< Ezekiel 33 >
HIKI mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
2 “Ọmọ ènìyàn sọ̀rọ̀ sí àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ kí ó sì sọ fún wọn: ‘Nígbà tí mo bá fi idà kọlu ilẹ̀ kan, tí àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà yan ọ̀kan lára àwọn ọkùnrin wọn láti jẹ́ alóre wọn,
E ke keiki a ke kanaka, e olelo aku i na keiki o kou poe kanaka, ei aku ia lakou, O ka aina, ina lawe au i ka pahikaua maluna ona, a lawe na kanaka o ka aina i ke kanaka o ko lakou mau palena, a e hooku ia ia i kiai no lakou;
3 tí ó sì rí i pé idà ń bọ̀ lórí ilẹ̀ náà, tí ó sì fọn ìpè láti kìlọ̀ fún àwọn ènìyàn,
Aia ike ia i ka pahikaua e hele mai ana maluna o ka aina, ina e pupuhi oia i ka pu e ao aku i kanaka;
4 nígbà náà tí ẹnikẹ́ni bá gbọ́ ìpè ṣùgbọ́n tí kò gbọ́ ìkìlọ̀, tí idà náà wá tí ó sì gba ẹ̀mí rẹ̀, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò wà lórí ara rẹ̀.
Alaila, o ka mea lohe i ke kani ana o ka pu, aole hoi i malama i ke ao ana; a ina hele mai ka pahikaua, a lawe aku ia ia, aia no kona koko maluna o kona poo iho.
5 Nítorí tí ó gbọ́ ohùn ìpè ṣùgbọ́n tí kò sì gbọ́ ìkìlọ̀, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò wà ní orí ara rẹ̀. Tí ó bá gbọ́ ìkìlọ̀, òun ìbá ti gba ara rẹ̀ là.
O ke kani ana o ka pu kana i lohe ai, aka, aole ia i malama i ke ao ana; aia maluna ona iho hoi kona koko: aka, o ka mea malama i ke ao ana, e hoopakele oia i kona ola iho.
6 Ṣùgbọ́n bí alóre bá rí idà tí o ń bọ̀, tí kò sì fọn ìpè láti ki àwọn ènìyàn nílọ̀, tí idà náà wá, tí ó sì gba ẹ̀mí ọ̀kan nínú wọn, a yóò mú ọkùnrin náà lọ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n èmi yóò béèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.’
Aka, ina ike ke kiai i ka hele ana mai o ka pahikaua, aole hoi pupuhi i ka pu, aole hoi e aoia na kanaka; a hele mai ka pahikaua, a e lawe aku i kekahi maiwaena aku o lakou, ua laweia'ku oia maloko o kona hewa; aka, e kii aku au i kona koko ma ka lima o ke kiai.
7 “Ọmọ ènìyàn, èmi fi ọ ṣe alóre fún ilé Israẹli; nítorí náà gbọ́ ọ̀rọ̀ tí mo sọ, kí o sì fún wọn ni ìkìlọ̀ láti ọ̀dọ̀ mi.
Pela no oe, e ke keiki a ke kanaka, ua hooku au ia oe i kiai no ka ohana a Iseraela; nolaila e hoolohe oe i ka olelo ma ko'u waha, a e ao aku ia lakou na'u aku no.
8 Nígbà ti mo bá sọ fún ẹni búburú pé, ‘A! Ẹni búburú, ìwọ yóò kú dandan,’ ti ìwọ kò sì sọ̀rọ̀ síta láti yí i lọ́kàn padà kúrò ni ọ̀nà rẹ̀ gbogbo, ẹni búburú náà yóò kú nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, èmi yóò sì béèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ.
Aia olelo au i ke kanaka hewa, E ke kanaka hewa, e make io no oe; ina aole oe e olelo aku e ao aku i ua kanaka la no kona aoao, e make no ia kanaka hewa maloko o kona hewa; aka, e kii aku no au i kona koko ma kou lima.
9 Ṣùgbọ́n bí ìwọ bá kìlọ̀ fún ẹni búburú láti yí padà kúrò ni ọ̀nà rẹ̀ gbogbo, tí òun kò sì ṣe bẹ́ẹ̀, òun yóò kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ìwọ ti gba ọkàn rẹ̀ là.
Aka, ina e ao aku oe i ka mea hewa no kona aoao, aole hoi i huli mai, mai koua aoao mai, e make no ia iloko o kona hewa; aka, ua hoopakele oe i kou uhane iho.
