< Ezekiel 33 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
BOEIPA ol te kai taengla ha pawk tih,
2 “Ọmọ ènìyàn sọ̀rọ̀ sí àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ kí ó sì sọ fún wọn: ‘Nígbà tí mo bá fi idà kọlu ilẹ̀ kan, tí àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà yan ọ̀kan lára àwọn ọkùnrin wọn láti jẹ́ alóre wọn,
“Hlang capa aw, na pilnam paca te voek lamtah amih te thui pah. Khohmuen te cunghang ka muk thil vaengah khohmuen pilnam loh a khobawt lamkah hlang pakhat te a tuek uh tih anih te amamih kah rhaltawt la a khueh uh.
3 tí ó sì rí i pé idà ń bọ̀ lórí ilẹ̀ náà, tí ó sì fọn ìpè láti kìlọ̀ fún àwọn ènìyàn,
cunghang loh khohmuen soah a tlak te a hmuh vaengah tuki a ueng tih pilnam te a thuituen.
4 nígbà náà tí ẹnikẹ́ni bá gbọ́ ìpè ṣùgbọ́n tí kò gbọ́ ìkìlọ̀, tí idà náà wá tí ó sì gba ẹ̀mí rẹ̀, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò wà lórí ara rẹ̀.
Tuki ol te a yaak khaw a yaak dae a ngaihuet pawt dongah cunghang loh a tlak thil. Te vaengah anih a loh te a thii khaw amah lu dongah tla saeh.
5 Nítorí tí ó gbọ́ ohùn ìpè ṣùgbọ́n tí kò sì gbọ́ ìkìlọ̀, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò wà ní orí ara rẹ̀. Tí ó bá gbọ́ ìkìlọ̀, òun ìbá ti gba ara rẹ̀ là.
Tuki ol a yaak lalah a ngaihuet pawt atah amah thii ni amah soah a tlak eh. Amah a ngaihuet atah a hinglu a hlawt ni.
6 Ṣùgbọ́n bí alóre bá rí idà tí o ń bọ̀, tí kò sì fọn ìpè láti ki àwọn ènìyàn nílọ̀, tí idà náà wá, tí ó sì gba ẹ̀mí ọ̀kan nínú wọn, a yóò mú ọkùnrin náà lọ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n èmi yóò béèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.’
Tedae rhaltawt loh cunghang ha pawk te a hmuh lalah tuki te ueng pawt tih pilnam huek pawh. Te vaengah cunghang ha pawk tih amih lamkah a hinglu te a loh pa atah amah kathaesainah kongah yook mai cakhaw a thii te rhaltawt kut ah ni ka toem eh.
7 “Ọmọ ènìyàn, èmi fi ọ ṣe alóre fún ilé Israẹli; nítorí náà gbọ́ ọ̀rọ̀ tí mo sọ, kí o sì fún wọn ni ìkìlọ̀ láti ọ̀dọ̀ mi.
Nang hlang capa namah ni Israel imkhui kah rhaltawt la kang khueh coeng. Te dongah ka ka lamkah ol na yaak neh kai lamloh amih te huek laeh.
8 Nígbà ti mo bá sọ fún ẹni búburú pé, ‘A! Ẹni búburú, ìwọ yóò kú dandan,’ ti ìwọ kò sì sọ̀rọ̀ síta láti yí i lọ́kàn padà kúrò ni ọ̀nà rẹ̀ gbogbo, ẹni búburú náà yóò kú nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, èmi yóò sì béèrè ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ.
Halang, halang te, 'Na duek rhoe na duek ni, 'ka ti nah lalah halang te a longpuei lamloh ngaihuet sak ham na thui pawt atah, halang te amah kathaesainah dongah duek cakhaw a thii te tah nang kut ah ni ka toem eh.
9 Ṣùgbọ́n bí ìwọ bá kìlọ̀ fún ẹni búburú láti yí padà kúrò ni ọ̀nà rẹ̀ gbogbo, tí òun kò sì ṣe bẹ́ẹ̀, òun yóò kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ìwọ ti gba ọkàn rẹ̀ là.
Tedae nang loh halang te a longpuei lamloh mael sak ham na huek lalah a longpuei lamloh a mael pawt atah amah thaesainah ah duek vetih nang tah na hinglu na huul ni.
