< Ezekiel 26 >

1 Ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kọ́kànlá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
EIA kekahi, i ka makahiki umikumamakahi, i ka la mua o ia malama, hiki mai ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
2 “Ọmọ ènìyàn, nítorí pé Tire sọ nípa Jerusalẹmu pé, ‘Háà! A fọ́ èyí tí í ṣe bodè àwọn orílẹ̀-èdè, a yí i padà sí mi, èmi yóò di kíkún, òun yóò sì di ahoro,’
E ke keiki a ke kanaka, no ka olelo ku e ana o Turo ia Ierusalema, Aia la, ua nahaha oia, ka mea i noho he mau puka no na kanaka; ua huli mai ia ia'u; e hoolakoia au, ua hooneoneoia ia:
3 nítorí náà, báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí, kíyèsi i, èmí dojúkọ ọ́ ìwọ tire, Èmi yóò sì jẹ́ kí Orílẹ̀-èdè púpọ̀ dìde sí ọ, gẹ́gẹ́ bí Òkun tí ru sókè.
Nolaila, ke olelo nei Iehova ka Haku, Eia hoi, e ku e au ia oe, e Turo, a e kono au i na lahuikanaka he nui e pii ku e ia oe, e like me ke kai e hoopii ai i kona mau ale.
4 Wọn yóò wó odi tire lulẹ̀, wọn yóò sì wo ilé ìṣọ́ rẹ̀ lulẹ̀, Èmi yóò sì ha erùpẹ̀ rẹ̀ kúrò, Èmi yóò sì sọ ọ́ di orí àpáta.
A e wawahi lakou i na pa o Turo, a e hoohiolo i kona mau halekiai: a e kope hoi au i kona lepo mai ona aku, a e hoolilo au ia ia e like me ka pohaku olohelohe.
5 Yóò sì jẹ́ ibi nína àwọ̀n tí wọn fi ń pẹja sí láàrín Òkun, ní Olúwa Olódùmarè wí. Yóò di ìkógun fún àwọn orílẹ̀-èdè.
E lilo ia i wahi e hohola ai i na upena, iwaenakonu o ke kai, no ka mea, na'u no ia i olelo, wahi a Iehova, a e lilo ia i waiwai pio no ko na aina.
6 Ìlú tí ó tẹ̀dó sí, ní àárín gbùngbùn ilẹ̀ rẹ̀ ni a ó fi idà sọ ọ́ di ahoro. Nígbà náà ní wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
A o kona mau kaikamahine, na mea ma ka aina, e pepehiia lakou i ka pahikaua; a e ike lakou owau no Iehova.
7 “Nítorí báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi i, láti ìhà àríwá ni èmi yóò ti mú Nebukadnessari ọba Babeli, ọba àwọn ọba, dìde sí Tire pẹ̀lú ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ ogun pẹ̀lú àwọn ẹlẹ́ṣin àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ológun.
No ka mea, ke olelo mai nei o Iehova ka Haku, penei; Eia hoi, e alakai ana au ia Nebukaneza, ke alii o Babulona, ke alii o na'lii, e ku e ia Turo, mai ke kukulu akau mai, me na lio, a me na kaa, a me na hoohololio, a me na anaina, a me na kanaka he nui wale.
8 Yóò sì fi idà sá àwọn ọmọbìnrin rẹ ní oko, yóò sì kọ́ odi tì ọ́, yóò sì mọ òkìtì tì ọ́, yóò sì gbé àpáta sókè sí ọ.
E pepehi oia me ka pahikaua i kou mau kaikamahine ma ka aina; a e hana oia i ka halekaua ku e ia oe, a e hana hoi oia i puu ku e ia oe, a kaikai i ka palekaua ku e ia oe.
9 Yóò sì gbé ẹ̀rọ ogun tí odi rẹ, yóò sì fi ohun èlò ogun wó ilé ìṣọ́ rẹ palẹ̀.
A e hoonoho ku e oia i na mea kaua i kou mau pa, a e wawahi i kou mau halekiai me kona mau koi.
