< Ezekiel 32 >

1 Ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kejìlá, ọdún kejìlá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Kum hlai nit, hla hlai nit, hlasae hnin at a pha vaengah BOEIPA ol te kai taengla ha pawk tih,
2 “Ọmọ ènìyàn, ṣe ìpohùnréré ẹkún nítorí Farao ọba Ejibiti kí o sì wí fún un: “‘Ìwọ dàbí kìnnìún láàrín àwọn orílẹ̀-èdè náà; ìwọ dàbí ohun ẹ̀mí búburú inú àwọn omi okun to ń lọ káàkiri inú àwọn odò rẹ, ìwọ fi ẹsẹ̀ rẹ tẹ omi láti mú kí àwọn odò ní ẹrẹ̀.
“Hlang capa aw, Egypt manghai Pharaoh ham rhahlung phueih pah lamtah amah te thui pah. Namtom kah sathuengca na puet dae tuipuei kah tuihnam bangla na om. Na tuiva ah m'poh tih na kho neh tui na nok dongah a tuiva na nu sak.
3 “‘Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Pẹ̀lú ọ̀pọ̀ ìpéjọ ènìyàn èmi yóò da àwọ̀n mi bò ọ́ wọn yóò sì fà ọ́ sókè nínú àwọ̀n mi.
Ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui ni. Nang soah ka lawk he pilnam hlangping neh kan thing khungdaeng vetih nang te kai kah yaehtaboeih neh n'doek uh ni.
4 Èmi yóò jù ọ́ sí orí ilẹ̀ èmi yóò sì fà ọ́ sókè sí orí pápá gbangba. Èmi yóò jẹ́ kí gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run ṣe àtìpó ní orí rẹ. Gbogbo àwọn ẹranko ayé yóò fi ìwọra gbé ara wọn lórí rẹ.
Nang te diklai ah kam phap vetih khohmuen hoeng ah nang kang hut ni. Vaan kah vaa cungkuem loh nang soah cu vetih nang te diklai mulhing tom ka cung sak ni.
5 Èmi yóò tan ẹran-ara rẹ ká sórí àwọn òkè gíga ìyókù ara rẹ ní wọn yóò fi kún àwọn àárín àwọn òkè gíga.
Na saa te tlang ah ka khueh vetih na rhok te kolrhawk ah ka bae sak ni.
6 Ẹ̀jẹ̀ rẹ ti ń sàn ní èmi yóò sì fi rin ilẹ̀ náà gbogbo ọ̀nà sí orí àwọn òkè gíga, àwọn àlàfo jíjìn ní wọn yóò kún fún ẹran-ara rẹ.
Na thii la tlang due na ka long neh diklai ka suep vetih nang nen te sokca rhoek khaw bae uh ni.
7 Nígbà tí mo bá fọ́n ọ jáde, èmi yóò pa ọ̀run dé àwọn ìràwọ̀ wọn yóò sì ṣókùnkùn; èmi yóò sì fi ìkùùkuu bo oòrùn òṣùpá kì yóò sì tan ìmọ́lẹ̀ rẹ̀.
Nang kan thih vaengah vaan te ka thing vetih a aisi te ka kopang sak ni. Khomik te cingmai neh ka thing vetih hla kah a vangnah khaw sae mahpawh.
8 Gbogbo ìmọ́lẹ̀ títàn ní ojú ọ̀run ni èmi yóò mú ṣókùnkùn lórí rẹ; èmi yóò mú òkùnkùn wá sórí ilẹ̀ rẹ, ni Olúwa Olódùmarè wí.
Vaan kah a aa vangnah cungkuem te nang soah ka hmuep sak vetih na khohmuen soah hmaisuep ka tlak sak ni. He tah ka Boeipa ka Yahovah kah olphong ni.
9 Èmi yóò da ọkàn ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn rú nígbà tí mo bá mú ìparun rẹ wá ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè tí ìwọ kò í tí ì mọ̀.
Amih te na ming pawt dae diklai kah namtom taengah na pocinah te ka khuen vaengah pilnam kah lungbuei muep ka veet ni.