10 “Ọmọ ènìyàn; sọ fún ilé Israẹli, ‘Èyí yìí ní ìwọ sọ: “Àwọn ìrékọjá àti ẹ̀ṣẹ̀ wa tẹ orí wa ba, àwa sì ń ṣòfò dànù nítorí wọn. Bá wó wa ni a ṣe lè yè?”’
A o oe, e ke keiki a ke kanaka, e olelo aku oe i ka ohana a Iseraela, Ke olelo nei oukou, i ka i ana, Ina eia maluna o kakou ko kakou mau hala a me ko kakou mau hewa, a olala ae kakou maloko oia mau mea, pehea la hoi kakou e ola'i?
11 Sọ fún wọn pé, ‘Níwọ́n ìgbà tí mo wà láààyè ni Olúwa Olódùmarè wí, èmi kò ní inú dídùn sí ikú ènìyàn búburú, ṣùgbọ́n dípò bẹ́ẹ̀, kí wọ̀nyí padà kúrò ní ọ̀nà wọn gbogbo kì wọn kì ó sì yè. Yí! Yípadà kúrò ni ọ̀nà búburú gbogbo! Kí ló dé tí ìwọ yóò kú ẹ̀yin ènìyàn Israẹli?’
E olelo aku ia lakou, Ma ko'u ola ana, wahi a Iehova ka Haku, aohe o'u oluolu i ka make ana o ka mea hewa; aka hoi, e huli mai ka mea hewa, mai kona aoao mai, a e ola ia; e huli mai, e huli mai oukou mai ko oukou mau aoao hewa mai; no ke aha la oukou e make ai, e ka ohana a Iseraela?
12 “Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, sọ fún àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ, ‘Ìṣòdodo ti olódodo ènìyàn kì yóò gbà á nígbà tí òun bá ṣe àìgbọ́ràn, ìwà búburú ènìyàn búburú kì yóò mú kí o ṣubú nígbà tí ó bá yí padà kúrò nínú rẹ̀. Bí olódodo ènìyàn bá ṣẹ̀, a kò ni jẹ́ kí ó yè nítorí òdodo rẹ̀ ti tẹ́lẹ̀.’
Nolaila, e ke keiki a ke kanaka, e olelo aku i na keiki a kou poe kanaka, Aole ka pono o ka mea pono e hoopakele ia ia i ka la e hewa ai ia: a o ka hewa o ka mea hewa, aole oia e haule ilaila i ka la e huli ai oia mai kona hewa mai: aole hoi e hiki i ka mea pono ke ola nona, i kona la e hana hewa ai.
13 Bí mo bá sọ fún olódodo ènìyàn pé òun yóò yè, ṣùgbọ́n nígbà náà tí ó gbẹ́kẹ̀lé òdodo rẹ̀ tí ó sì ṣe búburú, a kò ní rántí nǹkan kan nínú iṣẹ́ òdodo tí o ti ṣe sẹ́yìn; òun yóò kú nítorí búburú tí ó ṣe.
Aia olelo aku au i ka mea pono, e ola io no ia; ina e hilinai oia ma kona pono iho, a hana hewa hoi, e pau no kona pono i ka hoomanao ole ia; aka, no kona hewa ana i hana'i, e make ai no ia.
14 Bí mo bá sọ fún ènìyàn búburú pé, ‘Ìwọ yóò kú dandan,’ ṣùgbọ́n tí ó bá yípadà kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ti o sì ṣe èyí tí ó tọ́ àti èyí tí o yẹ.
A i ka wa e olelo aku ai au i ka mea hewa, E make io no oe; ina e huli mai ia, mai kona hewa mai, a hana hoi i ka mea pono a me ka pololei;
15 Tí ó bá mu ògo padà, tí o sì da ohun tí o ti jí gbé padà, tí ó sì tẹ̀lé òfin tí ó ń fún ni ní ìyè, tí kò sì ṣe búburú, òun yóò yè dandan; òun kì yóò kú.
Ina e hoihoi aku ka mea hewa i ka waiwai kaohi a ka aie, a ua hoihoi aku hoi i ka waiwai ana i lawe wale ai, a ua hele hoi ma na kanawai e ola'i, me ka hana hewa ole; e ola io no ia, aole ia e make.
16 A kò ní rántí ọ̀kan nínú ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti dá. Ó ti ṣe èyí tí ó tọ àti èyí tí o yẹ; òun yóò sì yè dájúdájú.
Aole loa ka hewa ana i hana'i e haiia'ku ia ia; ua hana oia i ka mea pono a me ka pololei, e ola io no ia.