10 “Ọmọ ènìyàn; sọ fún ilé Israẹli, ‘Èyí yìí ní ìwọ sọ: “Àwọn ìrékọjá àti ẹ̀ṣẹ̀ wa tẹ orí wa ba, àwa sì ń ṣòfò dànù nítorí wọn. Bá wó wa ni a ṣe lè yè?”’
Te dongah nang hlang capa, Israel imkhui te voek laeh. He he thui lamtah, 'Mamih kah boekoek neh mamih kah tholhnah ngawn tah mamih soah tla coeng. Amih kongah mamih m'muei uh tih metlae n'hing eh? 'ti saeh.
11 Sọ fún wọn pé, ‘Níwọ́n ìgbà tí mo wà láààyè ni Olúwa Olódùmarè wí, èmi kò ní inú dídùn sí ikú ènìyàn búburú, ṣùgbọ́n dípò bẹ́ẹ̀, kí wọ̀nyí padà kúrò ní ọ̀nà wọn gbogbo kì wọn kì ó sì yè. Yí! Yípadà kúrò ni ọ̀nà búburú gbogbo! Kí ló dé tí ìwọ yóò kú ẹ̀yin ènìyàn Israẹli?’
Amih te thui pah. Kai tah hingnah ni. He he Ka Boeipa Yahovah kah olphong ni. Halang kah dueknah dongah khaw ka naep pawt dongah halang khaw a longpuei lamloh lat mael saeh lamtah hing saeh. Na boethae longpuei lamloh mael rhoe mael laeh. Balae tih Israel imkhui loh tarha na duek eh?
12 “Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, sọ fún àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ, ‘Ìṣòdodo ti olódodo ènìyàn kì yóò gbà á nígbà tí òun bá ṣe àìgbọ́ràn, ìwà búburú ènìyàn búburú kì yóò mú kí o ṣubú nígbà tí ó bá yí padà kúrò nínú rẹ̀. Bí olódodo ènìyàn bá ṣẹ̀, a kò ni jẹ́ kí ó yè nítorí òdodo rẹ̀ ti tẹ́lẹ̀.’
Te dongah nang hlang capa loh na pilnam paca te thui pah. A boekoek hnin ah tah aka dueng kah duengnah loh anih te huul mahpawh. A halangnah lamloh a mael khohnin ah halang kah halangnah dongah khaw tongtah mahpawh. Aka dueng khaw a tholh khohnin ah tah tholh neh a hing ham coeng pawh.
13 Bí mo bá sọ fún olódodo ènìyàn pé òun yóò yè, ṣùgbọ́n nígbà náà tí ó gbẹ́kẹ̀lé òdodo rẹ̀ tí ó sì ṣe búburú, a kò ní rántí nǹkan kan nínú iṣẹ́ òdodo tí o ti ṣe sẹ́yìn; òun yóò kú nítorí búburú tí ó ṣe.
Aka dueng te hing rhoe hing ni ka ti sitoe cakhaw anih te amah kah duengnah dongah pangtung tih dumlai saii koinih anih kah duengnah boeih te a duengnah la poek uh mahpawh. A dumlai a saii dongah te amah ni a. duek eh.
14 Bí mo bá sọ fún ènìyàn búburú pé, ‘Ìwọ yóò kú dandan,’ ṣùgbọ́n tí ó bá yípadà kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ti o sì ṣe èyí tí ó tọ́ àti èyí tí o yẹ.
Halang te duek rhoe duek ni ka ti bal sitoe cakhaw a tholhnah lamloh mael tih tiktamnah neh duengnah a saii.
15 Tí ó bá mu ògo padà, tí o sì da ohun tí o ti jí gbé padà, tí ó sì tẹ̀lé òfin tí ó ń fún ni ní ìyè, tí kò sì ṣe búburú, òun yóò yè dandan; òun kì yóò kú.
A halang akhaw hnohol te a mael tih a huenkoe te koep a thuung, hingnah khosing dongah pongpa tih dumlai a saii pawt atah hing roe hing vetih duek mahpawh.
16 A kò ní rántí ọ̀kan nínú ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti dá. Ó ti ṣe èyí tí ó tọ àti èyí tí o yẹ; òun yóò sì yè dájúdájú.
A tholhnah cungkuem neh a tholh te a a taengah tholhnah poek uh pawt vetih tiktamnah neh duengnah a saii dongah hing rhoe hing ni.
