< Ezekiel 28 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé:
Pǝrwǝrdigarning sɵzi manga kelip mundaⱪ deyildi: —
2 “Ọmọ ènìyàn, sọ fún ọmọ-aládé Tire pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Nítorí tí ọkàn rẹ gbé sókè sí mi, ìwọ wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run; Èmi jókòó sí orí ìtẹ́ òrìṣà, ní àárín gbùngbùn Òkun.” Ṣùgbọ́n ènìyàn ni ọ́, kì i ṣe òrìṣà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ìwọ rò pé ìwọ gbọ́n bí Ọlọ́run.
I insan oƣli, turning xaⱨzadisigǝ mundaⱪ degin: — Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — «Sening ɵzüngni qong tutup: «Mǝn bir ilaⱨturmǝn; Mǝn Hudaning tǝhtigǝ, yǝni dengiz-okyanlarning baƣrida olturimǝn», degǝnsǝn; (Biraⱪ sǝn insan, Huda ǝmǝssǝn!) Sǝn ɵz kɵnglüngni Hudaning kɵngli dǝp oylap ⱪalding.
3 Ìwọ gbọ́n ju Daniẹli lọ bí? Ṣé kò sí àṣírí kan tí ó pamọ́ fún ọ?
Mana, sǝn Daniyaldin danasǝn; Ⱨeqⱪandaⱪ sir sǝndin yoxurun ǝmǝs;
4 Pẹ̀lú ọgbọ́n àti ìmọ̀ rẹ, ìwọ tí jèrè ọrọ̀ fún ara rẹ, àti àkójọpọ̀ wúrà àti fàdákà, nínú àwọn ilé ìṣúra rẹ.
Danaliⱪing wǝ ǝⱪling bilǝn sǝn bayliⱪlarƣa igǝ boldung, Altun-kümüxni hǝziniliringgǝ toplap ⱪoydung;
5 Nípa ọgbọ́n rẹ ńlá àti nípa òwò rẹ, ìwọ ti sọ ọrọ̀ rẹ di púpọ̀, àti nítorí ọrọ̀ rẹ di púpọ̀, ọkàn rẹ gbé sókè, nítorí ọrọ̀ rẹ.
Tijarǝttǝ bolƣan zor danaliⱪing bilǝn bayliⱪliringni awuttung; Bayliⱪliring tüpǝylidin ɵzüngni qong tuttung: —
6 “‘Nítorí náà èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Nítorí pé ìwọ rò pé o gbọ́n, pé ìwọ gbọ́n bí Ọlọ́run.
Xunga Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — Sǝn ɵz kɵnglüngni Hudaning kɵngli dǝp oylap kǝtkǝnlikingdin,
7 Èmi yóò mú kí àwọn àjèjì dìde sí ọ, ẹlẹ́rù nínú àwọn orílẹ̀-èdè; wọn yóò yọ idà wọn sí ọ, ẹwà rẹ àti ọgbọ́n rẹ, wọn yóò sì ba dídán rẹ̀ jẹ́.
Əmdi mana, Mǝn yat adǝmlǝr, Yǝni ǝllǝrning dǝⱨxitini üstünggǝ epkelimǝn; Ular danaliⱪingning parlaⱪliⱪini yoⱪitixⱪa ⱪiliqlirini suƣurup, Xan-xǝripingni bulƣaydu;
8 Wọn yóò mú ọ sọ̀kalẹ̀ wá sínú ihò, ìwọ yóò sì kú ikú gbígbóná, àwọn tí a pa ní àárín Òkun.
Ular seni ⱨangƣa qüxüridu; Xuning bilǝn sǝn dengiz-okyanlarning ⱪoynida ɵltürülgǝnlǝrning ɵlümidǝ ɵlisǝn.
9 Ṣé ìwọ yóò wá wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run,” ní ojú àwọn tí ó pa ọ́? Ìwọ yóò jẹ́ ènìyàn, kì í ṣe Ọlọ́run, ní ọwọ́ àwọn ti yóò pa ọ́.
