< Ezekiel 33 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
We Perwerdigarning sözi manga kélip shundaq déyildi: —
2 “Ọmọ ènìyàn sọ̀rọ̀ sí àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ kí ó sì sọ fún wọn: ‘Nígbà tí mo bá fi idà kọlu ilẹ̀ kan, tí àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà yan ọ̀kan lára àwọn ọkùnrin wọn láti jẹ́ alóre wọn,
I insan oghli, el-yurtungdikilerge söz yetküzüp ulargha mundaq dégin: — Men qilichni melum bir zémin üstige chiqarghinimda, zémindiki xelq öz arisidin bir ademni tépip uni közetchi békétse, —
3 tí ó sì rí i pé idà ń bọ̀ lórí ilẹ̀ náà, tí ó sì fọn ìpè láti kìlọ̀ fún àwọn ènìyàn,
u qilichning zémin üstige chiqqanliqini körüp, kanay chélip xelqni agahlandursa,
4 nígbà náà tí ẹnikẹ́ni bá gbọ́ ìpè ṣùgbọ́n tí kò gbọ́ ìkìlọ̀, tí idà náà wá tí ó sì gba ẹ̀mí rẹ̀, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò wà lórí ara rẹ̀.
kimdikim kanay awazini anglap, agahni almisa, qilich kélip uni élip ketse, emdi uning qéni öz béshi üstige bolidu.
5 Nítorí tí ó gbọ́ ohùn ìpè ṣùgbọ́n tí kò sì gbọ́ ìkìlọ̀, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò wà ní orí ara rẹ̀. Tí ó bá gbọ́ ìkìlọ̀, òun ìbá ti gba ara rẹ̀ là.
U kanay awazini anglap, agahni almighan; shunga uning qéni özige bolidu; u agah alghan bolsa, jénini qutquzghan bolatti.
6 Ṣùgbọ́n bí alóre bá rí idà tí o ń bọ̀, tí kò sì fọn ìpè láti ki àwọn ènìyàn nílọ̀, tí idà náà wá, tí ó sì gba ẹ̀mí ọ̀kan nínú wọn, a yóò mú ọkùnrin náà lọ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n èmi yóò béèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.’
Biraq közetchi qilichning kéliwatqinini körüp, kanay chalmay, xelqni agahlandurmisa, emdi qilich kélip ular arisidin birawni élip ketse, undaqta u öz qebihlikide élip kétilidu; biraq uning qéni üchün Men közetchidin hésab alimen.
7 “Ọmọ ènìyàn, èmi fi ọ ṣe alóre fún ilé Israẹli; nítorí náà gbọ́ ọ̀rọ̀ tí mo sọ, kí o sì fún wọn ni ìkìlọ̀ láti ọ̀dọ̀ mi.
Emdi, i insan oghli, Men séni Israil jemeti üchün közetchi dep békitkenmen; sen Méning aghzimdin xewer anglap, ulargha Mendin agah yetküzisen.
8 Nígbà ti mo bá sọ fún ẹni búburú pé, ‘A! Ẹni búburú, ìwọ yóò kú dandan,’ ti ìwọ kò sì sọ̀rọ̀ síta láti yí i lọ́kàn padà kúrò ni ọ̀nà rẹ̀ gbogbo, ẹni búburú náà yóò kú nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, èmi yóò sì béèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ.
Men rezil ademge: «I rezil adem, sen choqum ölisen» désem, we özüng bu rezilni yolidin yandurushqa söz qilmay uni agahlandurmisang, u rezil öz qebihlikide ölidu; biraq uning qéni üchün sendin hésab alimen.
9 Ṣùgbọ́n bí ìwọ bá kìlọ̀ fún ẹni búburú láti yí padà kúrò ni ọ̀nà rẹ̀ gbogbo, tí òun kò sì ṣe bẹ́ẹ̀, òun yóò kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ìwọ ti gba ọkàn rẹ̀ là.
Biraq sen rezilni yolidin yénish toghruluq agahlandursang, u yolidin yanmisa, u öz qebihlikide ölidu; biraq özüng öz jéningni qutquzup qalisen.
10 “Ọmọ ènìyàn; sọ fún ilé Israẹli, ‘Èyí yìí ní ìwọ sọ: “Àwọn ìrékọjá àti ẹ̀ṣẹ̀ wa tẹ orí wa ba, àwa sì ń ṣòfò dànù nítorí wọn. Bá wó wa ni a ṣe lè yè?”’
