< Ezekiel 28 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé:
BOEIPA ol te kai taengah ha pawk tih,
2 “Ọmọ ènìyàn, sọ fún ọmọ-aládé Tire pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Nítorí tí ọkàn rẹ gbé sókè sí mi, ìwọ wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run; Èmi jókòó sí orí ìtẹ́ òrìṣà, ní àárín gbùngbùn Òkun.” Ṣùgbọ́n ènìyàn ni ọ́, kì i ṣe òrìṣà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé ìwọ rò pé ìwọ gbọ́n bí Ọlọ́run.
“Hlang capa aw, Ka Boeipa Yahovah loh a thui he Tyre rhaengsang taengah thui pah. Na lungbuei sang tih, ‘Kai la pathen, tuipuei tuilung kah pathen tolrhum ah ka ngol,’ na ti. Tedae nang hlang tangkik loh na lungbuei tah pathen lungbuei la na poek cakhaw na pathen moenih.
3 Ìwọ gbọ́n ju Daniẹli lọ bí? Ṣé kò sí àṣírí kan tí ó pamọ́ fún ọ?
Daniel lakah Daniel la na cueih ta te. A kael boeih khaw nang ham a hmuep moenih ko te.
4 Pẹ̀lú ọgbọ́n àti ìmọ̀ rẹ, ìwọ tí jèrè ọrọ̀ fún ara rẹ, àti àkójọpọ̀ wúrà àti fàdákà, nínú àwọn ilé ìṣúra rẹ.
Na cueihnah neh na lungcuei lamloh na thadueng la na saii. Na thakvoh khuiah sui neh cak na hen.
5 Nípa ọgbọ́n rẹ ńlá àti nípa òwò rẹ, ìwọ ti sọ ọrọ̀ rẹ di púpọ̀, àti nítorí ọrọ̀ rẹ di púpọ̀, ọkàn rẹ gbé sókè, nítorí ọrọ̀ rẹ.
Na hnothungnah dongah na cueihnah khaw puh tih na thadueng sai van. Tedae na thadueng dongah na thinko sang.
6 “‘Nítorí náà èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Nítorí pé ìwọ rò pé o gbọ́n, pé ìwọ gbọ́n bí Ọlọ́run.
Na thinko te pathen kah lungbuei bangla na ngai dongah ni ka Boeipa Yahovah loh he he a thui.
7 Èmi yóò mú kí àwọn àjèjì dìde sí ọ, ẹlẹ́rù nínú àwọn orílẹ̀-èdè; wọn yóò yọ idà wọn sí ọ, ẹwà rẹ àti ọgbọ́n rẹ, wọn yóò sì ba dídán rẹ̀ jẹ́.
Te dongah ni hlanghaeng neh namtom kholong te nang taengla kang khuen he. A cunghang neh na cueihnah sakthen te a khoh uh vetih na omyalnah khaw a poeih ni.
8 Wọn yóò mú ọ sọ̀kalẹ̀ wá sínú ihò, ìwọ yóò sì kú ikú gbígbóná, àwọn tí a pa ní àárín Òkun.
Vaam khuila nang n'suntlak sak uh vetih tuipuei tuilung ah rhok dongkah dueknah neh na duek ni.
9 Ṣé ìwọ yóò wá wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run,” ní ojú àwọn tí ó pa ọ́? Ìwọ yóò jẹ́ ènìyàn, kì í ṣe Ọlọ́run, ní ọwọ́ àwọn ti yóò pa ọ́.
Nang aka ngawn kah mikhmuh ah, ‘Kai la pathen,’ na ti khaw na ti aya? Nang adam ngawn tah namah aka poeih kut ah na pathen moenih.
10 Ìwọ yóò kú ikú aláìkọlà, ní ọwọ́ àwọn àjèjì. Èmi ni ó ti sọ ọ́, ní Olúwa Olódùmarè wí.’”
Kamah loh ka thui coeng dongah kholong kut ah ni pumdul kah dueknah neh na duek eh. He tah ka Boeipa Yahovah kah olphong ni,” a ti.
