< Ezekiel 35 >
Angraeng ih lok kai khaeah angzoh,
2 “Ọmọ ènìyàn kọjú sí òkè Seiri; sọtẹ́lẹ̀ sí i,
kami capa, Seir Mae bangah angqoi ah loe, anih misa haih lok to thui ah;
3 kí o sì sọ wí pé, ‘Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmí lòdì sí ọ, òkè Seiri, Èmi yóò sì na ọwọ́ mi síta ní ìlòdì sí ọ, èmi yóò sì mú kí ó di ahoro.
khenah, Seir mae, nang loe Angraeng Sithaw mah misa ah kang suek, nang tuk hanah ban ka phok moe, kang pongsak sut han.
4 Èmi yóò pa àwọn ìlú rẹ run, ìwọ yóò sì di ahoro. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
Na vangpuinawk to kam rosak moe, angqai krang ah kang suek han, to naah Kai loe Angraeng ni, tiah na panoek tih.
5 “‘Nítorí ìwọ dá ààbò bo ọ̀tẹ̀ àtayébáyé, tí ìwọ sì fi Israẹli lé idà lọ́wọ́, ní àsìkò ìdààmú wọn, ní àsìkò tí ìjìyà wọn dé góńgó,
Nang loe hnukmahaih na tawnh moe, Israel caanawk raihaih tongh o nathuem ih a sakpazae o haih pongah, boenghaih phak o naah nihcae to sumsen hoiah na hum o, tiah thuih, tiah thui paeh, tiah ang naa.
6 nítorí náà bi mo ti wà láààyè, ni Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò fi ọ kalẹ̀ fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ. Níwọ́n ìgbà tí ìwọ kò ti kórìíra ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ.
To pongah Kai ka hing baktih toengah, Angraeng Sithaw mah, athii kang palong han, to athii mah na patom tih; kami athii palonghaih to na hnuma ai pongah, athii mah na patom tih.
7 Èmi yóò mú kí òkè Seiri di ahoro; ọ̀fọ̀ gbogbo àwọn tí ó ń lọ tí ó ń bọ̀ ní èmi yóò gé kúrò lára rẹ.
To tiah Seir maesom to kam rosak moe, to ah caeh tathuk, caeh tahang kaminawk to ka boengsak han.
8 Èmi yóò fi àwọn tí a pa kún orí òkè rẹ, àwọn tí a fi idà pa yóò ṣubú ní orí òkè rẹ, àti ní àárín àwọn òkè rẹ.
Nangmah ih maenawk to kami qok hoiah ka koisak han; sumsen hoi hum ih kaminawk loe nangmah ih maesomnawk, longhawhnawk hoi vapuinawk thungah amtim o tih.
9 Èmi yóò mú kí ó di ahoro títí láé, kò ní sí olùgbé ní ìlú rẹ. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
Nang loe pong sut tih boeh, na vangpuinawk thungah kami om o mak ai boeh; to naah Kai loe Angraeng ni, tiah na panoek o tih, tiah thuih.
10 “‘Nítorí tí ìwọ sọ pé, “Àwọn orílẹ̀-èdè àti ilẹ̀ méjì wọ̀nyí yóò jẹ́ tiwa, àwa yóò sì gbà wọ́n ní ìní,” bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, Èmi Olúwa wà níbẹ̀,
To prae thungah Angraeng oh to mah, nangcae mah, Hae acaeng hnik, Israel hoi Judah, nihnik ih prae to ka lak moe, qawk ah ka toep o han boeh, tiah na thuih o:
11 nítorí náà níwọ̀n ìgbà tí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò hùwà sí ọ ní ìbámu pẹ̀lú ìbínú àti owú tí o fihàn nínú ìkórìíra rẹ sí wọn, èmi yóò fi ara mi hàn ní àárín wọn, nígbà tí mo bá ṣe ìdájọ́ rẹ.
Kai ka hing baktih toengah, Angraeng Sithaw mah, Kai ih kaminawk nuiah palungphuihaih hoi uthaih na tawnh o pongah, lok kang caek o han; lok kang caek o naah, nihcae khaeah kam tueng pae han.
12 Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti gbọ́ gbogbo ohun ẹ̀gàn tí ìwọ ti sọ lòdì sí àwọn òkè Israẹli náà. Ìwọ wí pé, “A sọ wọ́n di ahoro, a sì fi wọ́n fún wa láti run.”
Nangcae mah Israel maenawk loe pong sut boeh, a caak o hanah aicae han ang paek boeh, tiah kasae na thuih o haih loknawk to Kai Angraeng mah ka thaih boih boeh, tiah na panoek o tih, tiah thuih.
13 Ìwọ lérí sí mi, ó sì sọ̀rọ̀ lòdì sí mí láìsí ìdádúró, èmi sì gbọ́ ọ.
Pakha hoiah kai nam oek o thuih moe, kai misa ah nang suek o haih lok to angsum ai ah na thuih o, to loknawk doeh ka thaih boeh.
14 Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí gbogbo ayé bá ń yọ̀, èmi yóò mú kí ó di ahoro.
Angraeng Sithaw mah, Long pum anghoe naah, nang loe angqai krangah kang ohsak han.
15 Nítorí pé ìwọ ń yọ̀ nígbà tí ìní ilé Israẹli di ahoro, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni èmi yóò ṣe hùwà sí ọ. Ìwọ yóò di ahoro, ìwọ òkè Seiri, ìwọ àti gbogbo ará Edomu. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
Israel imthung takoh ih qawk to pong sut naah, nang hoe o baktih toengah, nangcae khaeah doeh ka sak han; Aw Seir mae, Edumea loe amro boih tih; to naah Kai loe Angraeng ni, tiah na panoek o tih, tiah thui paeh, tiah ang naa.