< Ezekiel 29 >

1 Ní ọjọ́ kejìlá, oṣù kẹwàá, ọdún kẹwàá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Hagi Babilonima kinama ome hutama mani'nonkeno 10nima hiankafumofona 10ni ikantera 12fu knazupa Ra Anumzamo'a amanage huno nasami'ne.
2 “Ọmọ ènìyàn, kọjú sí Farao ọba Ejibiti kí ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí i àti sí gbogbo Ejibiti.
Vahe'mofo mofavrea Izikieliga, Isipi kini ne' Fero'ma nemania kaziga kavugosa hunte'nenka, agrane Isipi vahe'mo'zanema havizama hanaza zamofo kasnampa kea,
3 Sọ̀rọ̀, kí ó sì wí pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Èmi lòdì sí ọ, Farao ọba Ejibiti ìwọ ẹ̀mí búburú ńlá inú òkun tí ó dùbúlẹ̀ sí àárín àwọn odò ṣíṣàn rẹ. Èyí tí ó sọ wí pé, “Tèmi ni odò Naili; èmi ni ó sì ṣe é fún ara mi.”
amanage hunka huo, Ra Anumzana Agra Anumzamo'a amanage hie, Antahio, Isipi kini ne' Feroga kagra tusi'a osifave krerfa tinka'afina masenanku Nagra hara regantegahue. Hagi kagra hunka Naeli tina nagra tro hunte'noankino, nagri ti me'ne hunka hu'nane.
4 Ṣùgbọ́n èmi yóò fi ìwọ̀ mú ẹnu rẹ èmi yóò sì mú ẹja inú odò rẹ gbogbo lẹ̀ mọ́ ìpẹ́ ara rẹ. Èmi yóò fà ọ́ síta kúrò láàrín àwọn odò rẹ, àti gbogbo ẹja odò rẹ yóò lẹ̀ mọ́ ìpẹ́ ara rẹ.
Hianagi Nagra kagemazampafi hukua eri rusi hu'na, ana timpintira kavazuhu atresugeno ana timpima nemani'za nozamemo'za kaheheka'are akamarenesage'na ana maka zamavazu hu atitregahue.
5 Èmi yóò sọ ọ́ nù sí aginjù ìwọ àti gbogbo ẹja inú odò rẹ: ìwọ yóò ṣubú sí gbangba oko a kì yóò sì ṣà ọ́ jọ tàbí gbé ọ sókè. Èmi ti fi ọ ṣe oúnjẹ fún àwọn ẹranko igbó àti fún àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run láti jẹ.
Hagi kagri'ene mika nozameraminena tamavre'na hagege kokampi ome tamatregahue. Ana hanugeno vahe'mo'za ome zoraonkisageta afi zagagafane, namaramimofo ne'za segahaze.
6 Nígbà náà gbogbo àwọn olùgbé ni Ejibiti yóò mọ pé, Èmi ni Olúwa. “‘Ìwọ ti jẹ́ ọ̀pá ìyè fún ilé Israẹli.
E'ina hanuge'za Isipima mani'naza vahe'mo'za Nagrikura Ra Anumza mani'ne hu'za ke'za antahiza hugahaze. Na'ankure Israeli vahe'mo'za kagrikura hankave azompa mani'nampi hu'za hu'nazanagi, hake azotagna huno hankaveka'a omane'ne.
7 Nígbà tí wọn fi ọwọ́ agbára wọn dì ọ́ mú. Ìwọ fọ́, ìwọ sì ya gbogbo èjìká wọn; nígbà tí wọn fi ara tì ọ́, ìwọ sẹ́, ìwọ sì mú gbogbo ẹ̀gbẹ́ wọn gbọ̀n.
Israeli vahe'mo'za azompama hiaza hu'za kagrira zamazampi kazerine'za nevazagenka, kagra ru hantaginka zamazampi vazinka zamare'nane. Kagrite'ma zamagenama rentintima hazagenka zamaza osu zamatranke'za traka hu'za mase'naze.