Emdi sen, i insan oghli, Israil jemetige söz qilip: — Siler: «Bizning itaetsizliklirimiz we gunahlirimiz béshimizdidur, biz ular bilen zeipliship kétiwatimiz; emdi biz qandaqmu hayatqa érishimiz?» deysiler.
11 Sọ fún wọn pé, ‘Níwọ́n ìgbà tí mo wà láààyè ni Olúwa Olódùmarè wí, èmi kò ní inú dídùn sí ikú ènìyàn búburú, ṣùgbọ́n dípò bẹ́ẹ̀, kí wọ̀nyí padà kúrò ní ọ̀nà wọn gbogbo kì wọn kì ó sì yè. Yí! Yípadà kúrò ni ọ̀nà búburú gbogbo! Kí ló dé tí ìwọ yóò kú ẹ̀yin ènìyàn Israẹli?’
Ulargha sözümni yetküzüp: «Men hayatim bilen qesem qilimenki, — deydu Reb Perwerdigar, — Men rezil ademning ölümidin héch xursenlikim yoqtur; peqet ularni rezil yolidin yénip hayatqa érishsun deymen; rezil yolliringlardin yéninglar, yéninglar! Némishqa ölgünglar kélidu, i Israil jemeti?!» — dégin.
12 “Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, sọ fún àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ, ‘Ìṣòdodo ti olódodo ènìyàn kì yóò gbà á nígbà tí òun bá ṣe àìgbọ́ràn, ìwà búburú ènìyàn búburú kì yóò mú kí o ṣubú nígbà tí ó bá yí padà kúrò nínú rẹ̀. Bí olódodo ènìyàn bá ṣẹ̀, a kò ni jẹ́ kí ó yè nítorí òdodo rẹ̀ ti tẹ́lẹ̀.’
We sen, i insan oghli, el-yurtungdikilerge mundaq dégin: — Heqqaniy ademning heqqaniyliqi asiyliq qilghan künide uni qutquzmaydu; hem rezil adem bolsa, u öz rezillikidin yan’ghan künide rezillikidin yiqilmaydu; heqqaniy adem gunah sadir qilghan künide, u eslidiki heqqaniyliqi bilen hayatta turiwermeydu.
13 Bí mo bá sọ fún olódodo ènìyàn pé òun yóò yè, ṣùgbọ́n nígbà náà tí ó gbẹ́kẹ̀lé òdodo rẹ̀ tí ó sì ṣe búburú, a kò ní rántí nǹkan kan nínú iṣẹ́ òdodo tí o ti ṣe sẹ́yìn; òun yóò kú nítorí búburú tí ó ṣe.
Men heqqaniygha: «Sen berheq hayatqa érishsen» déginimde, u öz heqqaniyliqigha tayinip qebihlik sadir qilsa, emdi uning heqqaniy ishliridin héchqaysisi eslenmeydu; eksiche u ötküzgen qebihliki tüpeylidin ölidu.
14 Bí mo bá sọ fún ènìyàn búburú pé, ‘Ìwọ yóò kú dandan,’ ṣùgbọ́n tí ó bá yípadà kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ti o sì ṣe èyí tí ó tọ́ àti èyí tí o yẹ.
Emdi men rezilge: «Sen choqum ölisen» désem, biraq u gunahidin yénip, köz aldimda adalet we heqqaniyliqni yürgürse —
15 Tí ó bá mu ògo padà, tí o sì da ohun tí o ti jí gbé padà, tí ó sì tẹ̀lé òfin tí ó ń fún ni ní ìyè, tí kò sì ṣe búburú, òun yóò yè dandan; òun kì yóò kú.
Rezil adem qerzge kapaletke alghan nersini qayturup berse, — bulangchiliqta alghanni qayturup berse — qebihlik sadir qilmay, hayat belgilimiliride mangsa — emdi u berheq hayatqa ige bolidu, u ölmeydu.
16 A kò ní rántí ọ̀kan nínú ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti dá. Ó ti ṣe èyí tí ó tọ àti èyí tí o yẹ; òun yóò sì yè dájúdájú.
Uning sadir qilghan gunahliridin héchqaysisi eslenmeydu; u adalet we heqqaniyliqni yürgürgen — u berheq hayatqa ige bolidu.