10 Àwọn ẹṣin rẹ̀ yóò pọ̀ dé bí pé wọn yóò fi eruku bò ọ́ mọ́lẹ̀. Àwọn ògiri rẹ yóò mì tìtì fún igbe àwọn ẹṣin ogun kẹ̀kẹ́ ẹrù àti kẹ̀kẹ́ ogun nígbà tí ó bá wọ ẹnu-ọ̀nà odi gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí ń wọ ìlú láti inú àwọn ògiri rẹ̀ ti ó di fífọ́ pátápátá.
No ka nui o kona mau lio, e uhi mai ko lakou lepo maluna ou; i ke kamumu ana o na hoohololio, a me na huila, a me na kaa, e haalulu ai kou mau pa, i kona komo ana'e iloko o kou mau ipuka, e like me ke komo ana o na kanaka i ke kulanakauhale i wahiia.
11 Pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin rẹ̀ ni yóò fi tẹ gbogbo òpópónà rẹ mọ́lẹ̀; yóò fi idà pa àwọn ènìyàn rẹ, àwọn ọ̀wọ́n rẹ ti o lágbára yóò wó palẹ̀.
Me na maiuu o kona mau lio e hahi oia i kou mau alanui a pau, a e luku oia i kou poe kanaka me ka pahikaua, a e haule iho na kia o kou ikaika ilalo i ka lepo.
12 Wọn yóò kó ọrọ̀ rẹ, wọn yóò sì fi òwò rẹ ṣe ìjẹ ogun; wọn yóò sì wó odi rẹ lulẹ̀, wọn yóò sì ba àwọn ilé rẹ dídára jẹ́, wọn yóò sì kó àwọn òkúta rẹ̀, àti igi ìtì ìkọ́lé rẹ̀, àti erùpẹ̀ rẹ̀, dà sí inú Òkun.
A e hao aku lakou i kou waiwai nui, a e kaili aku hoi i kou waiwai kalepa; a e wawahi iho lakou i kou mau pa ilalo, a e hookai hoi i kou mau hale makemakeia; a e waiho iho lakou i kou laau, a me kou mau pohaku, a me kou lepo iwaena konu o ka wai.
13 Èmi yóò sì mú ariwo orin rẹ̀ dákẹ́ àti ìró dùùrù orin rẹ̀ ni a kì yóò gbọ́ mọ́.
A e hooki au i ka leo o kau mau mele; aole hoi e lohe hou ia ke kani ana o kou mau kinora.
14 Èmi yóò sọ ọ di àpáta lásán, ìwọ yóò sì di ibi tí a ń sá àwọ̀n ẹja sí. A kì yóò sì tún ọ mọ nítorí Èmi Olúwa ti sọ ọ̀rọ̀ ní Olúwa Olódùmarè wí.
A e hoolilo au ia oe e like me ka pohaku olohelohe; e lilo oe i wahi e hohola ai i ua upena, aole e kukulu hou ia'ku oe; no ka mea, na'u na Iehova i olelo, wahi a Iehova ka Haku.
15 “Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí sí Tire: Ǹjẹ́ àwọn erékùṣù kì yóò ha wárìrì nípa ìṣubú rẹ, nígbà tí ìkórìíra ìpalára àti rírẹ́ni lọ́run bá ń ṣẹlẹ̀ ní inú rẹ?
Ke i mai nei Iehova ka Haku, penei, ia Turo, Aole anei e haalulu na mokupuni i ke halulu ana o kou hiolo ana, i ka wa e auwe ai ka poe eha, a he lukuia hoi iwaenakonu ou.
