< Ezekiel 32 >
1 Ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kejìlá, ọdún kejìlá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Eso age amola oubi fago amola ode fago amoga ninia mugululi misi, Hina Gode da nama amane sia: i,
2 “Ọmọ ènìyàn, ṣe ìpohùnréré ẹkún nítorí Farao ọba Ejibiti kí o sì wí fún un: “‘Ìwọ dàbí kìnnìún láàrín àwọn orílẹ̀-èdè náà; ìwọ dàbí ohun ẹ̀mí búburú inú àwọn omi okun to ń lọ káàkiri inú àwọn odò rẹ, ìwọ fi ẹsẹ̀ rẹ tẹ omi láti mú kí àwọn odò ní ẹrẹ̀.
“Dunu egefe! Idibidi hina bagade ema gasa bagade sisane sia: ma! Na sia: amane alofele ima. ‘Di da fifi asi gala ba: ma: ne laione wa: me agoane hamosa. Be amomane di da hanome gafulusa dasi ahoa agoane ba: sa. Di da dia emoga hano ubagesa, amola hano wadela: lesisa.
3 “‘Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Pẹ̀lú ọ̀pọ̀ ìpéjọ ènìyàn èmi yóò da àwọ̀n mi bò ọ́ wọn yóò sì fà ọ́ sókè nínú àwọ̀n mi.
Fifi asi gala bagohame gilisisia, Na da di efegele, fifi asi gala dunu da bia gado di hiouginana masunu.
4 Èmi yóò jù ọ́ sí orí ilẹ̀ èmi yóò sì fà ọ́ sókè sí orí pápá gbangba. Èmi yóò jẹ́ kí gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run ṣe àtìpó ní orí rẹ. Gbogbo àwọn ẹranko ayé yóò fi ìwọra gbé ara wọn lórí rẹ.
Na da di osoboga galagale, osobo bagade sio amola ohe fi huluane di moma: ne oule misunu.
5 Èmi yóò tan ẹran-ara rẹ ká sórí àwọn òkè gíga ìyókù ara rẹ ní wọn yóò fi kún àwọn àárín àwọn òkè gíga.
Na dia da: i hodo dasagia: i amoga goumi amola fago huluane dedebolesimu.
6 Ẹ̀jẹ̀ rẹ ti ń sàn ní èmi yóò sì fi rin ilẹ̀ náà gbogbo ọ̀nà sí orí àwọn òkè gíga, àwọn àlàfo jíjìn ní wọn yóò kún fún ẹran-ara rẹ.
Na da dia maga: me soga: digili, goumi da amoga dedeboi amola hano da amoga nabai ba: mu.
7 Nígbà tí mo bá fọ́n ọ jáde, èmi yóò pa ọ̀run dé àwọn ìràwọ̀ wọn yóò sì ṣókùnkùn; èmi yóò sì fi ìkùùkuu bo oòrùn òṣùpá kì yóò sì tan ìmọ́lẹ̀ rẹ̀.
Na da di wadela: sea, Na da mu amola gasumuni dedebolesimu. Eso da mu mobiga uligili, wamoaligimu amola oubi da bu hame diga: mu.
8 Gbogbo ìmọ́lẹ̀ títàn ní ojú ọ̀run ni èmi yóò mú ṣókùnkùn lórí rẹ; èmi yóò mú òkùnkùn wá sórí ilẹ̀ rẹ, ni Olúwa Olódùmarè wí.
Na da mu hadigi huluane ha: ba: domu amola osobo bagade da gasi fawane ba: mu. Na, Ouligisudafa Hina Gode da sia: i dagoi.
9 Èmi yóò da ọkàn ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn rú nígbà tí mo bá mú ìparun rẹ wá ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè tí ìwọ kò í tí ì mọ̀.
Na da fifi asi gala (mogili di da hamedafa dawa: i) amoga dia da wadela: lesi dagoi olelesea, fifi asi gala bagohame da da: i dione fofogadigimu.
10 Èmi yóò mú kí ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn dẹ́rùbà ọ́, àwọn ọba wọn yóò sì wárìrì fún ìbẹ̀rù pẹ̀lú ìpayà nítorí rẹ, nígbà tí mo bá ju idà mi ní iwájú wọn. Ní ọjọ́ ìṣubú rẹ ọ̀kọ̀ọ̀kan nínú wọn yóò wárìrì ní gbogbo ìgbà fún ẹ̀mí rẹ.