17 “Síbẹ̀ àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ sọ pé, ‘Ọ̀nà Olúwa kò tọ́.’ Ṣùgbọ́n ọ̀nà tí àwọn ní ó tọ́.
Biraq el-yurtungdikiler: «Rebning yoli hemmige barawer emes» deydu; emeliyette ularning yoli bolsa hemmige barawer emes.
18 Bí olódodo ènìyàn ba yípadà kúrò nínú òdodo rẹ̀, tí o sì ṣe búburú, òun yóò kú nítorí rẹ̀.
Heqqaniy adem öz heqqaniyliqidin yénip, qebihlikni sadir qilsa, u buningda ölidu.
19 Bí ènìyàn búburú bá yípadà kúrò nínú búburú rẹ̀, tí ó sì ṣe èyí tí ó tọ́ àti èyí tí ó yẹ, òun yóò yè nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀.
Rezil adem öz rezillikidin yénip, adalet we heqqaniyliq yürgürse, bu ishlardin hayatqa ige bolidu.
20 Síbẹ̀, ilé Israẹli ìwọ wí pé, ‘Ọ̀nà Olúwa ki i ṣe òtítọ́.’ Ṣùgbọ́n èmi yóò ṣe ìdájọ́ ẹnìkọ̀ọ̀kan gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀ ṣe rí.”
Lékin siler: «Rebning yoli hemmige barawer emes» deysiler; i Israil jemeti, Men herqaysinglargha öz yolliringlar boyiche üstünglerge höküm chiqirimen!
21 Ní ọjọ́ karùn-ún oṣù kẹwàá, ọdún kejìlá ìkólọ wa, ọkùnrin kan tí ó sá kúrò ni Jerusalẹmu wá sọ́dọ̀ mi, ó sì wí pé, “Ìlú ńlá náà ti ṣubú!”
We shundaq boldiki, sürgün bolghan on ikkinchi yili, oninchi ayning beshinchi künide, Yérusalémdin qachqan birsi yénimgha kélip: «Sheher bösüldi!» — dédi.
22 Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ tí ó ku ọ̀la tí ẹni tí ó sálọ náà yóò dé, ọwọ́ Olúwa sì níbẹ̀ lára mi, o sì ya ẹnu mi ki ọkùnrin náà tó wá sọ́dọ̀ mi ní òwúrọ̀. Ẹnu mí sì ṣí, èmi kò sì yadi mọ́.
Emdi qachqan ademning yétip kélishining aldinqi axshimida Perwerdigarning qoli méning wujudumgha qon’ghanidi; shuning bilen U aghzimni échip qoydi; aghzim échilip, men yene gacha bolmidim.
23 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
We Perwerdigarning sözi manga kélip shundaq déyildi: —
24 “Ọmọ ènìyàn, àwọn ènìyàn tí ó ń gbé nínú ìparun ní ilẹ̀ Israẹli ń wí pé, ‘Abrahamu jẹ́ ọkùnrin kan, síbẹ̀ o gba ilẹ̀ ìní náà. Ṣùgbọ́n àwa pọ̀, lóòótọ́ a ti fi ilẹ̀ náà fún wa gẹ́gẹ́ bí ìní wa.’
I insan oghli, Israil zéminidiki xarabe jaylarda turuwatqanlar: «Ibrahim peqet bir adem turupmu bu zémin’gha miras bolghanidi; biraq biz köp ademmiz; emdi zémin beribir bizge teqdim qilindi» — dep éytiwatidu.
25 Nítorí náà, sọ fún wọn pé, ‘Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Níwọ́n ìgbà tí ẹ̀yin jẹ ẹran pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ni inú rẹ̀, tí ẹ̀yin sì wó àwọn ère yín, tí ẹ sì ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀, ẹ̀yin yóò ha gba ilẹ̀ náà?
Shunga ulargha mundaq dégin: — Reb Perwerdigar mundaq deydu: «Siler göshni qan bilen yeysiler; siler öz mebudliringlarni bash kötürüp izdeysiler; siler qan töküwatisiler; emdi siler zémin’gha miras bolamsiler?
26 Ẹ̀yin gbẹ́kẹ̀lé idà yín, ẹ̀yin ṣe nǹkan ìríra, ẹnìkọ̀ọ̀kan nínú yín ba á obìnrin aládùúgbò rẹ̀ jẹ́. Ẹ̀yin yóò ha gba ilẹ̀ náà?’
