< Ezekiel 26 >

1 Ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kọ́kànlá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
A kum hlaibun, thapa yung pasuek, hnin pasuek dawkvah, hettelah doeh, BAWIPA e lawk kai koe a pha. Tami capa Taire ni Jerusalem taranlahoi haha! miphunnaw e takhang lah kaawm e a rawk toe khe, kai koe lah a kamlang teh, koung raphoe lah ao vaiteh, kai kama law teh, a cak han telah ati.
2 “Ọmọ ènìyàn, nítorí pé Tire sọ nípa Jerusalẹmu pé, ‘Háà! A fọ́ èyí tí í ṣe bodè àwọn orílẹ̀-èdè, a yí i padà sí mi, èmi yóò di kíkún, òun yóò sì di ahoro,’
Tami capa Taire ni Jerusalem taranlahoi haha! miphunnaw e takhang lah kaawm e a rawk toe khe, kai koe lah a kamlang teh, koung raphoe lah ao vaiteh, kai kama law teh, a cak han telah ati.
3 nítorí náà, báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí, kíyèsi i, èmí dojúkọ ọ́ ìwọ tire, Èmi yóò sì jẹ́ kí Orílẹ̀-èdè púpọ̀ dìde sí ọ, gẹ́gẹ́ bí Òkun tí ru sókè.
Hatdawkvah, Bawipa Jehovah ni telah a dei, khenhaw! Oe Taire, kai ni na taran, talî ni tuicapa a thaw sak e patetlah nang nama taranlahoi miphun moikapap nang koe ka tho sak han.
4 Wọn yóò wó odi tire lulẹ̀, wọn yóò sì wo ilé ìṣọ́ rẹ̀ lulẹ̀, Èmi yóò sì ha erùpẹ̀ rẹ̀ kúrò, Èmi yóò sì sọ ọ́ di orí àpáta.
Taire rapan hah a raphoe awh vaiteh, imrasangnaw hah a raphoe awh han. Ama koehoi vaiphu hah kathoungcalah ka hui pou vaiteh, ka ke e lungsong lah ka coung sak han.
5 Yóò sì jẹ́ ibi nína àwọ̀n tí wọn fi ń pẹja sí láàrín Òkun, ní Olúwa Olódùmarè wí. Yóò di ìkógun fún àwọn orílẹ̀-èdè.
Talî lungui e tamlawk yangda rumram nahanelah ao han, bangkongtetpawiteh, kai ni ka dei toe, telah Bawipa Jehovah ni a dei, hottelah miphunnaw hanelah lawphno lah ao awh han.
6 Ìlú tí ó tẹ̀dó sí, ní àárín gbùngbùn ilẹ̀ rẹ̀ ni a ó fi idà sọ ọ́ di ahoro. Nígbà náà ní wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
Kahrawngum kaawm e a canu hah tahloi hoi thei e lah ao han, hat toteh, BAWIPA lah ka o tie a panue awh han.
7 “Nítorí báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi i, láti ìhà àríwá ni èmi yóò ti mú Nebukadnessari ọba Babeli, ọba àwọn ọba, dìde sí Tire pẹ̀lú ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ ogun pẹ̀lú àwọn ẹlẹ́ṣin àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ológun.
Bangkongtetpawiteh, Bawipa Jehovah ni hettelah a dei, khenhaw! Taire taranlahoi Babilon siangpahrang Nebukhadnezar, siangpahrangnaw e siangpahrang teh atunglae ram lahoi marang hoi marangransanaw hoi tami moikapap hoi ka thokhai han.
8 Yóò sì fi idà sá àwọn ọmọbìnrin rẹ ní oko, yóò sì kọ́ odi tì ọ́, yóò sì mọ òkìtì tì ọ́, yóò sì gbé àpáta sókè sí ọ.
Na canu hah kahrawngum vah tahloi hoi a thei awh han. Nang na rungngang nahanelah rapan hah a sak awh vaiteh, nang na tuk nahanelah ravo a sak awh vaiteh, ahnimouh taranlahoi bahlingnaw a sin awh han.
9 Yóò sì gbé ẹ̀rọ ogun tí odi rẹ, yóò sì fi ohun èlò ogun wó ilé ìṣọ́ rẹ palẹ̀.
Nang e rapannaw avanglah takhang a raphoe nahanelah a sak awh vaiteh, cakâ hoi imrasang hah a raphoe awh han.
10 Àwọn ẹṣin rẹ̀ yóò pọ̀ dé bí pé wọn yóò fi eruku bò ọ́ mọ́lẹ̀. Àwọn ògiri rẹ yóò mì tìtì fún igbe àwọn ẹṣin ogun kẹ̀kẹ́ ẹrù àti kẹ̀kẹ́ ogun nígbà tí ó bá wọ ẹnu-ọ̀nà odi gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí ń wọ ìlú láti inú àwọn ògiri rẹ̀ ti ó di fífọ́ pátápátá.
Kapappoung e marang kecu dawk, vaiphu hoi muen ramuk e lah ao han, raphoe e khopui dawkvah, tami ouk a kâen e patetlah na takhang dawk a kâen awh han, na takhang dawk a kâen awh navah, marangransanaw e pawlawk hoi tarantuknae leng pawlawk dawk rapan rasang hah a kâhuet han.
11 Pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin rẹ̀ ni yóò fi tẹ gbogbo òpópónà rẹ mọ́lẹ̀; yóò fi idà pa àwọn ènìyàn rẹ, àwọn ọ̀wọ́n rẹ ti o lágbára yóò wó palẹ̀.