10 Èmi yóò mú kí ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn dẹ́rùbà ọ́, àwọn ọba wọn yóò sì wárìrì fún ìbẹ̀rù pẹ̀lú ìpayà nítorí rẹ, nígbà tí mo bá ju idà mi ní iwájú wọn. Ní ọjọ́ ìṣubú rẹ ọ̀kọ̀ọ̀kan nínú wọn yóò wárìrì ní gbogbo ìgbà fún ẹ̀mí rẹ.
Nang soah pilnam boeiping te ka pong sak vetih a manghai rhoek khaw nang kong ah hlithae loh a yawn ni. Amih mikhmuh ah ka cunghang ka hlaek vetih na cungkunah hnin ah tah hlang he a hinglu ham mikhaptok ah lakueng uh ni.
11 “‘Nítorí èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Idà ọba Babeli yóò wá sí orí rẹ,
Ka Boeipa Yahovah he ni a thui. Babylon manghai kah cunghang he nang taengla ha pawk ni.
12 Èmi yóò mú kí ìjọ ènìyàn rẹ kí ó tí ipa idà àwọn alágbára ènìyàn ṣubú àwọn orílẹ̀-èdè aláìláàánú jùlọ. Wọn yóò tú ìgbéraga Ejibiti ká, gbogbo ìjọ rẹ ní a yóò dá ojú wọn bolẹ̀.
Amih namtom hlanghaeng neh hlangrhalh boeih kah cunghang dongah na hlangping te ka cungku sak ni. Egypt kah hoemdamnah te a rhoelrhak uh vetih a hlangping khaw boeih a mitmoeng sak ni.
13 Gbogbo ẹran ọ̀sìn rẹ ni èmi yóò parun ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi kì i ṣe ẹsẹ̀ ènìyàn ní yóò tẹ ibẹ̀ ẹsẹ̀ ẹran ọ̀sìn kì yóò sì mú kí ibẹ̀ ni ẹrọ̀fọ̀.
Tui yet taeng lamkah a rhamsa boeih te ka milh sak ni. Te te hlang kho loh koep nok pawt vetih rhamsa khomae loh te te nok mahpawh.
14 Lẹ́yìn náà èmi yóò mú kí omi rẹ̀ tòrò kí àwọn odò rẹ̀ kí o sàn bí epo, ni Olúwa Olódùmarè wí.
Te vaengah a tui ka cil sak vetih a tuiva te situi bangla ka long sak ni. He tah ka Boeipa Yahovah olphong ni.
15 Nígbà tí mo bá sọ Ejibiti di ahoro, tí mo sì kó gbogbo ohun tí ó wà ní orí ilẹ̀ náà kúrò. Nígbà tí mo bá gé àwọn olùgbé ibẹ̀ lulẹ̀, nígbà náà wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’
Egypt khohmuen te khopong la ka khueh coeng. Te dongah a khuikah khosa boeih te ka ngawn tih khohmuen te a pum la a pong vaengah BOEIPA kamah he m'ming uh bitni.
16 “Èyí yìí ni ẹkún tí a yóò sun fún un. Àwọn ọmọbìnrin orílẹ̀-èdè yóò sun ún; nítorí Ejibiti àti gbogbo ìjọ rẹ, wọn yóò sun ún, ní Olúwa Olódùmarè wí.”
He rhahlung neh anih te a rhaengsae uh ni. Namtom canu rhoek loh Egypt ham rhaengsae uh vetih a hlangping boeih ham rhaengsae uh ni. He tah ka Boeipa Yahovah kah olphong ni,” a ti.
17 Ní ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù, ọdún kejìlá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ mí wá:
Kum hlai nit hla khat hnin hlai nga vaengah BOEIPA ol te kai taengla ha pawk tih,
18 “Ọmọ ènìyàn, pohùnréré ẹkún lórí Ejibiti kí o sì ránṣẹ́ sí ìsàlẹ̀ ilẹ̀ àti òun àti àwọn ọmọbìnrin orílẹ̀-èdè alágbára, pẹ̀lú àwọn tí o lọ sí ìsàlẹ̀, kòtò.
Hlang capa aw, Egypt hlangping ham rhathi laeh. Anih khaw diklai laedil duela tangrhom ah aka suntla taengah namtom tanu aka khuet neh suntla uh saeh.
