< Ezekiel 29 >

1 Ní ọjọ́ kejìlá, oṣù kẹwàá, ọdún kẹwàá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Na rĩrĩ, mwaka-inĩ wa ikũmi, mweri wa ikũmi, mũthenya wa ikũmi na ĩĩrĩ wa mweri wa ikũmi, kiugo kĩa Jehova nĩkĩanginyĩrĩire, ngĩĩrwo atĩrĩ:
2 “Ọmọ ènìyàn, kọjú sí Farao ọba Ejibiti kí ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí i àti sí gbogbo Ejibiti.
“Mũrũ wa mũndũ, erekeria ũthiũ waku kũrĩ Firaũni mũthamaki wa Misiri, ũmũũkĩrĩre, na ũmũrathĩre ũhoro wa kũmũũkĩrĩra na wa gũũkĩrĩra bũrũri wothe wa Misiri.
3 Sọ̀rọ̀, kí ó sì wí pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Èmi lòdì sí ọ, Farao ọba Ejibiti ìwọ ẹ̀mí búburú ńlá inú òkun tí ó dùbúlẹ̀ sí àárín àwọn odò ṣíṣàn rẹ. Èyí tí ó sọ wí pé, “Tèmi ni odò Naili; èmi ni ó sì ṣe é fún ara mi.”
Mwarĩrie ũmwĩre atĩrĩ, ‘Mwathani Jehova ekuuga ũũ: “‘Nĩngũgũũkĩrĩra, wee Firaũni mũthamaki wa Misiri, o wee nyamũ ĩno nene ũkomete tũrũũĩ-inĩ twaku. Uugaga atĩrĩ, “Nili nĩ rũũĩ rwakwa; nĩ niĩ ndarũthondekire nĩ ũndũ wakwa.”
4 Ṣùgbọ́n èmi yóò fi ìwọ̀ mú ẹnu rẹ èmi yóò sì mú ẹja inú odò rẹ gbogbo lẹ̀ mọ́ ìpẹ́ ara rẹ. Èmi yóò fà ọ́ síta kúrò láàrín àwọn odò rẹ, àti gbogbo ẹja odò rẹ yóò lẹ̀ mọ́ ìpẹ́ ara rẹ.
No nĩngagwĩkĩra ndwano thĩa-inĩ ciaku, na ndũme thamaki cia tũrũũĩ twaku ciĩgwatĩrĩre ngũcĩ-inĩ ciaku. Nĩngakũguucia ngũrute tũrũũĩ-inĩ twaku, hamwe na thamaki ciothe iria ciĩgwatĩrĩire ngũcĩ-inĩ ciaku.
5 Èmi yóò sọ ọ́ nù sí aginjù ìwọ àti gbogbo ẹja inú odò rẹ: ìwọ yóò ṣubú sí gbangba oko a kì yóò sì ṣà ọ́ jọ tàbí gbé ọ sókè. Èmi ti fi ọ ṣe oúnjẹ fún àwọn ẹranko igbó àti fún àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run láti jẹ.
Nĩngagũtiga werũ-inĩ, wee, hamwe na thamaki ciothe cia tũrũũĩ twaku. Nĩũkagũa kũu werũ-inĩ, na ndũkoererwo kana ũnganio. Ngaakũneana ũtuĩke irio cia nyamũ cia gĩthaka, na nyoni cia rĩera-inĩ.
6 Nígbà náà gbogbo àwọn olùgbé ni Ejibiti yóò mọ pé, Èmi ni Olúwa. “‘Ìwọ ti jẹ́ ọ̀pá ìyè fún ilé Israẹli.
Hĩndĩ ĩyo arĩa othe matũũraga bũrũri wa Misiri nĩmakamenya atĩ niĩ nĩ niĩ Jehova. “‘Wee ũkoretwo ũrĩ mũthĩgi wa kamũrangi wa gũtiira nyũmba ya Isiraeli.
7 Nígbà tí wọn fi ọwọ́ agbára wọn dì ọ́ mú. Ìwọ fọ́, ìwọ sì ya gbogbo èjìká wọn; nígbà tí wọn fi ara tì ọ́, ìwọ sẹ́, ìwọ sì mú gbogbo ẹ̀gbẹ́ wọn gbọ̀n.
