihàn nínú ìkórìíra rẹ sí wọn, èmi yóò fi ara mi hàn ní àárín wọn, nígbà tí mo bá ṣe ìdájọ́ rẹ.
derfor vil jeg, så sant jeg lever, sier Herren, Israels Gud, gjøre med dig efter den vrede og avind som du har lagt for dagen i ditt hat mot dem, og jeg skal bli kjent blandt dem når jeg dømmer dig.
12 Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti gbọ́ gbogbo ohun ẹ̀gàn tí ìwọ ti sọ lòdì sí àwọn òkè Israẹli náà. Ìwọ wí pé, “A sọ wọ́n di ahoro, a sì fi wọ́n fún wa láti run.”
Og du skal kjenne at jeg, Herren, har hørt alle de spottord som du har talt mot Israels fjell, da du sa: De er ødelagt, oss er de gitt til føde.
13 Ìwọ lérí sí mi, ó sì sọ̀rọ̀ lòdì sí mí láìsí ìdádúró, èmi sì gbọ́ ọ.
Og I talte overmodig mot mig med eders munn og brukte mange ord mot mig; jeg har nok hørt det.
14 Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí gbogbo ayé bá ń yọ̀, èmi yóò mú kí ó di ahoro.
Så sier Herren, Israels Gud: Mens all jorden gleder sig, vil jeg legge dig øde.
15 Nítorí pé ìwọ ń yọ̀ nígbà tí ìní ilé Israẹli di ahoro, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni èmi yóò ṣe hùwà sí ọ. Ìwọ yóò di ahoro, ìwọ òkè Seiri, ìwọ àti gbogbo ará Edomu. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
Som du gledet dig fordi Israelættens arv blev ødelagt, således vil jeg gjøre mot dig; en ørken skal Se'ir-fjellet og hele, hele Edom bli, og de skal kjenne at jeg er Herren.