17 “Síbẹ̀ àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ sọ pé, ‘Ọ̀nà Olúwa kò tọ́.’ Ṣùgbọ́n ọ̀nà tí àwọn ní ó tọ́.
Aka, ke olelo nei na keiki o kou poe kanaka, Aole kaulike na aoao o ka Haku; aka, o lakou, aole kaulike ko lakou aoao.
18 Bí olódodo ènìyàn ba yípadà kúrò nínú òdodo rẹ̀, tí o sì ṣe búburú, òun yóò kú nítorí rẹ̀.
A huli ae ka mea pono mai kona pono ae, a hana ma ka hewa, e make no hoi ia malaila.
19 Bí ènìyàn búburú bá yípadà kúrò nínú búburú rẹ̀, tí ó sì ṣe èyí tí ó tọ́ àti èyí tí ó yẹ, òun yóò yè nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀.
A huli ae ka mea hewa mai kona hewa ae, a hana hoi i ka mea pono a me ka pololei, e ola no ia malaila.
20 Síbẹ̀, ilé Israẹli ìwọ wí pé, ‘Ọ̀nà Olúwa ki i ṣe òtítọ́.’ Ṣùgbọ́n èmi yóò ṣe ìdájọ́ ẹnìkọ̀ọ̀kan gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀ ṣe rí.”
Aka, ke olelo nei oukou, Aole kaulike na aoao o ka Haku. E hooponopono aku au ia oukou, kela kanaka keia kanaka, e like me kona aoao, e ka ohana a Iseraela.
21 Ní ọjọ́ karùn-ún oṣù kẹwàá, ọdún kejìlá ìkólọ wa, ọkùnrin kan tí ó sá kúrò ni Jerusalẹmu wá sọ́dọ̀ mi, ó sì wí pé, “Ìlú ńlá náà ti ṣubú!”
Eia keia, i ka umikumamalua o ka makahiki o ko kakou pio ana, i ka malama umi, i ka la alima o ka malama, hele mai io'u nei kekahi i pakele, mai Ierusalema mai, i mai la, Ua pepehiia ke kulanakauhale.
22 Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ tí ó ku ọ̀la tí ẹni tí ó sálọ náà yóò dé, ọwọ́ Olúwa sì níbẹ̀ lára mi, o sì ya ẹnu mi ki ọkùnrin náà tó wá sọ́dọ̀ mi ní òwúrọ̀. Ẹnu mí sì ṣí, èmi kò sì yadi mọ́.
A ua kau mai ka lima o Iehova maluna o'u i ke ahiahi mamua o ka hiki ana mai io'u nei o ka mea i pakele; a ua wehe mai i kuu waha, a hiki mai ia i ke kakahiaka; a ua weheia kuu waha, aole au i leopaa hou aku.
23 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Alaila, hiki mai ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
24 “Ọmọ ènìyàn, àwọn ènìyàn tí ó ń gbé nínú ìparun ní ilẹ̀ Israẹli ń wí pé, ‘Abrahamu jẹ́ ọkùnrin kan, síbẹ̀ o gba ilẹ̀ ìní náà. Ṣùgbọ́n àwa pọ̀, lóòótọ́ a ti fi ilẹ̀ náà fún wa gẹ́gẹ́ bí ìní wa.’
E ke keiki a ke kanaka, o ka poe i noho ma keia mau wahi neoneo o ka aina o ka Iseraela, ke olelo nei lakou, i ka i ana, Hookahi no o Aberahama, a ua ili ka aina ia ia; a he nui no hoi kakou, a ua haawi mai ka aina no kakou i waiwai ili.
25 Nítorí náà, sọ fún wọn pé, ‘Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Níwọ́n ìgbà tí ẹ̀yin jẹ ẹran pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ni inú rẹ̀, tí ẹ̀yin sì wó àwọn ère yín, tí ẹ sì ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀, ẹ̀yin yóò ha gba ilẹ̀ náà?
Nolaila, e olelo aku ia lakou, Ke i mai nei Iehova ka Haku, Ua ai oukou me ke koko, a ua leha ae i ko oukou mau maka i ko oukou poe akuakii, a ua hookahe i ke koko; e loaa anei ia oukou ka aina?
26 Ẹ̀yin gbẹ́kẹ̀lé idà yín, ẹ̀yin ṣe nǹkan ìríra, ẹnìkọ̀ọ̀kan nínú yín ba á obìnrin aládùúgbò rẹ̀ jẹ́. Ẹ̀yin yóò ha gba ilẹ̀ náà?’