Əmdi seni ɵltürgüqining aldida: «Mǝn Huda» — dǝmsǝn? Biraⱪ sǝn ɵzüngni sanjip ɵltüridiƣanning ⱪoli astida Tǝngri ǝmǝs, insan bolup qiⱪisǝn.
10 Ìwọ yóò kú ikú aláìkọlà, ní ọwọ́ àwọn àjèjì. Èmi ni ó ti sọ ọ́, ní Olúwa Olódùmarè wí.’”
Sǝn yat adǝmlǝrning ⱪolida hǝtnǝ ⱪilinmiƣanlarƣa layiⱪ bolƣan ɵlüm bilǝn ɵlisǝn; Qünki Mǝn xundaⱪ sɵz ⱪilƣan», — dǝydu Rǝb Pǝrwǝrdigar.
11 Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé:
Pǝrwǝrdigarning sɵzi manga kelip mundaⱪ deyildi: —
12 “Ọmọ ènìyàn, pohùnréré ẹkún sórí ọba Tire kí ó sì sọ fún un pé: ‘Èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: “‘Ìwọ jẹ́ àpẹẹrẹ ìjẹ́pípé náà, o kún fún ọgbọ́n, o sì pé ní ẹwà.
I insan oƣli, Turning padixaⱨi toƣruluⱪ awazingni kɵtürüp bu mǝrsiyǝni aƣzingƣa elip uningƣa mundaⱪ degin: — Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — «Sǝn, kamalǝtning jǝwⱨiri bolƣan, Danaliⱪⱪa tolƣan, güzǝlliktǝ kamalǝtkǝ yǝtkǝniding;
13 Ìwọ ti wà ní Edeni, ọgbà Ọlọ́run; onírúurú òkúta oníyebíye ni ìbora rẹ; sardiu, topasi àti diamọndi, berili, óníkìsì, àti jasperi, safire, emeradi, turikuose, àti karbunkili, àti wúrà, ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ àti àwọn òkè rẹ ní a dà, láti ara wúrà, ní ọjọ́ tí á dá ọ ní a pèsè wọn.
Sǝn Erǝm baƣqisi, yǝni Hudaning baƣqisida bolƣansǝn; Ⱨǝrbir ⱪimmǝtlik taxlar, yǝni ⱪizil yaⱪut, seriⱪ gɵⱨǝr wǝ almas, beril yaⱪut, aⱪ ⱨeⱪiⱪ, anartax, kɵk yaⱪut, zumrǝt wǝ kɵk ⱪaxtax sanga yɵgǝk bolƣan; Yaⱪut kɵzliring wǝ nǝⱪⱪaxliring altun iqigǝ yasalƣan; Sǝn yaritilƣan kününgdǝ ular tǝyyarlanƣanidi.
14 A fi àmì òróró yàn ọ́ gẹ́gẹ́ bí olùtọ́jú kérúbù, torí èyí ni mo fi yàn ọ́. Ìwọ wà lórí òkè mímọ́ Ọlọ́run; ìwọ rìn ni àárín òkúta a mú bí iná.
Sǝn bolsang mǝsiⱨlǝngǝn muⱨapizǝtqi kerub idingsǝn, Qünki Mǝn seni xundaⱪ bekitkǝnidim; Sǝn Hudaning muⱪǝddǝs teƣida bolƣansǝn; Sǝn otluⱪ taxlar arisida yürǝtting;
15 Ìwọ pé ní ọ̀nà rẹ, láti ọjọ́ tí a ti dá ọ, títí a fi rí àìṣedéédéé ní inú rẹ.
Sǝn yaritilƣan kündin beri, sǝndǝ ⱪǝbiⱨlik pǝyda bolƣuqǝ, yolliringda mukǝmmǝl bolup kǝlgǝniding.