11 Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé:
BOEIPA ol te kai taengla ha pawk bal tih,
12 “Ọmọ ènìyàn, pohùnréré ẹkún sórí ọba Tire kí ó sì sọ fún un pé: ‘Èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: “‘Ìwọ jẹ́ àpẹẹrẹ ìjẹ́pípé náà, o kún fún ọgbọ́n, o sì pé ní ẹwà.
Hlang capa aw Tyre manghai ham rhahlung phueih pah lamtah amah te thui pah. Ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. Cueihnah khuengrhueng neh sakthen boeih kah cungkuemnah kutha aka daeng khaw nang ni.
13 Ìwọ ti wà ní Edeni, ọgbà Ọlọ́run; onírúurú òkúta oníyebíye ni ìbora rẹ; sardiu, topasi àti diamọndi, berili, óníkìsì, àti jasperi, safire, emeradi, turikuose, àti karbunkili, àti wúrà, ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ àti àwọn òkè rẹ ní a dà, láti ara wúrà, ní ọjọ́ tí á dá ọ ní a pèsè wọn.
Pathen kah dum Eden ah tah lung vang cungkuem te na thoeicamnah tih lungling vaya, lungmik, timsuih, oitha, maihae, minhum khocillung neh tamkuei, na kamrhing neh na rhotak toembael sui hnopai neh nang n'suen khohnin ah ni na khuiah a tawn uh.
14 A fi àmì òróró yàn ọ́ gẹ́gẹ́ bí olùtọ́jú kérúbù, torí èyí ni mo fi yàn ọ́. Ìwọ wà lórí òkè mímọ́ Ọlọ́run; ìwọ rìn ni àárín òkúta a mú bí iná.
Nang tah koelhnah aka thingthung cherubim ni. Te dongah ni Pathen kah cimcaihnah tlang ah nang kang khueh. Hmai lungto lakli ah khaw na om tih na pongpa coeng.
15 Ìwọ pé ní ọ̀nà rẹ, láti ọjọ́ tí a ti dá ọ, títí a fi rí àìṣedéédéé ní inú rẹ.
Nang kan suen khohnin lamloh na khuikah dumlai a phoe hil pataeng na longpuei ah na cuemthuek.
16 Nípa ìtànkálẹ̀ òwò rẹ, ìwọ kún fún ìwà ipá; ìwọ sì dẹ́ṣẹ̀. Nítorí náà ni mo ṣe sọ ọ nù, bí ohun àìlọ́wọ̀ kúrò lórí òkè Ọlọ́run. Èmi sì pa ọ run, ìwọ kérúbù, tí ó bọ́ kúrò ní àárín òkúta a mú bí iná.
Na hnothungnah kah a puhnah lamloh na kotak te kuthlahnah hah tih na tholh. Te dongah ni Pathen kah tlang lamloh nang kam poeih tih hmai lungto lakli lamkah aka thingthung cherubim taeng lamloh nang kam milh sak.
17 Ọkàn rẹ gbéraga, nítorí ẹwà rẹ. Ìwọ sì ba ọgbọ́n rẹ jẹ́, nítorí dídára rẹ. Nítorí náà mo le ọ sórí ayé; mo sọ ọ di awòojú níwájú àwọn ọba.
Na sakthen dongah na lungbuei khaw sang tih na cueihnah neh na poci. Na omyalnah dongah ni diklai la manghai rhoek kah mikhmuh ah nang kam voeih tih nang te sawt sak ham nang kang khueh.
18 Nípa ẹ̀ṣẹ̀ púpọ̀ rẹ àti òwò àìṣòótọ́ rẹ, ìwọ ti ba àwọn ibi mímọ́ rẹ jẹ́. Nítorí náà mo mú kí iná jáde wá, láti inú rẹ, yóò sì jó ọ run, èmi yóò sì sọ ọ́ di eérú lórí ilẹ̀, lójú gbogbo àwọn tí ó ń wò ọ́.
Na hnothungnah dumlai dongah namah kah thaesainah tah khawk tih na rhokso ni na poeih coeng. Te dongah ni na khui lamloh hmai ka puek sak tih nang n'hlawp. Te vaengah nang aka so boeih kah mikhmuh ah nang te diklai hmaiphu la kang khueh.