Ke ku nei oukou maluna o ka oukou pahikaua, ke hana nei oukou i ka mea inainaia; ke hoohaumia nei oukou, kela kanaka keia kanaka, i ka wahine a kona hoalauna; e loaa anei ia oukou ka aina?
27 “Sọ èyí fún wọn: ‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Bí mo ti wà láààyè, àwọn tí ó kúrò nínú ìparun yóò ti ipa idà ṣubú, àwọn tí ẹranko búburú yóò pajẹ, àwọn tí ó sì wà ní ilé ìṣọ́ àti inú ihò òkúta ni àjàkálẹ̀-ààrùn yóò pa.
Penei e olelo aku ai ia lakou, Ke i mai nei Iehova ka Haku penei; Ma ko'u ola ana, o ka poe ma na wahi neoneo, e haule lakou i ka pahikaua, a o ka mea ma ke kula mawaho ka'u e haawi aku ai i na holoholona hihiu, e pau ai i ka aiia; a o ka poe maloko o na pakaua a me na ana, e make no lakou i ka mai ahulau.
28 Èmi yóò mú kí ilẹ̀ náà di ahoro, ọ̀ṣọ́ ńlá agbára rẹ̀ kì yóò sí mọ́, àwọn òkè Israẹli yóò sì di ahoro, tí ẹnikẹ́ni kò ní le là á kọjá.
E haawi au i ka aina i neoneo loa, a e oki ka hanohano o kona ikaika; a e neoneo no hoi na mauna o ka Iseraela, aole mea e hele ae mawaena.
29 Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa, nígbà tí mo bá mú ilẹ̀ náà di ahoro nítorí gbogbo ohun ìríra tí wọ́n ti ṣe.’
Alaila e ike lakou owau no Iehova, aia haawi au i ka aina i neoneo loa, no na mea inainaia a lakou i hana'i.
30 “Ní tìrẹ, ọmọ ènìyàn, àwọn ènìyàn ìlú n sọ̀rọ̀ nípa rẹ ní ẹ̀gbẹ́ ògiri àti ní ẹnu-ọ̀nà ilé wọn, wọ́n ń sọ sí ara wọn wí pé, ‘Ẹ wá gbọ́ iṣẹ́ ti a ran láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá.’
A o oe, e ke keiki a ke kanaka, ke kamailio ku e nei na keiki a kou poe kanaka ia oe, ma na paia, a ma na puka o na hale, a ua olelo kekahi i kekahi, kela mea keia mea i kona hoahanau, e i ana, E hele mai oukou, ea, a e hoolohe i ka olelo i hiki mai, mai Iehova mai.
31 Àwọn ènìyàn mi wá sọ́dọ̀ rẹ, gẹ́gẹ́ bí wọn ṣe ń ṣe, wọn sì jókòó níwájú rẹ láti fetísí ọ̀rọ̀ rẹ, ṣùgbọ́n wọn kò mú wá sí ìṣe. Ẹnu wọn ni wọ́n fi n sọ̀rọ̀ ìfọkànsìn, ṣùgbọ́n ọkàn wọn ní ìwọra èrè tí kò tọ́.
A ua hele lakou iou la, e like me ka hele ana o kanaka, a ua noho lakou imua ou e like me ko'u poe kanaka, a ua lohe lakou i kau mau olelo, aole hoi lakou e malama aku ia; no ka mea, me ko lakou waha, ua hoike lakou i ke aloha nui. aka, me ko lakou naau, ua hahai lakou mamuli o ko lakou makee waiwai.
32 Nítòótọ́ lójú wọn, ìwọ jẹ́ ẹni kan tí ó ń kọrin ìfẹ́ pẹ̀lú ohun dídára àti ohun èlò orin kíkọ, nítorí wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ ṣùgbọ́n wọn kò mu wá sí ìṣe.
Ua lilo oe ia lakou me he mele makemakeia la a ka mea leo oluolu a e hiki ia ia ke hula pono ma ka mea kani; no ka mea, ua lohe lakou i kau mau olelo, aole nae lakou e hana malaila.
33 “Nígbà tí gbogbo ìwọ̀nyí bá ṣẹ tí yóò sì ṣẹ dandan, nígbà náà wọn yóò mọ̀ pé wòlíì kan ti wa láàrín wọn rí.”
Aia hiki mai keia mea; aia hoi, e hiki mai no ia, alaila e ike no lakou, he kanla ka iwaena o lakou.