16 Nípa ìtànkálẹ̀ òwò rẹ, ìwọ kún fún ìwà ipá; ìwọ sì dẹ́ṣẹ̀. Nítorí náà ni mo ṣe sọ ọ nù, bí ohun àìlọ́wọ̀ kúrò lórí òkè Ọlọ́run. Èmi sì pa ọ run, ìwọ kérúbù, tí ó bọ́ kúrò ní àárín òkúta a mú bí iná.
Ⱪilƣan sodiliringning kɵp bolƣanliⱪidin sǝn zorluⱪ-zumbuluⱪ bilǝn tolup, gunaⱨ sadir ⱪilƣan; Xunga Mǝn seni Hudaning teƣidin ⱨaram nǝrsǝ dǝp taxliwǝtkǝnmǝn; Mǝn seni, i muⱨapizǝtqi kerub, otluⱪ taxlar arisidin ⱨǝydǝp yoⱪatⱪanmǝn;
17 Ọkàn rẹ gbéraga, nítorí ẹwà rẹ. Ìwọ sì ba ọgbọ́n rẹ jẹ́, nítorí dídára rẹ. Nítorí náà mo le ọ sórí ayé; mo sọ ọ di awòojú níwájú àwọn ọba.
Sening kɵnglüng güzǝlliking bilǝn tǝkǝbburlixip kǝtti; Parlaⱪliⱪing tüpǝylidin sǝn danaliⱪingni bulƣiƣansǝn; Mǝn seni yǝrgǝ taxliwǝttim; Padixaⱨlar seni kɵrüp yetixi üqün Mǝn seni ular aldida yatⱪuzdum.
18 Nípa ẹ̀ṣẹ̀ púpọ̀ rẹ àti òwò àìṣòótọ́ rẹ, ìwọ ti ba àwọn ibi mímọ́ rẹ jẹ́. Nítorí náà mo mú kí iná jáde wá, láti inú rẹ, yóò sì jó ọ run, èmi yóò sì sọ ọ́ di eérú lórí ilẹ̀, lójú gbogbo àwọn tí ó ń wò ọ́.
Sening ⱪǝbiⱨlikliringning kɵplüki tüpǝylidin, Ⱪilƣan sodangning adilsizliⱪi tüpǝylidin, Ɵz muⱪǝddǝs jayliringni bulƣiƣansǝn; Mǝn ɵzüngdin bir otni qiⱪardim, U seni kɵydürüp yǝwǝtti; Xuning bilǝn sanga ⱪarap turƣanlarning ⱨǝmmisining kɵz aldida, Mǝn seni yǝrdǝ ⱪalƣan küllǝrgǝ aylanduruwǝttim.
19 Gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó mọ̀ ọ́n, ní ẹnu ń yà sí ọ; ìwọ yóò sì jẹ́ ẹ̀rù, ìwọ kì yóò sì ṣí mọ́ láéláé.’”
Seni tonuƣanlarning ⱨǝmmisi sanga ⱪarap sarasimidǝ ⱪalidu; Sǝn ɵzüng bir wǝⱨxǝt bolup ⱪalding, ǝmdi ⱪaytidin bolmaysǝn».
20 Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé:
Pǝrwǝrdigarning sɵzi manga kelip mundaⱪ deyildi: —
21 “Ọmọ ènìyàn, kọ ojú sí Sidoni; kí o sì sọtẹ́lẹ̀ sí i,
I insan oƣli, yüzüngni Zidonƣa ⱪaritip uni ǝyiblǝp bexarǝt berip mundaⱪ degin: —
22 kí ó sì wí pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: “‘Èmi lòdì sí ọ, ìwọ Sidoni, a ó sì ṣe mí lógo láàrín rẹ. Wọn yóò mọ̀ pé èmi ní Olúwa, nígbà tí mo bá mú ìdájọ́ mi ṣẹ nínú rẹ, tí a sì yá mí sí mímọ́ nínú rẹ.
Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: — «Mana, Mǝn sanga ⱪarxi, i Zidon; Ɵzüm arangda uluƣlinimǝn; Mǝn uning üstigǝ ⱨɵküm qiⱪirip jazaliƣinimda, Ɵzümni uningda pak-muⱪǝddǝs ikǝnlimni kɵrsǝtkinimdǝ, Ular Mening Pǝrwǝrdigar ikǝnlikimni tonup yetidu.
