< Ezekiel 28 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé:
HIKI mai la hoi ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
2 “Ọmọ ènìyàn, sọ fún ọmọ-aládé Tire pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Nítorí tí ọkàn rẹ gbé sókè sí mi, ìwọ wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run; Èmi jókòó sí orí ìtẹ́ òrìṣà, ní àárín gbùngbùn Òkun.” Ṣùgbọ́n ènìyàn ni ọ́, kì i ṣe òrìṣà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ìwọ rò pé ìwọ gbọ́n bí Ọlọ́run.
E ke keiki a ke kanaka, e olelo aku oe i ke alii o Turo, ke i mai nei Iehova ka Haku, penei; No ka mea, ua hookiekie kou naau, a ua olelo oe, He akua no wau, ke noho nei au ma kahi noho o ke Akua, iwaena o ke kai; he kanaka no nae oe, aole he akua, ina e hoonoho oe i kou naau me ka naau o ke Akua.
3 Ìwọ gbọ́n ju Daniẹli lọ bí? Ṣé kò sí àṣírí kan tí ó pamọ́ fún ọ?
Aia hoi, ua oi aku kou akamai mamua o ke akamai o Daniela; aole hiki ia lakou ke huna ia oe i kekahi mea huna.
4 Pẹ̀lú ọgbọ́n àti ìmọ̀ rẹ, ìwọ tí jèrè ọrọ̀ fún ara rẹ, àti àkójọpọ̀ wúrà àti fàdákà, nínú àwọn ilé ìṣúra rẹ.
Me kou akamai a me kou naauao, ua loaa ia oe ka waiwai nui, a ua loaa ia oe ke gula a me ke kala iloko o kou waiwai nui.
5 Nípa ọgbọ́n rẹ ńlá àti nípa òwò rẹ, ìwọ ti sọ ọrọ̀ rẹ di púpọ̀, àti nítorí ọrọ̀ rẹ di púpọ̀, ọkàn rẹ gbé sókè, nítorí ọrọ̀ rẹ.
Ma kou akamai nui, a ma kou kalepa ana ua hoonui oe i kou waiwai nui, a ua kiekie ae kou naau no ka nui o kou waiwai.
6 “‘Nítorí náà èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Nítorí pé ìwọ rò pé o gbọ́n, pé ìwọ gbọ́n bí Ọlọ́run.
Nolaila, ke i mai nei Iehova ka Haku, No kou hoonoho ana i kou naau e like me ka naau o ke Akua;
7 Èmi yóò mú kí àwọn àjèjì dìde sí ọ, ẹlẹ́rù nínú àwọn orílẹ̀-èdè; wọn yóò yọ idà wọn sí ọ, ẹwà rẹ àti ọgbọ́n rẹ, wọn yóò sì ba dídán rẹ̀ jẹ́.
Nolaila, ea, e lawe mai au i na malihini maluna ou, na mea weliweli o na lahuikanaka; a e unuhi ae lakou i ka lakou mau pahikaua e ku e i ka nani o kou akamai, a e hoohaumia lakou i kou alohilohi.
8 Wọn yóò mú ọ sọ̀kalẹ̀ wá sínú ihò, ìwọ yóò sì kú ikú gbígbóná, àwọn tí a pa ní àárín Òkun.
E lawe lakou ia oe ilalo i ka lua, a e make oe i ka make ana o ka poe i pepehiia iwaena o na kai.
9 Ṣé ìwọ yóò wá wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run,” ní ojú àwọn tí ó pa ọ́? Ìwọ yóò jẹ́ ènìyàn, kì í ṣe Ọlọ́run, ní ọwọ́ àwọn ti yóò pa ọ́.
E olelo anei oe imua o ka mea nana oe i pepehi, Owau no ke Akua? aka, he kanaka auanei oe aole he Akua, iloko o ka lima o ka mea nana oe i pepehi.
10 Ìwọ yóò kú ikú aláìkọlà, ní ọwọ́ àwọn àjèjì. Èmi ni ó ti sọ ọ́, ní Olúwa Olódùmarè wí.’”
E make auanei oe i ka make ana o ka poe okipoepoe ole ia ma ka lima o na malihini; no ka mea, na'u no i olelo, wahi a Iehova ka Haku.