17 “Síbẹ̀ àwọn ènìyàn ilẹ̀ rẹ sọ pé, ‘Ọ̀nà Olúwa kò tọ́.’ Ṣùgbọ́n ọ̀nà tí àwọn ní ó tọ́.
Te vaengah na pilnam paca loh, “Boeipa kah longpuei tiktam pawh,” ti uh cakhaw amih kah a longpuei ni a. tiktam pawh.
18 Bí olódodo ènìyàn ba yípadà kúrò nínú òdodo rẹ̀, tí o sì ṣe búburú, òun yóò kú nítorí rẹ̀.
Aka dueng khaw a duengnah lamloh mael tih dumlai a saii atah te dongah te duek van ni.
19 Bí ènìyàn búburú bá yípadà kúrò nínú búburú rẹ̀, tí ó sì ṣe èyí tí ó tọ́ àti èyí tí ó yẹ, òun yóò yè nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀.
Halang khaw a halangnah lamloh mael tih tiktamnah neh duengnah a saii atah te nen te anih hing ni.
20 Síbẹ̀, ilé Israẹli ìwọ wí pé, ‘Ọ̀nà Olúwa ki i ṣe òtítọ́.’ Ṣùgbọ́n èmi yóò ṣe ìdájọ́ ẹnìkọ̀ọ̀kan gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀ ṣe rí.”
'Ka Boeipa kah longpuei tiktam pawh,’ na ti uh dae hlang he a longpuei tarhing ah ni nang Israel imkhui te lai kan tloek eh?,” a ti.
21 Ní ọjọ́ karùn-ún oṣù kẹwàá, ọdún kejìlá ìkólọ wa, ọkùnrin kan tí ó sá kúrò ni Jerusalẹmu wá sọ́dọ̀ mi, ó sì wí pé, “Ìlú ńlá náà ti ṣubú!”
Kaimih hlangsol kah kum hlai nit hla rha hnin nga a lo vaengah Jerusalem lamkah hlangyong te kai taengla ha pawk tih, “Khopuei a tloek coeng,” a ti.
22 Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ tí ó ku ọ̀la tí ẹni tí ó sálọ náà yóò dé, ọwọ́ Olúwa sì níbẹ̀ lára mi, o sì ya ẹnu mi ki ọkùnrin náà tó wá sọ́dọ̀ mi ní òwúrọ̀. Ẹnu mí sì ṣí, èmi kò sì yadi mọ́.
Hlangyong ha pawk hmai kah kholaeh ah BOEIPA kut te kai soah om coeng. Te dongah kai taengla aka pawk taengah mincang due ka ka a ong. Ka ka a ong tangloeng vaengah tah ka khuep voel pawh.
23 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Te vaengah BOEIPA ol te kai taengah ah ha pawk tih,
24 “Ọmọ ènìyàn, àwọn ènìyàn tí ó ń gbé nínú ìparun ní ilẹ̀ Israẹli ń wí pé, ‘Abrahamu jẹ́ ọkùnrin kan, síbẹ̀ o gba ilẹ̀ ìní náà. Ṣùgbọ́n àwa pọ̀, lóòótọ́ a ti fi ilẹ̀ náà fún wa gẹ́gẹ́ bí ìní wa.’
“Hlang capa aw, Israel khohmuen imrhong kah khosa rhoek loh, 'Abraham pakhat bueng ni om tih khohmuen a pang mai. Tedae kaimih he yet ham he kamamih taengah khohmuen ni khoh la m'paek,” a ti uh.
25 Nítorí náà, sọ fún wọn pé, ‘Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Níwọ́n ìgbà tí ẹ̀yin jẹ ẹran pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ni inú rẹ̀, tí ẹ̀yin sì wó àwọn ère yín, tí ẹ sì ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀, ẹ̀yin yóò ha gba ilẹ̀ náà?
Te dongah amih taengah ka Boeipa Yahovah kah a thui he thui pah. Thii te na caak uh tih na mik te na mueirhol taengla na huel. Thii na kingling cingah nim khohmuen na pang eh?
26 Ẹ̀yin gbẹ́kẹ̀lé idà yín, ẹ̀yin ṣe nǹkan ìríra, ẹnìkọ̀ọ̀kan nínú yín ba á obìnrin aládùúgbò rẹ̀ jẹ́. Ẹ̀yin yóò ha gba ilẹ̀ náà?’