23 Èmi yóò sì rán àjàkálẹ̀-ààrùn sínú rẹ, èmi yóò sì mú kí ẹ̀jẹ̀ sàn ní ìgboro rẹ, ẹni ti á pa yóò ṣubú ní àárín rẹ, pẹ̀lú idà lára rẹ ní gbogbo ẹ̀gbẹ́, nígbà náà wọn yóò mọ̀ wí pé èmi ni Olúwa.
Mǝn ularƣa wabani ǝwitip, rǝstǝ-koqilirida ⱪan aⱪⱪuzimǝn; Uningƣa ⱪarxi qiⱪⱪan ⱪiliqning ⱨǝr ǝtrapida bolƣanliⱪidin otturisida ɵltürülgǝnlǝr yiⱪilidu; Xuning bilǝn ular Mening Pǝrwǝrdigar ikǝnlikimni tonup yetidu;
24 “‘Kì yóò sì ṣí ẹ̀gún tí ń gun ni ní ilẹ̀ Israẹli mọ́, tàbí ẹ̀gún bíbani nínú jẹ́ ti gbogbo àwọn tí wọn wà ní àyíká wọn, tí wọ́n sì ń fi ojú yẹpẹrẹ wò wọ́n, nígbà náà ni wọn yóò mọ́ wí pé èmi ni Olúwa Olódùmarè.
Ular yǝnǝ Israil jǝmǝtini kɵzgǝ ilmiƣan ǝtrapidikilǝr arisida, Israil üqün adǝmni sanjiƣuqi jiƣan yaki dǝrd-ǝlǝmlik tikǝn bolmaydu; Xuning bilǝn ular Mening Rǝb Pǝrwǝrdigar ikǝnlikimni tonup yetidu».
25 “‘Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí èmi yóò bá sa àwọn ènìyàn Israẹli jọ kúrò ní gbogbo orílẹ̀-èdè tí wọ́n ti fọ́nká sí, tí a ó sì yà mí sí mímọ́ láàrín wọn lójú àwọn aláìkọlà. Nígbà náà ni wọn yóò gbé ní ilẹ̀ àwọn tìkálára wọn, èyí tí mo fún ìránṣẹ́ mi Jakọbu.
Rǝb Pǝrwǝrdigar mundaⱪ dǝydu: «Mǝn ular tarⱪitilƣan ǝllǝr arisidin Israil jǝmǝtini ⱪaytidin yiƣⱪinimda, ularda ǝllǝrning kɵz aldida Ɵzümning pak-muⱪǝddǝs ikǝnlikimni kɵrsǝtkinimdǝ, ǝmdi ular Mǝn Ɵz ⱪulum bolƣan Yaⱪupⱪa tǝⱪdim ⱪilƣan, ɵzining zeminida olturidu;
26 Wọn yóò sì máa gbé ní inú rẹ̀ ní àìléwu, wọn yóò sì kọ́lé, wọn yóò sì gbin ọgbà àjàrà; nítòótọ́ wọn yóò wà ní ìbàlẹ̀ àyà, nígbà tí èmi bá ti mú ìdájọ́ mi ṣẹ̀ sí ara àwọn tí ń ṣátá wọn ní gbogbo àyíká wọn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn.’”
ular uningda tinq-amanliⱪ iqidǝ yaxap, ɵylǝrni selip üzümzarlarni tikidu; Mǝn ularni kɵzgǝ ilmaydiƣan ǝtrapidikilǝrning ⱨǝmmisining üstigǝ ⱨɵküm qiⱪirip jazaliƣinimda, ular tinq-amanliⱪ iqidǝ turidu; xuning bilǝn ular Mening Pǝrwǝrdigar, ularning Hudasi ikǝnlikimni bilip yetidu».

< Ezekiel 28 >