19 Sọ fún wọn, ‘Ǹjẹ́ ìwọ ní ojúrere jù àwọn tí o kù lọ? Lọ sí ìsàlẹ̀ kí a sì tẹ́ ọ sí àárín àwọn aláìkọlà náà.’
Unim na hmae thil ngai? Suntla lamtah pumdul rhoek taengah yalh laeh.
20 Wọn yóò ṣubú láàrín àwọn tí a fi idà pa. A fa idà yọ; jẹ́ kí a wọ́ Ejibiti kúrò pẹ̀lú gbogbo ìjọ rẹ̀.
cunghang dongkah a mop te cunghang dongkah rhok lakli ah ni a yalh eh. Anih neh a hlangping boeih te sol laeh.
21 Láti inú isà òkú alágbára tí í ṣe aṣáájú yóò sọ nípa Ejibiti àti àwọn àlejò rẹ̀, ‘Wọn ti wá sí ìsàlẹ̀, wọn sì sùn pẹ̀lú aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa.’ (Sheol h7585)
Anih te Saelkhui lamkah neh pathen hlangrhalh rhoek neh anih aka bom rhoek loh thui uh saeh. cunghang dongkah pumdul rhok dongla suntla uh tih yalh uh lah ko. (Sheol h7585)
22 “Asiria wà níbẹ̀ pẹ̀lú gbogbo jagunjagun rẹ̀; àwọn isà òkú àwọn tí a ti pa sì yí i ká, gbogbo àwọn tí ó ti ipa idà ṣubú.
Te ah te Assyria neh a hlangping boeih he a phuel kaepvai kah cunghang dongah aka cungku kah rhok boeih ni.
23 Isà òkú wọn wà ní ibi tí ó jinlẹ̀ gan an nínú kòtò. Gbogbo àwọn tí ó ti tan ẹ̀rù ká ilẹ̀ alààyè ní a pa, tí ó ti ipa idà ṣubú.
Tangrhom hlaep ah a phuel a khueh pa uh tih a phuel kaepvai ah a hlangping om. Amih boeih tah cunghang dongah cungku tih mulhing khohmuen ah rhihnah aka pae kah a rhok ni.
24 “Elamu wà níbẹ̀, o yí isà òkú rẹ̀ ká pẹ̀lú gbogbo ogun rẹ̀. Gbogbo wọn ni a pa, àwọn tí ó ti ipa idà ṣubú. Gbogbo àwọn tí ó ti tan ẹ̀rù ká ilẹ̀ alààyè lọ sí ìsàlẹ̀ láìkọlà sí abẹ́ ilẹ̀. Wọ́n gba ìtìjú wọn pẹ̀lú àwọn tí ó lọ sí ìsàlẹ̀ kòtò.
Te ah te Elam neh a hlangping boeih a phuel kaepvai ah om. Amih boeih tah cunghang dongah aka cungku kah a rhok ni. Te rhoek te diklai laedil ah pumdul la suntla uh. Te long neh mulhing khohmuen ah amih kah rhihnah a paek tih a mingthae te tangrhom kah aka suntla neh a phueih uh.
25 A ṣe ibùsùn fún un láàrín àwọn tí a pa, pẹ̀lú gbogbo ìjọ rẹ̀ tí ó yí isà òkú ká. Gbogbo wọn jẹ́ aláìkọlà, tí a fi idà pa. Nítorí pé a tan ẹ̀rù wọn ká ilẹ̀ alààyè, wọn ru ìtìjú wọn pẹ̀lú àwọn tí ó lọ sí ìsàlẹ̀ kòtò; a tẹ́ wọn pẹ̀lú àwọn tí a pa.
Anih ham tah rhok lakli ah ni thingkong a khueh pa uh. A hlangping boeih loh a phuel kah a kaepvai ah om uh. Amih te cunghang dongah a rhok pumdul boeih ni. Mulhing khohmuen ah amamih kah rhihnah a paek tih a mingthae a phueih uh phoeiah tangrhom kah aka suntla neh rhok lakli ah ni a yalh.