Siler qilichinglargha tayinisiler, siler yirginchlik ishlarni chiqirisiler, herbiringlar öz qoshnisining ayaligha buzuqchiliq qilidu. Emdi siler zémin’gha miras bolamsiler?».
27 “Sọ èyí fún wọn: ‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Bí mo ti wà láààyè, àwọn tí ó kúrò nínú ìparun yóò ti ipa idà ṣubú, àwọn tí ẹranko búburú yóò pajẹ, àwọn tí ó sì wà ní ilé ìṣọ́ àti inú ihò òkúta ni àjàkálẹ̀-ààrùn yóò pa.
Ulargha mundaq dégin: — Reb Perwerdigar mundaq deydu: Men hayatim bilen qesem qilimenki, berheq, xarabe jaylarda turuwatqanlar qilichlinip yiqilidu; dalada qalghanni yawayi haywanlarning yewétishke tapshurimen; istihkamlar we gharlarda turghanlarmu waba késilidin ölidu.
28 Èmi yóò mú kí ilẹ̀ náà di ahoro, ọ̀ṣọ́ ńlá agbára rẹ̀ kì yóò sí mọ́, àwọn òkè Israẹli yóò sì di ahoro, tí ẹnikẹ́ni kò ní le là á kọjá.
Men zéminni weyrane we chöl-bayawan qilimen; uning küchidin bolghan pexri yoqilidu; Israilning taghliri weyrane boliduki, ulardin ötküchi héchbir adem bolmaydu.
29 Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa, nígbà tí mo bá mú ilẹ̀ náà di ahoro nítorí gbogbo ohun ìríra tí wọ́n ti ṣe.’
Ularning yürgüzgen yirginchlik qilmishliri tüpeylidin Men zéminni weyrane we chöl-bayawan qilghinimda ular Méning Perwerdigar ikenlikimni tonup yétidu».
30 “Ní tìrẹ, ọmọ ènìyàn, àwọn ènìyàn ìlú n sọ̀rọ̀ nípa rẹ ní ẹ̀gbẹ́ ògiri àti ní ẹnu-ọ̀nà ilé wọn, wọ́n ń sọ sí ara wọn wí pé, ‘Ẹ wá gbọ́ iṣẹ́ ti a ran láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá.’
— Emdi sen bolsang, i insan oghli, el-yurtungdikiler herdaim séni aghzigha élip öylirining tamlirining yénida we derwazilarda sözlep bir-birige hem herbiri öz qérindishigha sen toghruluq: «Qéni bérip, Perwerdigardin néme söz barkin, anglap kéleyli!» — deydu.
31 Àwọn ènìyàn mi wá sọ́dọ̀ rẹ, gẹ́gẹ́ bí wọn ṣe ń ṣe, wọn sì jókòó níwájú rẹ láti fetísí ọ̀rọ̀ rẹ, ṣùgbọ́n wọn kò mú wá sí ìṣe. Ẹnu wọn ni wọ́n fi n sọ̀rọ̀ ìfọkànsìn, ṣùgbọ́n ọkàn wọn ní ìwọra èrè tí kò tọ́.
Ular jamaet süpitide yéninggha kélip, Méning xelqimning süpitide aldingda olturidu; ular sözliringni anglaydu, biraq ulargha emel qilmaydu; ular aghzi bilen sanga muhebbet körsitidu, biraq köngli haram menpeetke tartidu;
32 Nítòótọ́ lójú wọn, ìwọ jẹ́ ẹni kan tí ó ń kọrin ìfẹ́ pẹ̀lú ohun dídára àti ohun èlò orin kíkọ, nítorí wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ ṣùgbọ́n wọn kò mu wá sí ìṣe.
mana, sen ular üchün peqet yéqimliq awaz bilen, sazliri obdan tengshilip éytilghan muhebbet naxshisisen, xalas; ular sözliringni anglaydu, biraq ulargha emel qilmaydu.
33 “Nígbà tí gbogbo ìwọ̀nyí bá ṣẹ tí yóò sì ṣẹ dandan, nígbà náà wọn yóò mọ̀ pé wòlíì kan ti wa láàrín wọn rí.”
Emdi buning hemmisi emelge ashurulghinida (u berheq emelge ashurulidu!) ular bir peyghemberning ularning arisida bolghanliqini tonup yétidu».

< Ezekiel 33 >