16 Nígbà náà ni gbogbo àwọn ọmọ-aládé etí Òkun yóò sọ̀kalẹ̀ láti orí ìtẹ́ wọn, wọn yóò sì pa àwọn aṣọ ìgúnwà wọn da, tì wọn yóò sì bọ́ àwọn aṣọ iṣẹ́ ọnà abẹ́rẹ́ kúrò. Ẹ̀rù yóò bò wọ́n, wọn yóò sì jókòó lórí ilẹ̀ pẹ̀pẹ̀, wọn yóò sì máa wárìrì ní gbogbo ìgbà, ẹnu yóò sì yà wọ́n sí ọ́.
Alaila, e iho iho na'lii a pau o ke kai mai luna mai o ko lakou mau nohoalii, a e waiho ae i ko lakou aahu alii, a e wehe ae i ko lakou mau kapa onionio: e aahu lakou i ka haalulu, e noho iho lakou ma ka honua, a e weliweli i kela minute, keia minute, a e pilihua ia oe.
17 Nígbà náà wọn yóò gbóhùn ẹkún sókè nítorí rẹ, wọn yóò sì wí fún ọ pé: “‘Báwo ni a ṣe pa ọ́ run, ìwọ ìlú olókìkí ìwọ tí àwọn èrò okun ti gbé inú rẹ̀! Ìwọ jẹ alágbára lórí okun gbogbo òun àti àwọn olùgbé inú rẹ̀; ìwọ gbé ẹ̀rù rẹ lórí gbogbo olùgbé ibẹ̀.
A e hoomaka lakou i ke kanikau nou, a e olelo aku ia oe, Ua luku e ia oe, e ka mea i nohoia e na holokai, ke kulanakauhale kaulana i paa maloko o ke kai, oia a me kona poe noho, na mea i hana e weliweli ai ka poe a pau i noho ilaila!
18 Nísinsin yìí erékùṣù wárìrì ní ọjọ́ ìṣubú rẹ; erékùṣù tí ó wà nínú Òkun ni ẹ̀rù bà torí ìṣubú rẹ.’
Ano hoi e haalulu na mokupuni i kou la e hiolo ai; oia, e weliweli na moku iloko o ke kai i kou lilo ana aku.
19 “Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí mo bá sọ ọ́ di ìlú ahoro, gẹ́gẹ́ bi àwọn ìlú tí a kò gbé inú wọn mọ́, àti nígbà tí èmi yóò mú ibú agbami Òkun wá sí orí rẹ, omi ńlá yóò sì bò ọ́,
No ka mea, ke i inai nei Iehova ka Haku, penei; Aia hoolilo au ia oe i neoneo, e like me na kulanakauhale i noho ole ia, i ko'u hoopii ana'e i ka hohonu maluna ou, a e uhi ae na wai nui maluna ou;
20 nígbà tí èmi yóò mú ọ wálẹ̀ pẹ̀lú àwọn tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ihò, pẹ̀lú àwọn ènìyàn àtijọ́. Èmi yóò sì gbé ọ lọ si bi ìsàlẹ̀, ní ibi ahoro àtijọ́, pẹ̀lú àwọn tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ihò, ìwọ kì yóò sì padà gbé inú rẹ̀ mọ́, èmi yóò sì gbé ògo kalẹ̀ ní ilẹ̀ àwọn alààyè.
I ko'u hooiho ana ia oe ilalo me ka poe e iho i ka lua, me na kanaka o ka wa kahiko, a e hoonoho ia oe ma kahi haahaa o ka honua, ma na wahi neoneo kahiko no, me ka poe i iho ilalo i ka lua, i ole oe e nohoia; a e hoonoho aku au i ka nani ma ka aina o ka poe e ola ana.
21 Èmi yóò ṣe ọ ní ẹ̀rù, ìwọ kì yóò sì ṣí mọ́. Bí a tilẹ̀ wá ọ, síbẹ̀ a kì yóò tún rí ọ mọ́, ní Olúwa Olódùmarè wí.”
E hoolilo au ia oe i mea e weliweli ai, a, e ole aku no oe: a ina e imiia'ku oe, aole loa oe e loaa hou, a mau loa aku, wahi a Iehova ka Haku.

< Ezekiel 26 >