Fifi asi gala bagohame da Na dima hamomu ba: sea, bagade fofogadigimu. Na da Na gegesu gobihei bagade gufuli abasea, osobo bagade hina bagade dunu ilia da beda: ga yagugumu. Di da dafasea, ilia da bogosa: besa: le, beda: igia: le, yagugumu.”
11 “‘Nítorí èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Idà ọba Babeli yóò wá sí orí rẹ,
Ouligisudafa Hina Gode da Idibidi hina bagade ema amane sia: sa, “Ba: bilone hina bagade da ea gegesu gobiheiga dima doagala: mu.
12 Èmi yóò mú kí ìjọ ènìyàn rẹ kí ó tí ipa idà àwọn alágbára ènìyàn ṣubú àwọn orílẹ̀-èdè aláìláàánú jùlọ. Wọn yóò tú ìgbéraga Ejibiti ká, gbogbo ìjọ rẹ ní a yóò dá ojú wọn bolẹ̀.
Nimi bagade fifi asi gala dadi gagui dunu da ilia gegesu gobihei dugale gadole, dia fi dunu huluane medole legema: ne, Na da logo doasimu. Dia fi dunu huluane amola dia liligi (amoma di da hidale ba: sa) huluane da gugunufinisi dagoi ba: mu.
13 Gbogbo ẹran ọ̀sìn rẹ ni èmi yóò parun ní ẹ̀gbẹ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi kì i ṣe ẹsẹ̀ ènìyàn ní yóò tẹ ibẹ̀ ẹsẹ̀ ẹran ọ̀sìn kì yóò sì mú kí ibẹ̀ ni ẹrọ̀fọ̀.
Na da dia bulamagau amo hano gu gelabo huluane gadenene medole legemu. Dunu amola bulamagau amo hano bu ubagemu da hame ba: mu.
14 Lẹ́yìn náà èmi yóò mú kí omi rẹ̀ tòrò kí àwọn odò rẹ̀ kí o sàn bí epo, ni Olúwa Olódùmarè wí.
Dia hano huluane da fafu ha: ina sa: ili, ida: iwane ba: ma: ne, Na da logo doasimu. Na, Ouligisudafa Hina Gode, da sia: i dagoi.
15 Nígbà tí mo bá sọ Ejibiti di ahoro, tí mo sì kó gbogbo ohun tí ó wà ní orí ilẹ̀ náà kúrò. Nígbà tí mo bá gé àwọn olùgbé ibẹ̀ lulẹ̀, nígbà náà wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’
Na da Idibidi soge wadela: sea, amola dunu huluane amogai esala, medole lelegesea, ilia da Na da Hina Gode dawa: mu.
16 “Èyí yìí ni ẹkún tí a yóò sun fún un. Àwọn ọmọbìnrin orílẹ̀-èdè yóò sun ún; nítorí Ejibiti àti gbogbo ìjọ rẹ, wọn yóò sun ún, ní Olúwa Olódùmarè wí.”
Amo gasa bagade sisane iasu da idigisa gesami hea: su agoane ba: mu. Fifi asi gala uda ilia da Idibidi soge amola ea fi dunu huluane ilia dafai dawa: beba: le, amo gesami gogolole disa hea: mu. Na, Ouligisudafa Hina Gode da sia: i dagoi.”
17 Ní ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù, ọdún kejìlá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ mí wá:
Eso 15amola oubi age amola ode fago amoga ninia mugululi misi, Hina Gode da nama amane sia: i,
18 “Ọmọ ènìyàn, pohùnréré ẹkún lórí Ejibiti kí o sì ránṣẹ́ sí ìsàlẹ̀ ilẹ̀ àti òun àti àwọn ọmọbìnrin orílẹ̀-èdè alágbára, pẹ̀lú àwọn tí o lọ sí ìsàlẹ̀, kòtò.
“Dunu egefe! Idibidi dunu huluane da bogomuba: le, gogolole didigia: ma. Ili amola eno gasa fifi asi gala, amo gilisili bogoi sogega asunasima.
