< Ezekiel 34 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ́ mi wá:
BOEIPA ol kai taengla koep ha pawk tih,
2 “Ọmọ ènìyàn, fi àsọtẹ́lẹ̀ tako Olùṣọ́-àgùntàn Israẹli; sọtẹ́lẹ̀ fún wọn pé: ‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Ègbé ni fún olùṣọ́-àgùntàn Israẹli tí ó ń tọ́jú ara wọn nìkan! Ṣé ó dára kí olùṣọ́-àgùntàn ṣaláì tọ́jú agbo ẹran?
“Hlang capa Israel aka dawn taengah tonghma pah. Tonghma lamtah amih aka dawn taengah thui pah. Ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. Anunae Israel aka dawn rhoek khaw amamih aka luem la om uh tih boiva aka luem te dawn uh pawt mico?
3 Ìwọ jẹ wàrà. O sì wọ aṣọ olówùú sí ara rẹ, o sì ń pa ẹran tí ó wù ọ́, ṣùgbọ́n ìwọ kò tọ́jú agbo ẹran.
A tha te na caak uh tih tumul te na bai uh. Na luem puei uh van pawt ah, boiva a toitup te na ngawn uh.
4 Ìwọ kò ì tí ì mú aláìlágbára lára le tàbí wo aláìsàn sàn tàbí di ọgbẹ́ fún ẹni tí o fi ara pa. Ìwọ kò í tí ì mú aṣáko padà tàbí wá ẹni tí ó nù. Ìwọ ṣe àkóso wọn ní ọ̀nà lílé pẹ̀lú ìwà òǹrorò.
Aka nue te na moem uh pawt tih aka tlo te na toi uh pawh. Aka khaem te na khop uh pawt tih a heh uh te khaw na mael uh puei pawh. Aka milh te khaw na toem uh pawh. Tedae amih te mangkhak la, thama la na buem uh.
5 Nítorí náà wọn fọ́n káàkiri nítorí àìsí olùṣọ́-àgùntàn, nígbà tí wọ́n fọ́nká tán wọn di ìjẹ fún gbogbo ẹranko búburú.
Aka dawn a tal dongah taekyak uh tangloeng. A taek a yak vaengah tah khohmuen mulhing boeih kah cakok la poeh.
6 Àgùntàn mi n rin ìrìn àrè kiri ní gbogbo àwọn òkè gíga àti òkè kékeré. A fọ́n wọn ká gbogbo orí ilẹ̀ ẹni kankan kò sì wá wọn.
Ka boiva loh tlang tom neh som a sang tom ah palang uh. Diklai hman tom ah ka boiva loh a taekyak vaengah toem voel pawt tih tlap voel pawh.
7 “‘Nítorí náà, ìwọ olùṣọ́-àgùntàn, gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
Te dongah aka dawn rhoek loh BOEIPA ol te hnatun uh.
8 Níwọ́n ìgbà tí mo wà láààyè ní Olúwa Olódùmarè wí, nítorí pé agbo ẹran mi kò ní olùṣọ́-àgùntàn nítorí tí a kọ̀ wọ́n, tì wọ́n sì di ìjẹ fún ẹranko búburú gbogbo àti pé, nítorí tí àwọn olùṣọ́-àgùntàn mi kò ṣe àwárí agbo ẹran mi, ṣùgbọ́n wọn ń ṣe ìtọ́jú ara wọn dípò ìtọ́jú agbo ẹran mi,
Kai tah hingnah ni tite Boeipa Yahovah kah olphong ni. Ka boiva te maeh la om mailai pawt nim? Ka boiva loh khohmuen mulhing boeih kah cakok la a poeh he khaw dawn voel pawt tih a toem pawt dongah ni. Ka boiva te ka dawn sak dae amamih aka dawn la luem tih ka boiva te dawn uh pawh.
9 nítorí náà, ẹ̀yin olùṣọ́-àgùntàn, gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
Te dongah tu dawn rhoek loh BOEIPA ol hnatun uh.
10 Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi ṣe ìlòdì sí àwọn Olùṣọ́-àgùntàn, èmi yóò sì béèrè agbo ẹran mi lọ́wọ́ wọn. Èmi yóò sì mú wọn dẹ́kun àti máa darí agbo ẹran mi, tí àwọn olùṣọ́-àgùntàn náà kò sì ní lè bọ́ ara wọn mọ́. Èmi yóò gba agbo ẹran mi kúrò ni ẹnu wọn, kì yóò sì jẹ́ oúnjẹ fún wọn mọ́.
Ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. Tu aka dawn rhoek te ka pai thil coeng tih amih kut lamkah ka boiva te ka toem ni. Amih te boiva aka luem puei lamloh ka paa sak daengah ni amamih ah aka dawn long khaw koep a luem thil uh pawt eh. Ka boiva te amih ka lamloh ka huul daengah ni amih kah cakok la a poeh pawt eh.
11 “‘Nítorí èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi fúnra mi yóò wá àgùntàn mi kiri, èmi yóò sì ṣe àwárí wọn.
Ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. Kai kamah loh ka boiva te ka toem ngawn vetih amih ka hnukdawn ni he.