Na cunghang dongah na pangnal uh tih tueilaehkoi na saii uh. Hlang long he a hui kah yuu te na poeih uh cingah nim khohmuen na pang eh?
27 “Sọ èyí fún wọn: ‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Bí mo ti wà láààyè, àwọn tí ó kúrò nínú ìparun yóò ti ipa idà ṣubú, àwọn tí ẹranko búburú yóò pajẹ, àwọn tí ó sì wà ní ilé ìṣọ́ àti inú ihò òkúta ni àjàkálẹ̀-ààrùn yóò pa.
Ka Boeipa Yahovah loh a thui he amih taengah thui pah. Hingnah khaw kamah coeng dongah imrhong khuikah rhoek te cunghang dongah cungku uh het mahpawt nim? Te phoeiah khohmuen hoeng kah te mulhing taengla ka paek vetih anih te a ngaeh ni. Rhalmahim khui neh lungko khuikah te khaw duektahaw nen ni a. duek uh eh.
28 Èmi yóò mú kí ilẹ̀ náà di ahoro, ọ̀ṣọ́ ńlá agbára rẹ̀ kì yóò sí mọ́, àwọn òkè Israẹli yóò sì di ahoro, tí ẹnikẹ́ni kò ní le là á kọjá.
Khohmuen te khopong neh a rhaerhap la ka khueh vetih a hoemdamnah a sarhi a kangkuen sak ni. Te vaengah Israel tlang te pong vetih aka paan om mahpawh.
29 Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa, nígbà tí mo bá mú ilẹ̀ náà di ahoro nítorí gbogbo ohun ìríra tí wọ́n ti ṣe.’
Tedae BOEIPA kamah loh khohmuen te khopong neh rhaerhap la ka khueh khaw amamih kah tueilaehkoi cungkuem a saii uh dongah ni tila a ming uh bitni.
30 “Ní tìrẹ, ọmọ ènìyàn, àwọn ènìyàn ìlú n sọ̀rọ̀ nípa rẹ ní ẹ̀gbẹ́ ògiri àti ní ẹnu-ọ̀nà ilé wọn, wọ́n ń sọ sí ara wọn wí pé, ‘Ẹ wá gbọ́ iṣẹ́ ti a ran láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá.’
“Nang hlang capa aw na pilnam paca loh nang te pangbueng kaep neh im thohka taengah n'thui uh. Hlang pakhat loh a manuca te kang a voek tih, 'Lo laeh lamtah BOEIPA taeng lamkah hang khuen ol he hnatun uh,’ a ti.
31 Àwọn ènìyàn mi wá sọ́dọ̀ rẹ, gẹ́gẹ́ bí wọn ṣe ń ṣe, wọn sì jókòó níwájú rẹ láti fetísí ọ̀rọ̀ rẹ, ṣùgbọ́n wọn kò mú wá sí ìṣe. Ẹnu wọn ni wọ́n fi n sọ̀rọ̀ ìfọkànsìn, ṣùgbọ́n ọkàn wọn ní ìwọra èrè tí kò tọ́.
Nang taengah khotlak pilnam bangla ha pawk uh van tih ka pilnam bangla na mikhmuh ah kho a sak uh. Na ol te a yaak uh van akhaw te te a vai uh moenih. A ka dongah hlampan uh ngawn cakhaw a lungbuei ah amamih kah mueluemnah dongah a pongpa te a phoe uh.
32 Nítòótọ́ lójú wọn, ìwọ jẹ́ ẹni kan tí ó ń kọrin ìfẹ́ pẹ̀lú ohun dídára àti ohun èlò orin kíkọ, nítorí wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ ṣùgbọ́n wọn kò mu wá sí ìṣe.
Nang te amih taengah sakthen ol neh hlampan laa banghui ni ne. Na ol yaak sak ham balh na tum akhaw te te aka vai a om uh hae moenih.
33 “Nígbà tí gbogbo ìwọ̀nyí bá ṣẹ tí yóò sì ṣẹ dandan, nígbà náà wọn yóò mọ̀ pé wòlíì kan ti wa láàrín wọn rí.”
Tedae te te ha pawk vaengah tah rhep ha pawk vetih amih lakli ah tonghma a om te a ming uh bitni,” a ti.

< Ezekiel 33 >