Hĩndĩ ĩrĩa maakũnyiitire na moko mao-rĩ, nĩwatũkangire, na ũgĩtarũranga ciande ciao; hĩndĩ ĩrĩa meetiiranirie nawe-rĩ, nĩwoinĩkangire, nayo mĩgongo yao ĩkĩgonyoka.
8 “‘Nítorí náà, èyí ní Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi, Èmi yóò mú idà kan wá sórí rẹ tí yóò sì gé ènìyàn àti ẹran kúrò nínú rẹ.
“‘Nĩ ũndũ ũcio Mwathani Jehova ekuuga ũũ: Nĩngakũrehithĩria rũhiũ rwa njora rũgũũkĩrĩre na rũũrage andũ aku na mahiũ mao.
9 Ilẹ̀ Ejibiti yóò di aginjù àti ahoro, nígbà náà ní wọn yóò sì mọ̀ wí pé èmi ní Olúwa. “‘Nítorí tí ìwọ wí pé, “Tèmi ni odò Naili, Èmi ni mo ṣe é,”
Misiri gũgaatuĩka bũrũri mũtiganĩrie, ũgakira ihooru. Hĩndĩ ĩyo nĩmakamenya atĩ niĩ nĩ niĩ Jehova. “‘Tondũ wee woigire atĩrĩ, “Rũũĩ rwa Nili nĩ rwakwa; nĩ niĩ ndarũthondekire,”
10 nítorí náà, mo lòdì sí ọ àti sí àwọn odò rẹ, èmi yóò sì mú kí ilẹ̀ Ejibiti di píparun àti ahoro, pátápátá, láti Migdoli lọ dé Siene, dé ààlà ilẹ̀ Kuṣi.
nĩ ũndũ ũcio nĩngũgũũkĩrĩra na njũkĩrĩre tũrũũĩ twaku, na nĩngatũma bũrũri wa Misiri wanangĩke na ũkire ihooru, kuuma Migidoli nginya Aswani, o na nginya mũhaka-inĩ wa Kushi.
11 Kò sí ẹsẹ̀ ènìyàn tàbí tí ẹranko tí yóò gba ibẹ̀ kọjá; ẹni kankan kò ní gbé ibẹ̀ fún ogójì ọdún.
Gũtirĩ ikinya rĩa mũndũ kana rĩa nyamũ rĩgaatuĩkanĩria kuo; gũtirĩ mũndũ ũgaatũũra kuo ihinda rĩa mĩaka mĩrongo ĩna.
12 Èmi yóò sọ ilẹ̀ Ejibiti di ọ̀kan ní àárín àwọn ìlú tí ó di ahoro, fún ogójì ọdún, Èmi yóò sì fọ́n àwọn ara Ejibiti ká sáàárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò sì tú wọn ká sáàárín gbogbo ilẹ̀.
Nĩngatũma bũrũri wa Misiri ũkire ihooru gatagatĩ-inĩ ka mabũrũri marĩa manangĩku, na matũũra maguo manene matiganĩrio mĩaka mĩrongo ĩna gatagatĩ ka matũũra manene marĩa manangĩku. Na nĩngahurunjĩra andũ a Misiri ndũrĩrĩ-inĩ, na ndĩmaharaganĩrie mabũrũri-inĩ.
13 “‘Ṣùgbọ́n báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Ní òpin ogójì ọdún, èmi yóò ṣa àwọn ará Ejibiti jọ láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn níbi tí a fọ́n wọn ká sí.
“‘No rĩrĩ, Mwathani Jehova oigĩte atĩrĩ: Mĩaka mĩrongo ĩna yathira-rĩ, nĩngacookanĩrĩria andũ a Misiri moime ndũrĩrĩ-inĩ iria maahurunjirwo.
14 Èmi yóò sì tún mú ìgbèkùn Ejibiti padà bọ̀, èmi yóò sì dá wọn padà sí ilẹ̀ Paturosi, ilẹ̀ àwọn baba ńlá wọn. Wọn yóò wà níbẹ̀ bí ìjọba tí a rẹ̀ sílẹ̀.
Nao andũ arĩa maatahĩtwo a Misiri nĩngamacookia bũrũri wa Pathirosi, bũrũri ũrĩa wa maithe mao. Marĩ kũu magaatuĩka ũthamaki wĩnyiihĩtie.