19 Sọ fún wọn, ‘Ǹjẹ́ ìwọ ní ojúrere jù àwọn tí o kù lọ? Lọ sí ìsàlẹ̀ kí a sì tẹ́ ọ sí àárín àwọn aláìkọlà náà.’
Ilima amane sia: ma, ‘Dilia dawa: loba, dili da eno dunu ilia nina: hamoi dili baligi dawa: sala: ? Dilia da bogoi soge amoga sa: ili, Gode Ea hou hame lalegagui dunu gilisili dialumu.
20 Wọn yóò ṣubú láàrín àwọn tí a fi idà pa. A fa idà yọ; jẹ́ kí a wọ́ Ejibiti kúrò pẹ̀lú gbogbo ìjọ rẹ̀.
Idibidi fi dunu da dunu gegesu ganodini bogoi, amo gilisili bogomu. Gegesu gobihei ili huluane medole legemusa: da momagei dagoi.
21 Láti inú isà òkú alágbára tí í ṣe aṣáájú yóò sọ nípa Ejibiti àti àwọn àlejò rẹ̀, ‘Wọn ti wá sí ìsàlẹ̀, wọn sì sùn pẹ̀lú aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa.’ (Sheol )
Gasa bagade gegesu dunu, amola dunu da Idibidi fi amoma gale gegene bogoi, ilia da Idibidi bogoi dunu ilia bogoi sogega doaga: sea, ili nodone lale sala. Ilia da amane wele sia: sa, ‘Gode Ea hou hame dawa: dunu da gegesu ganodini medole legei, goegudu misini, dialumu!’ (Sheol )
22 “Asiria wà níbẹ̀ pẹ̀lú gbogbo jagunjagun rẹ̀; àwọn isà òkú àwọn tí a ti pa sì yí i ká, gbogbo àwọn tí ó ti ipa idà ṣubú.
Asilia fi da bogoi sogega diala. Dadi gagui ilia bogoi uli dogoi da ili sisiga: sa. Ilia huluane gegesu ganodini medole legei ba: i.
23 Isà òkú wọn wà ní ibi tí ó jinlẹ̀ gan an nínú kòtò. Gbogbo àwọn tí ó ti tan ẹ̀rù ká ilẹ̀ alààyè ní a pa, tí ó ti ipa idà ṣubú.
Amola ilia uli dogoi da gududafa sogebi, bogoi soge ganodini diala. Musa: fifi asi gala esalebe dunu da ilia hou ba: beba: le beda: gia: i. Be ilia da gegesu ganodini medole legei ba: i, amola wali ilia bogoi uli dogoi da fedege agoane Asilia ea bogoi soge uli dogosu sisiga: sa.
24 “Elamu wà níbẹ̀, o yí isà òkú rẹ̀ ká pẹ̀lú gbogbo ogun rẹ̀. Gbogbo wọn ni a pa, àwọn tí ó ti ipa idà ṣubú. Gbogbo àwọn tí ó ti tan ẹ̀rù ká ilẹ̀ alààyè lọ sí ìsàlẹ̀ láìkọlà sí abẹ́ ilẹ̀. Wọ́n gba ìtìjú wọn pẹ̀lú àwọn tí ó lọ sí ìsàlẹ̀ kòtò.
25 A ṣe ibùsùn fún un láàrín àwọn tí a pa, pẹ̀lú gbogbo ìjọ rẹ̀ tí ó yí isà òkú ká. Gbogbo wọn jẹ́ aláìkọlà, tí a fi idà pa. Nítorí pé a tan ẹ̀rù wọn ká ilẹ̀ alààyè, wọn ru ìtìjú wọn pẹ̀lú àwọn tí ó lọ sí ìsàlẹ̀ kòtò; a tẹ́ wọn pẹ̀lú àwọn tí a pa.
Ilame da amogawi diala. Ea dadi gagui dunu ilia uli dogoi da e sisiga: le diala. Ilia huluane gegesu ganodini medole legele, gadofo mae damuiwane, bogoi soge amo gudu sa: i. Ilia esaloba, dunu eno da ilima bagade beda: i. Be wali ilia da udigili bogoi diala, amola eno da ilima hame obenane nodosa.
26 “Meṣeki àti Tubali wà níbẹ̀, pẹ̀lú gbogbo ogun wọn yí isà òkú wọn ká. Gbogbo wọn jẹ́ aláìkọlà, wọ́n fi idà pa wọ́n nítorí ẹ̀rù tiwọn tàn ká ilẹ̀ alààyè.