12 Gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́-àgùntàn ṣe fojú tó agbo ẹran rẹ̀ tí ó fọ́nká nígbà tí ó wà pẹ̀lú wọn, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò ṣe fojú tó àgùntàn mi. Èmi yóò gbá wọn kúrò ni gbogbo ibi tí wọ́n fọ́nká sí ni ọjọ́ ìkùùkuu àti òkùnkùn.
Te khohnin ah anih te a tuping aka dawn hnukdawnkung bangla taekyak tangtae a boiva lakli ah om ni. Ka boiva te ka hnukdawn vetih cingmai neh yinnah hnin ah a taek a yak nah hmuen boeih lamloh amih te ka huul ni.
13 Èmi yóò mú wọn jáde kúrò ní àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò sì kó wọn jọ láti inú àwọn ìlú, èmi yóò sì mú wọn wá sí ilẹ̀ ara wọn. Èmi yóò mú wọn jẹ ni orí àwọn òkè gíga Israẹli, ni àárín àwọn òkè àti ní gbogbo ibùdó ilẹ̀ náà.
Amih te pilnam lamloh ka khuen vetih amih te paeng tom lamloh ka coi ni. Amih te amamih khohmuen la ka thak vetih amih Israel tlang kah sokca neh khohmuen tolrhum cungkuem ah ka luem puei ni.
14 Èmi yóò ṣe ìtọ́jú wọn ní pápá oko tútù dáradára, àní orí àwọn òkè gíga ti Israẹli ni yóò jẹ́ ilẹ̀ ìjẹ koríko wọ́n. Níbẹ̀ wọn yóò dùbúlẹ̀ ní ilẹ̀ ìjẹ koríko dídára, níbẹ̀ wọn yóò jẹun ní pápá oko tútù tí ó dara ní orí òkè ti Israẹli.
Amih te luemnah then neh ka luem puei vetih Israel tlang sang ah amih kah tolkhoeng om ni. Tolkhoeng then ah kol uh vetih Israel tlang kah luemnah dongah pulpulh luem uh ni.
15 Èmi fúnra mi yóò darí àgùntàn mi, èmi yóò mú wọn dùbúlẹ̀, ni Olúwa Olódùmarè wí.
Ka boiva te kamah loh ka luem puei vetih amih te kamah loh ka kol sak ni. He tah ka Boeipa Yahovah olphong ni.
16 Èmi yóò ṣe àwárí àwọn tí ó nú, èmi yóò mú àwọn tí ó ń rin ìrìn àrè kiri padà. Èmi yóò di ọgbẹ́ àwọn tí ó fi ara pa, èmi yóò sì fún àwọn aláìlágbára ni okun, ṣùgbọ́n àwọn tí ó sanra tí ó sì ni agbára ní èmi yóò parun. Èmi yóò ṣe olùṣọ́ àwọn agbo ẹran náà pẹ̀lú òdodo.
Aka milh te ka toem vetih a heh tangtae te khaw ka mael puei ni. Aka khaem te ka poi pah vetih aka nue te tha ka caang sak ni. Tedae pulpulh aka tlungluen khaw ka mitmoeng sak vetih tiktamnah neh ka luem sak ni.
17 “‘Ní tìrẹ, agbo ẹran mi, èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi yóò ṣe ìdájọ́ láàrín àgùntàn kan àti òmíràn, àti láàrín àgbò àti ewúrẹ́.
Nangmih ka boiva rhoek aw, ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. Kai loh tu neh tu laklo, tutal laklo neh kikong laklo ah lai ka tloek coeng he.
18 Ṣé oúnjẹ jíjẹ ní pápá oko tútù dídára kò tó yín! Ṣé ó jẹ́ dandan fún ọ láti fi ẹsẹ̀ tẹ pápá oko tútù rẹ tí ó kù? Ṣé omi tí ó tòrò kò tó fún yín ní mímu? Ṣe dandan ni kí ó fi ẹrẹ̀ yí ẹsẹ̀ yín?
Luemnah then ah na luem uh tena yakvawt nim? Na luemnah coih te na kho neh na taelh. Tui cil na ok dae a coih te na kho neh na nu sak.
19 Ṣé dandan ni kí agbo ẹran mi jẹ́ koríko tí ẹ ti tẹ̀ mọ́lẹ̀, kí wọn sì mú omi tí wọ́n ti fi ẹsẹ̀ wọn sọ di ẹrẹ̀?
Nangmih kho loh a cawtkoi te ka boiva loh luem thil saeh lamtah nangmih kho loh a nookkoi te o saeh a?
20 “‘Nítorí náà, èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí fún wọn: Wò ó, èmi fúnra mi yóò ṣe ìdájọ́ láàrín àgùntàn tí ó sanra àti èyí tí ó rù.
Te dongah ka boeipa Yahovah loh amih taengah he ni a thui. Kai kamah loh tu tha laklo neh tu pim laklo ah lai ka tloek ngawn ni.