8 “‘Nítorí náà, èyí ní Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi, Èmi yóò mú idà kan wá sórí rẹ tí yóò sì gé ènìyàn àti ẹran kúrò nínú rẹ.
E'ina hu'negu Ra Anumzamo'a amanage hie, Nagra mago ha' vahe zamavare'na esuge'za bainati kazinteti maka vahe'ene zagagafanena eme zamahe vagaresigeno,
9 Ilẹ̀ Ejibiti yóò di aginjù àti ahoro, nígbà náà ní wọn yóò sì mọ̀ wí pé èmi ní Olúwa. “‘Nítorí tí ìwọ wí pé, “Tèmi ni odò Naili, Èmi ni mo ṣe é,”
Isipi mopafina vahera omaninkeno haviza hugahie. E'ina hanuge'za Isipima mani'naza vahe'mo'za, Nagrikura Ra Anumza mani'ne hu'za ke'za antahi'za hugahaze. Na'ankure kagra hunka, Naeli tina nagra tro huntogeno nagri ti me'ne hunka hunaku,
10 nítorí náà, mo lòdì sí ọ àti sí àwọn odò rẹ, èmi yóò sì mú kí ilẹ̀ Ejibiti di píparun àti ahoro, pátápátá, láti Migdoli lọ dé Siene, dé ààlà ilẹ̀ Kuṣi.
Nagra menina kagri'ene tinka'anena ha' reranantena, Isipi mopa Migdoli kazigati agafa huteno vuno Aswani kaziga vuteno, vu vava huno Itiopia mopama eme atrete uhanatisige'na mika eri haviza hanenkeno, vahera omanitfa hugahie.
11 Kò sí ẹsẹ̀ ènìyàn tàbí tí ẹranko tí yóò gba ibẹ̀ kọjá; ẹni kankan kò ní gbé ibẹ̀ fún ogójì ọdún.
Hagi 40'a kafufina magore huno vahe'mo'zane zagagafamozanena ana mopafina vano vanoa osugahaze.
12 Èmi yóò sọ ilẹ̀ Ejibiti di ọ̀kan ní àárín àwọn ìlú tí ó di ahoro, fún ogójì ọdún, Èmi yóò sì fọ́n àwọn ara Ejibiti ká sáàárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò sì tú wọn ká sáàárín gbogbo ilẹ̀.
Hagi mago'a moparamima haviza hu'za me'naza amu'nompina, Isipi mopa eri havizantafa hanugeno rankumatmimo'za 40'a kafufina haviza hu'za megahaze. Ana nehu'na Isipi vahetamina zamahe panani hanuge'za, ru vahe mopafine vahe kumapinena mago mago hu'za umani emani hugahaze.
13 “‘Ṣùgbọ́n báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Ní òpin ogójì ọdún, èmi yóò ṣa àwọn ará Ejibiti jọ láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn níbi tí a fọ́n wọn ká sí.
Ana hugahazanagi Ra Anumzana Agra Anumzamo'a huno, Isipi vahetamima vahe kumategama umani emanima hu'nazana, 40'a kafuma agaterena, anantegatira ete zamavare atru hugahue.
14 Èmi yóò sì tún mú ìgbèkùn Ejibiti padà bọ̀, èmi yóò sì dá wọn padà sí ilẹ̀ Paturosi, ilẹ̀ àwọn baba ńlá wọn. Wọn yóò wà níbẹ̀ bí ìjọba tí a rẹ̀ sílẹ̀.
Ana nehu'na kinama ome hunaregatira ete zamavare'na mopa agafazmire Patrosi kumate esuge'za, zamagi omane vahe emanigahaze.
15 Ibẹ̀ yóò jẹ́ ìjọba tí ó rẹlẹ̀ jùlọ nínú àwọn ìjọba, kì yóò sì gbé ara rẹ̀ ga mọ́ sórí àwọn orílẹ̀-èdè: nítorí èmi ni ó dín wọn kù, tiwọn kì yóò fi ṣe olórí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù mọ́.
