< Ezekiel 35 >
És lett hozzám az Örökkévaló igéje, mondván:
2 “Ọmọ ènìyàn kọjú sí òkè Seiri; sọtẹ́lẹ̀ sí i,
Ember fia, fordítsd arczodat Széir hegye felé és prófétálj róla.
3 kí o sì sọ wí pé, ‘Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmí lòdì sí ọ, òkè Seiri, Èmi yóò sì na ọwọ́ mi síta ní ìlòdì sí ọ, èmi yóò sì mú kí ó di ahoro.
És mondd neki: Így szól az Úr, az Örökkévaló: Íme én ellened fordulok, Széir hegye, kinyújtom reád kezemet s pusztulássá és pusztasággá teszlek.
4 Èmi yóò pa àwọn ìlú rẹ run, ìwọ yóò sì di ahoro. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
Városaidat rommá teszem és te pusztulássá leszel; és megtudod, hogy én vagyok az Örökkévaló.
5 “‘Nítorí ìwọ dá ààbò bo ọ̀tẹ̀ àtayébáyé, tí ìwọ sì fi Israẹli lé idà lọ́wọ́, ní àsìkò ìdààmú wọn, ní àsìkò tí ìjìyà wọn dé góńgó,
Mivel örök gyűlölséged volt és Izraél fiait oda vetetted a kard hatalmába, balsorsuk idején, a végbűn idején.
6 nítorí náà bi mo ti wà láààyè, ni Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò fi ọ kalẹ̀ fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ. Níwọ́n ìgbà tí ìwọ kò ti kórìíra ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ.
Azért ahogy élek, úgymond az Úr, az Örökkévaló, bizony vérré teszlek és vér üldözzön téged, ha te nem gyűlölted a vért, tehát vér üldözzön téged.
7 Èmi yóò mú kí òkè Seiri di ahoro; ọ̀fọ̀ gbogbo àwọn tí ó ń lọ tí ó ń bọ̀ ní èmi yóò gé kúrò lára rẹ.
És teszem Széir hegyét pusztasággá és pusztulássá, és kiirtok belőle járókelőt.
8 Èmi yóò fi àwọn tí a pa kún orí òkè rẹ, àwọn tí a fi idà pa yóò ṣubú ní orí òkè rẹ, àti ní àárín àwọn òkè rẹ.
És megtöltöm hegyeit megöltjeivel, halmaid, völgyeid és mind a medreid – kard megöltjei esnek el rajtuk.
9 Èmi yóò mú kí ó di ahoro títí láé, kò ní sí olùgbé ní ìlú rẹ. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
Örök pusztulássá teszlek, városaid nem állnak helyre; és megtudjátok, hogy én vagyok az Örökkévaló.
10 “‘Nítorí tí ìwọ sọ pé, “Àwọn orílẹ̀-èdè àti ilẹ̀ méjì wọ̀nyí yóò jẹ́ tiwa, àwa yóò sì gbà wọ́n ní ìní,” bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, Èmi Olúwa wà níbẹ̀,
Mivel azt mondtad: az a két nemzet és az a két ország az enyém lesz és elfoglaljuk, holott az Örökkévaló ott volt.
11 nítorí náà níwọ̀n ìgbà tí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò hùwà sí ọ ní ìbámu pẹ̀lú ìbínú àti owú tí o fihàn nínú ìkórìíra rẹ sí wọn, èmi yóò fi ara mi hàn ní àárín wọn, nígbà tí mo bá ṣe ìdájọ́ rẹ.
Azért, ahogy élek, úgymond az Úr, az Örökkévaló, cselekszem majd haragod és buzgalmad szerint, amellyel te cselekedtél gyűlöletedből ellenök; és megismertetem magamat köztük, midőn ítéllek tégedet.
12 Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti gbọ́ gbogbo ohun ẹ̀gàn tí ìwọ ti sọ lòdì sí àwọn òkè Israẹli náà. Ìwọ wí pé, “A sọ wọ́n di ahoro, a sì fi wọ́n fún wa láti run.”
És megtudod, hogy én az Örökkévaló hallottam mind a gyalázásaidat, a melyeket kimondottál Izraél hegyei ellen, mondván: elpusztultak, nekünk adattak eledelül.
13 Ìwọ lérí sí mi, ó sì sọ̀rọ̀ lòdì sí mí láìsí ìdádúró, èmi sì gbọ́ ọ.
És fennhéjáztatok ellenem szátokkal és szaporítjátok ellenem szavaitokat: én hallottam.
14 Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí gbogbo ayé bá ń yọ̀, èmi yóò mú kí ó di ahoro.
Így szól az Úr, az Örökkévaló: midőn majd örül az egész föld, pusztulást teszek veled.
15 Nítorí pé ìwọ ń yọ̀ nígbà tí ìní ilé Israẹli di ahoro, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni èmi yóò ṣe hùwà sí ọ. Ìwọ yóò di ahoro, ìwọ òkè Seiri, ìwọ àti gbogbo ará Edomu. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
A mint örültél Izraél házának örökségén, mivelhogy elpusztult, úgy cselekszem veled: pusztulássá lesz Széir hegye és Edóm egészen; és megtudják, hogy én vagyok az Örökkévaló.