15 Ibẹ̀ yóò jẹ́ ìjọba tí ó rẹlẹ̀ jùlọ nínú àwọn ìjọba, kì yóò sì gbé ara rẹ̀ ga mọ́ sórí àwọn orílẹ̀-èdè: nítorí èmi ni ó dín wọn kù, tiwọn kì yóò fi ṣe olórí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù mọ́.
Ũgaakorwo wĩnyiihĩtie gũkĩra mothamaki mothe, na ndũgacooka rĩngĩ gwĩtũũgĩria igũrũ rĩa ndũrĩrĩ iria ingĩ. Nĩ niĩ ngaawagithia hinya ũũ atĩ ndũrĩ hĩndĩ ĩngĩ ũgaatha ndũrĩrĩ.
16 Ejibiti kí yóò sì jẹ orísun ìgbẹ́kẹ̀lé fún ilé Israẹli mọ́ ṣùgbọ́n, yóò jẹ́ ìrántí fún àìṣedéédéé wọn, nígbà tí yóò bá wò wọ́n fún ìrànlọ́wọ́. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa Olódùmarè.’”
Bũrũri wa Misiri ndũgacooka gũtuĩka mwĩhoko wa andũ a Isiraeli, no ũgaatũĩka kĩririkania kĩa mehia mao ma gũcaria ũteithio kuo. Hĩndĩ ĩyo nĩmakamenya atĩ niĩ nĩ niĩ Mwathani Jehova.’”
17 Ó sì ṣe ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní, ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Mwaka-inĩ wa mĩrongo ĩĩrĩ na mũgwanja, mũthenya wa mbere wa mweri wa mbere, kiugo kĩa Jehova nĩkĩanginyĩrĩire, ngĩĩrwo atĩrĩ:
18 “Ọmọ ènìyàn, Nebukadnessari ọba Babeli mú kí ogun rẹ sin ìrú ńlá fún Tire. Gbogbo orí pá, àti gbogbo èjìká bó, síbẹ̀, òun àti àwọn ogun rẹ̀, kò rí owó ọ̀yà gbà láti Tire fún wa, fún ìrú ti a ti sìn.
“Mũrũ wa mũndũ, Nebukadinezaru, mũthamaki wa Babuloni, nĩatũmire mbũtũ ciake cia ita ciũkĩrĩre Turo na ihũũra inene; o mũtwe nĩwamunyirwo njuĩrĩ, na o kĩande gĩgĩcũnũrwo. No rĩrĩ, we mwene o na ita rĩake matiarĩhirwo kĩndũ nĩ ũndũ wa mbaara ĩyo aarũithirie ya gũũkĩrĩra Turo.
19 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi i, Èmi yóò fi Ejibiti fún Nebukadnessari ọba Babeli, òun yóò sì kó ọrọ̀ rẹ̀ lọ. Òun yóò bo ilé, yóò sì ṣe ìkógun ilẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bí owó iṣẹ́ tí a san fún ológun rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio Mwathani Jehova ekuuga ũũ: Nĩngũneana bũrũri wa Misiri harĩ Nebukadinezaru mũthamaki wa Babuloni, na nĩagakuua ũtonga wakuo. Agaatunyana na atahe indo cia bũrũri ũcio, ituĩke cia kũrĩha mbũtũ ciake cia ita.
20 Èmi ti fi Ejibiti fún un gẹ́gẹ́ bí èrè wàhálà rẹ̀ nítorí òun àti àwọn ológun rẹ ṣe é fún mi, ni Olúwa Olódùmarè wí.
Nĩndĩmũheete bũrũri wa Misiri ũtuĩke kĩheo gĩa kĩyo gĩake, tondũ we na mbũtũ ciake cia ita meekire ũguo nĩ ũndũ wakwa, ũguo nĩguo Mwathani Jehova ekuuga.
21 “Ní ọjọ́ náà, èmi yóò mú kí ìwo Israẹli ru jáde, èmi yóò sì fún ọ ní ẹnu ọ̀rọ̀ ní àárín wọn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.”
“Mũthenya ũcio, nĩngatũma nyũmba ya Isiraeli ĩmerie rũhĩa, na ndumũre kanua gaku thĩinĩ wao. Hĩndĩ ĩyo nĩmakamenya atĩ niĩ nĩ niĩ Jehova.”

< Ezekiel 29 >