26 “Meṣeki àti Tubali wà níbẹ̀, pẹ̀lú gbogbo ogun wọn yí isà òkú wọn ká. Gbogbo wọn jẹ́ aláìkọlà, wọ́n fi idà pa wọ́n nítorí ẹ̀rù tiwọn tàn ká ilẹ̀ alààyè.
Te ah te Tubal Meshek neh a hlangping boeih loh a phuel kah a kaepvai ah om. Amih boeih tah amamih kah rhihnah te mulhing khohmuen ah a paek uh dongah pumdul la cunghang neh a poeih rhoek ni.
27 Wọn kì yóò sì dùbúlẹ̀ ti àwọn tí ó ṣubú nínú àwọn aláìkọlà, tí wọn sọ̀kalẹ̀ lọ sí ipò òkú pẹ̀lú ìhámọ́ra ogun wọn, wọ́n tí fi idà wọn rọ orí wọn. Ṣùgbọ́n àìṣedéédéé wọn yóò wà ní orí egungun wọn—bí wọ́n tilẹ̀ jẹ́ ẹ̀rù àwọn alágbára ní ilẹ̀ alààyè. (Sheol h7585)
Pumdul lamloh aka cungku hlangrhalh taengah khaw yalh uh hae pawh. A caemtloek hnopai neh saelkhui la suntla uh tih a cunghang te a lu hmuiah a doelh uh. A hlangrhalh rhoek loh mulhing khohmuen ah rhihnah pae cakhaw amamih kah thaesainah te amamih rhuh dongah ni a tlak. (Sheol h7585)
28 “Ìwọ náà, Farao, ní yóò ṣẹ, ti yóò dùbúlẹ̀ láàrín aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa.
Nang khaw pumdul lakli ah na bawt vetih cunghang dongkah rhok neh na yalh ni.
29 “Edomu wà níbẹ̀, àwọn ọba rẹ̀ àti gbogbo ọmọbìnrin ọba; bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ní agbára, a tẹ́ wọn pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa. Wọn dùbúlẹ̀ pẹ̀lú aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn ti o lọ sínú kòtò.
Te ah te Edom kah a manghai rhoek neh a khoboei rhoek boeih om. Te rhoek tah a thayung thamal a paek. Tedae amih te cunghang dongkah rhok taeng neh tangrhom la aka suntla pumdul rhoek taengah ni a yalh uh.
30 “Gbogbo àwọn ọmọ-aládé ilẹ̀ àríwá àti gbogbo àwọn ará Sidoni wà níbẹ̀; wọn lọ sí ìsàlẹ̀ pẹ̀lú àwọn tí a pa ní ìtìjú, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọn ṣe okùnfà ẹ̀rù pẹ̀lú agbára wọn. Wọn sùn ní àìkọlà pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa, wọn sì ru ìtìjú wọn pẹ̀lú àwọn tí ó lọ sí ìsàlẹ̀ kòtò.
Te ah te amih tlangpuei boeimang boeih neh Sidoni boeih khaw om uh. Te rhoek tah amamih kah rhihnah hmanah a rhok rhoek neh suntla uh. A thayung thamal dongah yak uh tih te cunghang dongkah rhok neh pumdul la yalh uh. Te dongah tangrhom kah aka suntla rhoek neh a mingthae a phueih uh.
31 “Farao, òun àti gbogbo jagunjagun rẹ̀ yóò rí wọn, a yóò sì tù ú nínú nítorí gbogbo ogun rẹ̀ tí a fi idà pa, ní Olúwa Olódùmarè wí.
Amih te Pharaoh loh a hmuh vaengah a hlangping boeih ham khaw, cunghang dongkah a ngawn a hlangping ham khaw, Pharaoh neh a caem boeih ham khaw damti bitni. He tah ka Boeipa Yahovah kah olphong ni.
32 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti tan ẹ̀rù ká ilẹ̀ alààyè, Farao àti gbogbo ogun rẹ̀ ni a yóò tẹ́ sí àárín aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa ní Olúwa Olódùmarè wí.”
Mulhing khohmuen ah kai rhihnah te anih kah rhihnah la ka paek. Te dongah Pharaoh neh a hlangping boeih loh cunghang dongkah rhok neh pumdul lakli ah yalh. He tah ka Boeipa Yahovah kah olphong ni,” a ti.

< Ezekiel 32 >