Ana huno himamu'a omane kuma me'neno kote'ma hu'neaza huno hihamua erino ruga'a kumapi vahera zamagate oregahie. Hagi hanavezmia eri atresugeno magore huno mago'a kumatamina kegava huozmantegahie.
16 Ejibiti kí yóò sì jẹ orísun ìgbẹ́kẹ̀lé fún ilé Israẹli mọ́ ṣùgbọ́n, yóò jẹ́ ìrántí fún àìṣedéédéé wọn, nígbà tí yóò bá wò wọ́n fún ìrànlọ́wọ́. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa Olódùmarè.’”
Israeli vahe'mo'za mago'enena tamagritegatira zamazama hu'zana eme e'origahaze. Na'ankure tamagri'ma eme tamantahige'za zamaza hu'zama eri'za kumi'ma hu'naza zanku zamagesa nentahiza anara hugahaze. E'ina nehu'za Nagrikura Ra Anumzana Agra Anumza mani'ne huza ke'za antahi'za hugahaze.
17 Ó sì ṣe ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní, ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Hagi Babilonima kinama ome hutama mani'nonkeno, 27nima hia kafumofona ese ikantera ese knazupa Ra Anumzamo'a amanage huno nasami'ne.
18 “Ọmọ ènìyàn, Nebukadnessari ọba Babeli mú kí ogun rẹ sin ìrú ńlá fún Tire. Gbogbo orí pá, àti gbogbo èjìká bó, síbẹ̀, òun àti àwọn ogun rẹ̀, kò rí owó ọ̀yà gbà láti Tire fún wa, fún ìrú ti a ti sìn.
Vahe'mofo mofavre Izikeliga, Babiloni kini ne' Nebukatnesa'a Tairi kumate vahe'enena tusi ha' nehuno sondia vahe'a ra eri'za zamige'za enerizageno zamanu zamazokamo'a pupunesegeno zamafumo'a pro hu'ne. Hianagi Tairi vahe'ma ha'ma huzmantazana mago knare mizana e'ori'naze.
19 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi i, Èmi yóò fi Ejibiti fún Nebukadnessari ọba Babeli, òun yóò sì kó ọrọ̀ rẹ̀ lọ. Òun yóò bo ilé, yóò sì ṣe ìkógun ilẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bí owó iṣẹ́ tí a san fún ológun rẹ̀.
E'ina hu'negu Ra Anumzana Agra Anumzamo'a amanage hie, antahiho, menina Nagra Isipi vahe mopa Babiloni kini ne' Nebukatnesa eri ami'nugeno, ana mopafima me'nea maka fenozana rohu'reno eri vagareno vugahie. E'i ana zama erisiana sondia vahe'mofo mi'za megahie.
20 Èmi ti fi Ejibiti fún un gẹ́gẹ́ bí èrè wàhálà rẹ̀ nítorí òun àti àwọn ológun rẹ ṣe é fún mi, ni Olúwa Olódùmarè wí.
Nagri kema amage'ma ante'za, sondia vahe'ane agranema amuhoma hu'za Tairi vahe'ma zamazeri havizama hu'naza zante mizazamigna hu'na Isipi mopa zamigahue huno Mikozama Kegavama Hu'nea Ra Anumzamo'a hu'ne.
21 “Ní ọjọ́ náà, èmi yóò mú kí ìwo Israẹli ru jáde, èmi yóò sì fún ọ ní ẹnu ọ̀rọ̀ ní àárín wọn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.”
Hagi ana knazupa Israeli vahera hihamu hankavea nezami'na, Izikieliga kagira eri aka hanena zamagri amu'nompi maninenka nanekea zamasamigahane. E'ina hanuge'za Nagrikura Ra Anumza mani'ne hu'za ke'za antahi'za hugahaze.

< Ezekiel 29 >