Misiege amola Diubale da amogawi diala. Ela dadi gagui dunu ilia uli dogoi da ela sisiga: le diala. Ilia huluane da gadofo hame damui, amola ilia huluane da gegesu ganodini medole legei ba: i. Be musa: ilia hou hamobeba: le, esalebe dunu da beda: igia: i.
27 Wọn kì yóò sì dùbúlẹ̀ ti àwọn tí ó ṣubú nínú àwọn aláìkọlà, tí wọn sọ̀kalẹ̀ lọ sí ipò òkú pẹ̀lú ìhámọ́ra ogun wọn, wọ́n tí fi idà wọn rọ orí wọn. Ṣùgbọ́n àìṣedéédéé wọn yóò wà ní orí egungun wọn—bí wọ́n tilẹ̀ jẹ́ ẹ̀rù àwọn alágbára ní ilẹ̀ alààyè. (Sheol )
Musa: gasa bagade noga: i dunu da bogosea, dunu eno da amo nodone uli dogosu. Ilia da amo dunu ilia gegesu gobihei ilia dialuma ha ligisili, amola ilia gegesu gaga: su liligi ilia da: i hodo da: iya ligisili, uli dogosu. Amo musa: noga: i dunu da gasa bagadeba: le, esalebe dunu da beda: gia: i. (Sheol )
28 “Ìwọ náà, Farao, ní yóò ṣẹ, ti yóò dùbúlẹ̀ láàrín aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa.
Idibidi dunu da amo gadofo hame damui dunu gegesu ganodini medole legei, ili defele goudaiwane dialumu.
29 “Edomu wà níbẹ̀, àwọn ọba rẹ̀ àti gbogbo ọmọbìnrin ọba; bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó ní agbára, a tẹ́ wọn pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa. Wọn dùbúlẹ̀ pẹ̀lú aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn ti o lọ sínú kòtò.
Idome amola ea ouligisu dunu amola da amogawi esala. Ilia da gasa bagade dadi gagui dunu ba: i, be wali ilia da bogoi soge ganodini, gadofo hame damui dunu gegesu ganodini medole legei, ilima gilisili dialebe ba: sa.
30 “Gbogbo àwọn ọmọ-aládé ilẹ̀ àríwá àti gbogbo àwọn ará Sidoni wà níbẹ̀; wọn lọ sí ìsàlẹ̀ pẹ̀lú àwọn tí a pa ní ìtìjú, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọn ṣe okùnfà ẹ̀rù pẹ̀lú agbára wọn. Wọn sùn ní àìkọlà pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa, wọn sì ru ìtìjú wọn pẹ̀lú àwọn tí ó lọ sí ìsàlẹ̀ kòtò.
Ga (north) fi ouligisu dunu huluane amola Saidone dunu amola da amogawi dialebe ba: sa. Musa: , ilia da gasa bagade fili hamobeba: le, eno dunu da beda: gia: su. Be wali ilia da gogosiane, eno gadofo hame damui dunu gegesu ganodini medole legei, amo gilisili bogoi sogebi ganodini dialebe ba: sa.
31 “Farao, òun àti gbogbo jagunjagun rẹ̀ yóò rí wọn, a yóò sì tù ú nínú nítorí gbogbo ogun rẹ̀ tí a fi idà pa, ní Olúwa Olódùmarè wí.
Idibidi hina bagade amola ea dadi gagui dunu, da dunu huluane amo da gegesu ganodini medole legei, amo ba: beba: le, ilia dogo da denesimu,” Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: sa.
32 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti tan ẹ̀rù ká ilẹ̀ alààyè, Farao àti gbogbo ogun rẹ̀ ni a yóò tẹ́ sí àárín aláìkọlà, pẹ̀lú àwọn tí a fi idà pa ní Olúwa Olódùmarè wí.”
“Na da ea logo doasiba: le, Idibidi hina bagade ea hamobeba: le, esalebe dunu huluane da beda: gia: su. Be e amola ea dadi gagui dunu huluane da gadofo hame damui dunu gegesu ganodini medole legei, amoga gilisili, bogoi uli dogoi ganodini dialumu.” Ouligisudafa Hina Gode da sia: i dagoi.