11 Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé:
Hiki mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
12 “Ọmọ ènìyàn, pohùnréré ẹkún sórí ọba Tire kí ó sì sọ fún un pé: ‘Èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: “‘Ìwọ jẹ́ àpẹẹrẹ ìjẹ́pípé náà, o kún fún ọgbọ́n, o sì pé ní ẹwà.
E ke keiki a ke kanaka, e hoomaka oe i ke kanikau no ke alii o Turo, a e olelo aku ia ia, Ke i mai nei Iehova ka Haku, penei; He apo lima maikai loa oe, piha i ke akamai, a hemolele hoi i ka nani.
13 Ìwọ ti wà ní Edeni, ọgbà Ọlọ́run; onírúurú òkúta oníyebíye ni ìbora rẹ; sardiu, topasi àti diamọndi, berili, óníkìsì, àti jasperi, safire, emeradi, turikuose, àti karbunkili, àti wúrà, ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ àti àwọn òkè rẹ ní a dà, láti ara wúrà, ní ọjọ́ tí á dá ọ ní a pèsè wọn.
Maloko aku la oe i Edena ka mahinaai a ke Akua; o na pohaku maemae a pau oia ka mea uhi ia oe, o ka saredio, ke topasa, a me ke daimana, ka berila, ka onika, a me ka iasepa, ka sapeira, a me ka emerala, ka bareka, a me ke gula: o ka hana ana o kau mau pahu kani, a me kau mau mea hookiokio, ua hoomakaukauia ia iloko ou i kou la i hanau ai.
14 A fi àmì òróró yàn ọ́ gẹ́gẹ́ bí olùtọ́jú kérúbù, torí èyí ni mo fi yàn ọ́. Ìwọ wà lórí òkè mímọ́ Ọlọ́run; ìwọ rìn ni àárín òkúta a mú bí iná.
O oe no ke keruba e hohola ana a e uhi ana: ua hoonoho iho au ia oe maluna o ka mauna hoano o ke Akua; mawaenakonu hoi o na pohaku ahi i holoholo ai oe.
15 Ìwọ pé ní ọ̀nà rẹ, láti ọjọ́ tí a ti dá ọ, títí a fi rí àìṣedéédéé ní inú rẹ.
Ua hemolele no oe i kou mau aoao mai kou la i hanaia'i, a loaa ka hewa iloko ou.
16 Nípa ìtànkálẹ̀ òwò rẹ, ìwọ kún fún ìwà ipá; ìwọ sì dẹ́ṣẹ̀. Nítorí náà ni mo ṣe sọ ọ nù, bí ohun àìlọ́wọ̀ kúrò lórí òkè Ọlọ́run. Èmi sì pa ọ run, ìwọ kérúbù, tí ó bọ́ kúrò ní àárín òkúta a mú bí iná.
Ma ka nui loa o kou waiwai kalepa, ua hoopaapu lakou i ko waena ou me ka haunaele, a ua lawehala oe; nolaila, e hoolei aku au ia oe mo he mea haumia la mai ka mauna aku o ke Akua, a e luku aku au ia oe, e ke keruba e uhi ana mai waena aku o na pohaku ahi.
17 Ọkàn rẹ gbéraga, nítorí ẹwà rẹ. Ìwọ sì ba ọgbọ́n rẹ jẹ́, nítorí dídára rẹ. Nítorí náà mo le ọ sórí ayé; mo sọ ọ di awòojú níwájú àwọn ọba.
Ua hookiekie kou naau no kou nani, ua hoohaumia oe i kou akamai no kou alohilohi ana; e kiola iho au ia oe i ka lepo, e hoomoe aku au ia oe imua o na'lii e nana mai ai lakou ia oe.
18 Nípa ẹ̀ṣẹ̀ púpọ̀ rẹ àti òwò àìṣòótọ́ rẹ, ìwọ ti ba àwọn ibi mímọ́ rẹ jẹ́. Nítorí náà mo mú kí iná jáde wá, láti inú rẹ, yóò sì jó ọ run, èmi yóò sì sọ ọ́ di eérú lórí ilẹ̀, lójú gbogbo àwọn tí ó ń wò ọ́.
Ua hoohaumia oe i kou mau wahi hoano ma ka nui loa o kou mau hewa, ma ka hewa o kou kalepa ana; nolaila, e lawe mai au i ko ahi mai waenakonu ou, a e hoopau aku ia oe; a e hoolilo au ia oe i lehu ma ka honua imua o na maka o na mea a pau o ka poe e nana aku ia oe.