19 Gbogbo orílẹ̀-èdè tí ó mọ̀ ọ́n, ní ẹnu ń yà sí ọ; ìwọ yóò sì jẹ́ ẹ̀rù, ìwọ kì yóò sì ṣí mọ́ láéláé.’”
Pilnam khuikah nang aka ming boeih loh nang soah hal uh coeng. Mueirhih la na poeh tanglang tih kumhal duela na phoe pawh,” a ti.
20 Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé:
BOEIPA ol te kai taengla ha pawk bal tih,
21 “Ọmọ ènìyàn, kọ ojú sí Sidoni; kí o sì sọtẹ́lẹ̀ sí i,
“Hlang capa aw Sidon te na maelhmai khueh thil lamtah tonghma thil laeh.
22 kí ó sì wí pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: “‘Èmi lòdì sí ọ, ìwọ Sidoni, a ó sì ṣe mí lógo láàrín rẹ. Wọn yóò mọ̀ pé èmi ní Olúwa, nígbà tí mo bá mú ìdájọ́ mi ṣẹ nínú rẹ, tí a sì yá mí sí mímọ́ nínú rẹ.
Te vaengah ka Boeipa Yahovah loh a thui he thui pah. Kai loh Sidon nang kam pai thil coeng ne. Na kotak khuiah ka thangpom uh vetih BOEIPA kamah tila m'ming uh bitni. Tholhphu te anih soah ka saii vetih a khuiah ka ciim uh bitni.
23 Èmi yóò sì rán àjàkálẹ̀-ààrùn sínú rẹ, èmi yóò sì mú kí ẹ̀jẹ̀ sàn ní ìgboro rẹ, ẹni ti á pa yóò ṣubú ní àárín rẹ, pẹ̀lú idà lára rẹ ní gbogbo ẹ̀gbẹ́, nígbà náà wọn yóò mọ̀ wí pé èmi ni Olúwa.
A khuikah duektahaw neh a kawtpoeng ah thii ka tueih vaengah a kaepvai kah cunghang neh a kholung ah a rhok la cungku ni. Te vaengah BOEIPA kamah te m'ming uh bitni.
24 “‘Kì yóò sì ṣí ẹ̀gún tí ń gun ni ní ilẹ̀ Israẹli mọ́, tàbí ẹ̀gún bíbani nínú jẹ́ ti gbogbo àwọn tí wọn wà ní àyíká wọn, tí wọ́n sì ń fi ojú yẹpẹrẹ wò wọ́n, nígbà náà ni wọn yóò mọ́ wí pé èmi ni Olúwa Olódùmarè.
Te vaengah Israel imkhui ham tangti kah a huet neh hling kah a do khaw om voel mahpawh. A kaepvai boeih lamkah amih aka hnaep long khaw kai he ka Boeipa Yahovah ni tila a ming uh bitni.
25 “‘Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí èmi yóò bá sa àwọn ènìyàn Israẹli jọ kúrò ní gbogbo orílẹ̀-èdè tí wọ́n ti fọ́nká sí, tí a ó sì yà mí sí mímọ́ láàrín wọn lójú àwọn aláìkọlà. Nígbà náà ni wọn yóò gbé ní ilẹ̀ àwọn tìkálára wọn, èyí tí mo fún ìránṣẹ́ mi Jakọbu.
Ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. Israel imkhui te pilnam lamloh ka coi. Amih taengla taekyak uh cakhaw namtom mikhmuh kah amih taengah ka ciim coeng. Te dongah a khohmuen ah kho a sak uh ni. Te te ka sal Jakob taengah ka paek coeng.
26 Wọn yóò sì máa gbé ní inú rẹ̀ ní àìléwu, wọn yóò sì kọ́lé, wọn yóò sì gbin ọgbà àjàrà; nítòótọ́ wọn yóò wà ní ìbàlẹ̀ àyà, nígbà tí èmi bá ti mú ìdájọ́ mi ṣẹ̀ sí ara àwọn tí ń ṣátá wọn ní gbogbo àyíká wọn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn.’”
A khuiah ngaikhuek la hing uh vetih im a sak uh ni. Misur a phung uh vetih ngaikhuek la hing uh ni. A kaepvai lamkah amih aka hnaep boeih soah tholhphu ka suk vaengah kai he BOEIPA a Pathen la a ming uh bitni.

< Ezekiel 28 >