21 Nítorí ti ìwọ sún síwájú pẹ̀lú ìhà àti èjìká, tí ìwọ sì kan aláìlágbára àgùntàn pẹ̀lú ìwo rẹ títí ìwọ fi lé wọn lọ,
Na vae neh, laengpang neh na nen uh tih na ki neh na thoeh uh. Amih te boeih a muei hil vongvoel la na taek na yak uh.
22 Èmi yóò gba agbo ẹran mi là, a kì yóò sì kò wọ́n tì mọ́. Èmi yóò ṣe ìdájọ́ láàrín àgùntàn kan àti òmíràn.
Te dongah ka boiva te ka khang vetih maeh la om voel mahpawh. Tu neh tu laklo ah lai ka tloek.
23 Èmi yóò fi Olùṣọ́-àgùntàn kan ṣe olórí wọn, ìránṣẹ́ mi Dafidi, òun yóò sì tọ́jú wọn; òun yóò bọ́ wọn yóò sì jẹ́ Olùṣọ́-àgùntàn wọn.
Amih aka dawn te pakhat ka thoh pah vetih amih te a luem puei ni. Ka sal David loh amih te a luem puei vetih amah te amih aka dawn la om ni.
24 Èmi Olúwa yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn, ìránṣẹ́ mi Dafidi yóò jẹ́ ọmọ-aládé láàrín wọn. Èmi Olúwa ní o sọ̀rọ̀.
BOEIPA kamah he amih taengah Pathen la ka om vetih ka sal David tah amih lakli ah khoboei la om ni. He he BOEIPA kamah long ni ka thui.
25 “‘Èmi yóò dá májẹ̀mú àlàáfíà pẹ̀lú wọn, èmi yóò sì gba ilẹ̀ náà kúrò lọ́wọ́ ẹranko búburú, kí wọn kí o lè gbé ní aṣálẹ̀, kí àgùntàn sì gbé ní inú igbó ní àìléwu.
Amih taengah rhoepnah paipi ka saii vetih boethae mulhing te diklai lamloh ka kangkuen sak ni. Te daengah ni khosoek ah ngaikhuek la kho a sak uh vetih duup ah a ih uh eh.
26 Èmi yóò bùkún wọn àti ibi agbègbè ti ó yí òkè mi ká. Èmi yóò rán ọ̀wààrà òjò ni àkókò; òjò ìbùkún yóò sì wà.
Amih te ka som kaepvai kah yoethennah te ka paek ni. A tue vaengah khonal ka tueih vetih yoethennah khonal la om ni.
27 Àwọn igi igbó yóò mú èso wọn jáde, ilẹ̀ yóò sì mu irúgbìn jáde; A yóò sì dá ààbò bo àwọn ènìyàn ní ilẹ̀ náà. Wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa, nígbà tí mo bá já àwọn ohun tí ó ṣe okùnfà àjàgà, tí mo sì gbà wọ́n kúrò lọ́wọ́ àwọn tí ó fi wọ́n ṣe ẹrú.
Khohmuen thingkung loh a thaih te a paek vetih diklai loh a cangpai a paek ni. A khohmuen ah ngaikhuek la om uh vetih BOEIPA kamah he m'ming uh ni. Te vaengah amih kah hnamkun hnokohcung te ka haih pah vetih amih aka thotat sak kut lamloh amih ka huul ni.
28 Àwọn orílẹ̀-èdè kì yóò lè kó wọn ní ẹrú mọ́, àwọn ẹranko búburú kì yóò lè pa wọn mọ́. Wọn yóò gbé ni àìléwu, kò sì ṣí ẹni kankan tí yóò le dẹ́rùbà wọ́n.
Namtom kah maeh la om uh voel pawt vetih amih te diklai mulhing loh dolh mahpawh. Ngaikhuek la kho a sak uh vetih lakueng uh mahpawh.
29 Èmi yóò pèsè ilẹ̀ ti o ní oríyìn fún èso rẹ̀ fún wọn, wọn kì yóò sì jìyà nípasẹ̀ ìyàn mọ́ ni ilẹ̀ náà tàbí ru ẹ̀gàn àwọn orílẹ̀-èdè.
A thingling ming te amih ham ka thoh ni. Te daengah ni khokha aka tlung khaw khohmuen ah om voel pawt vetih namtom taengah mingthae a phueih uh voel pawt eh.
30 Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé, èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn, èmi wà pẹ̀lú wọn àti pé, àwọn ilé Israẹli jẹ́ ènìyàn mi, ni Olúwa Olódùmarè wí.
Te vaengah kai he amih taengkah a Pathen BOEIPA neh amih Israel imkhui khaw ka pilnam la a ming uh bitni. He tah ka Boeipa Yahovah kah olphong ni.
31 Ìwọ àgùntàn mi, àgùntàn pápá mi; ni ènìyàn, èmi sì ni Ọlọ́run rẹ; ni Olúwa Olódùmarè wí.’”
Nangmih tah kai kah boiva ni. Nangmih kah hlang te khaw ka rhamtlim khuikah boiva ni. Kai tah nangmih kah Pathen ni. He tah ka Boeipa Yahovah kah olphong ni,” a ti.

< Ezekiel 34 >