19 Gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó mọ̀ ọ́n, ní ẹnu ń yà sí ọ; ìwọ yóò sì jẹ́ ẹ̀rù, ìwọ kì yóò sì ṣí mọ́ láéláé.’”
O ka poe a pau i ike ia oe iwaena o na kanaka, e makau lakou nou; e lilo no oe i mea e weliweli ai; aole loa aku hoi oe.
20 Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé:
Hiki hou mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
21 “Ọmọ ènìyàn, kọ ojú sí Sidoni; kí o sì sọtẹ́lẹ̀ sí i,
E ke keiki a ke kanaka, e hooku i kou wahi maka e ku e ia Zidona, a e wanana ku e ia ia,
22 kí ó sì wí pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: “‘Èmi lòdì sí ọ, ìwọ Sidoni, a ó sì ṣe mí lógo láàrín rẹ. Wọn yóò mọ̀ pé èmi ní Olúwa, nígbà tí mo bá mú ìdájọ́ mi ṣẹ nínú rẹ, tí a sì yá mí sí mímọ́ nínú rẹ.
A e olelo aku, Ke i mai nei Iehova ka Haku, penei; Aia hoi, ke ku e nei au ia oe, e Zidona, a e hoonaniia mai au iwaenakonu ou; a e ike lakou, owau no Iehova, aia hoopai aku au maloko ona, a e hoanoia mai hoi iloko ona.
23 Èmi yóò sì rán àjàkálẹ̀-ààrùn sínú rẹ, èmi yóò sì mú kí ẹ̀jẹ̀ sàn ní ìgboro rẹ, ẹni ti á pa yóò ṣubú ní àárín rẹ, pẹ̀lú idà lára rẹ ní gbogbo ẹ̀gbẹ́, nígbà náà wọn yóò mọ̀ wí pé èmi ni Olúwa.
No ka mea, e hoouna'ku au i ka mai ahulau iloko ona, a me ke koko iloko o kona mau alanui; a e haule ka poe eha iwaenakonu ona i ka pahikaua maluna ona ma na aoao a puni; a e ike lakou, owau no Iehova.
24 “‘Kì yóò sì ṣí ẹ̀gún tí ń gun ni ní ilẹ̀ Israẹli mọ́, tàbí ẹ̀gún bíbani nínú jẹ́ ti gbogbo àwọn tí wọn wà ní àyíká wọn, tí wọ́n sì ń fi ojú yẹpẹrẹ wò wọ́n, nígbà náà ni wọn yóò mọ́ wí pé èmi ni Olúwa Olódùmarè.
Aole loa aku hoi ka mea ooi i ka ohana a Iseraela, aole hoi ke kakalaioa e kaumaha ai o ka poe a pau e hoopuni ana ia lakou, ka poe e hoowahawaha ia lakou; a e ike lakou owau no Iehova ka Haku.
25 “‘Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí èmi yóò bá sa àwọn ènìyàn Israẹli jọ kúrò ní gbogbo orílẹ̀-èdè tí wọ́n ti fọ́nká sí, tí a ó sì yà mí sí mímọ́ láàrín wọn lójú àwọn aláìkọlà. Nígbà náà ni wọn yóò gbé ní ilẹ̀ àwọn tìkálára wọn, èyí tí mo fún ìránṣẹ́ mi Jakọbu.
Ke i mai nei Iehova ka Haku, Aia pau ia'u ka ohana a Iseraela i ka hoouluuluia mai waena mai o ua lahuikanaka i hoopuehuiai lakou, a e hoanoia mai au ma o lakou la, imua o na maka o na lahuikanaka, aiaila e noho lakou ma ka aina a'u i haawi aku ai i kuu kauwa ia Iakoba.
26 Wọn yóò sì máa gbé ní inú rẹ̀ ní àìléwu, wọn yóò sì kọ́lé, wọn yóò sì gbin ọgbà àjàrà; nítòótọ́ wọn yóò wà ní ìbàlẹ̀ àyà, nígbà tí èmi bá ti mú ìdájọ́ mi ṣẹ̀ sí ara àwọn tí ń ṣátá wọn ní gbogbo àyíká wọn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn.’”
A e noho maluhia lakou malaila, a e kukulu lakou i na hale, a e kanu i na malawaina; oia, e noho lakou me ka makau ole, aia hoopai au i ka poe a pau i hoowahawaha ia lakou a puni; a e ike lakou owau no Iehova ko lakou Akua.

< Ezekiel 28 >