Na lamthungnaw hah marang khoksamen hoi be a katin awh vaiteh, na taminaw hah tahloi hoi a thei awh han. Ka rasang e na rapan hah talai dawk be a rawp awh han.
12 Wọn yóò kó ọrọ̀ rẹ, wọn yóò sì fi òwò rẹ ṣe ìjẹ ogun; wọn yóò sì wó odi rẹ lulẹ̀, wọn yóò sì ba àwọn ilé rẹ dídára jẹ́, wọn yóò sì kó àwọn òkúta rẹ̀, àti igi ìtì ìkọ́lé rẹ̀, àti erùpẹ̀ rẹ̀, dà sí inú Òkun.
Na tawntanae hah lawphno lah koung a la awh han, na hnopai pueng be a rawk han, na rapan hah a tip vaiteh, kahawipoung e na im hah a raphoe awh han, na thing, na talung hoi na talai kahawinaw hah tui dawk be a tâkhawng awh han.
13 Èmi yóò sì mú ariwo orin rẹ̀ dákẹ́ àti ìró dùùrù orin rẹ̀ ni a kì yóò gbọ́ mọ́.
La na sak pawlawk hah ka roum sak vaiteh, na ratoung pawlawk thai e lah awm mahoeh toe.
14 Èmi yóò sọ ọ di àpáta lásán, ìwọ yóò sì di ibi tí a ń sá àwọ̀n ẹja sí. A kì yóò sì tún ọ mọ nítorí Èmi Olúwa ti sọ ọ̀rọ̀ ní Olúwa Olódùmarè wí.
Ka ke e lungsong lah ka coung sak han, tamlawk yangda hanelah ka coung sak vaiteh, na kangdout sak mahoeh toe. Bangkongtetpawiteh, kai BAWIPA ni ka dei toe telah Bawipa Jehovah ni a dei.
15 “Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí sí Tire: Ǹjẹ́ àwọn erékùṣù kì yóò ha wárìrì nípa ìṣubú rẹ, nígbà tí ìkórìíra ìpalára àti rírẹ́ni lọ́run bá ń ṣẹlẹ̀ ní inú rẹ?
Bawipa Jehovah ni Taire koevah, hettelah a dei, nangmouh koevah kâtheinae ao. A hmâ ka cat e a hram toteh, na rawpnae a pawlawk dawk ramlouknaw hah a kâhuen mahoeh namaw.
16 Nígbà náà ni gbogbo àwọn ọmọ-aládé etí Òkun yóò sọ̀kalẹ̀ láti orí ìtẹ́ wọn, wọn yóò sì pa àwọn aṣọ ìgúnwà wọn da, tì wọn yóò sì bọ́ àwọn aṣọ iṣẹ́ ọnà abẹ́rẹ́ kúrò. Ẹ̀rù yóò bò wọ́n, wọn yóò sì jókòó lórí ilẹ̀ pẹ̀pẹ̀, wọn yóò sì máa wárìrì ní gbogbo ìgbà, ẹnu yóò sì yà wọ́n sí ọ́.
Talî dawk e kahrawikungnaw pueng ni a tungkhung dawk hoi a kum awh han, ka sungren poung e a hnicunaw hah a hruek awh vaiteh, a kamthoupnae be a rading awh han. Pâyawnae hah kamthoup awh vaiteh, talai dawk tahung laihoi pou a pâyaw awh han, kângairupoung awh han.
17 Nígbà náà wọn yóò gbóhùn ẹkún sókè nítorí rẹ, wọn yóò sì wí fún ọ pé: “‘Báwo ni a ṣe pa ọ́ run, ìwọ ìlú olókìkí ìwọ tí àwọn èrò okun ti gbé inú rẹ̀! Ìwọ jẹ alágbára lórí okun gbogbo òun àti àwọn olùgbé inú rẹ̀; ìwọ gbé ẹ̀rù rẹ lórí gbogbo olùgbé ibẹ̀.
Nang khuinae la a phueng awh vaiteh, nang koevah, talai van e a tha ka sai e khopui a min kamthang, tuikathoumnaw khosaknae hah ama hoi a thung kho ka sak pueng, ka cet kaawm e naw ni a bari e khocanaw hoi kakuep e kho, nang teh na rawknae a pataw poung.
18 Nísinsin yìí erékùṣù wárìrì ní ọjọ́ ìṣubú rẹ; erékùṣù tí ó wà nínú Òkun ni ẹ̀rù bà torí ìṣubú rẹ.’
Na rawpnae ni tuilum pueng koung a kâhuet sak, na kahma hnin vah, talîpui teng e ramnaw be yawng awh han, ati awh han telah ati.
19 “Èyí yìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí mo bá sọ ọ́ di ìlú ahoro, gẹ́gẹ́ bi àwọn ìlú tí a kò gbé inú wọn mọ́, àti nígbà tí èmi yóò mú ibú agbami Òkun wá sí orí rẹ, omi ńlá yóò sì bò ọ́,
Bangkongtetpawiteh, Bawipa Jehovah ni hettelah a dei, tami a ohoehnae khopui ka rawk e kingdi e khopui lah na coung sak toteh, kadungpoung e tui dawk na bo sak vaiteh, tui moikapap ni na ramuk han.
20 nígbà tí èmi yóò mú ọ wálẹ̀ pẹ̀lú àwọn tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ihò, pẹ̀lú àwọn ènìyàn àtijọ́. Èmi yóò sì gbé ọ lọ si bi ìsàlẹ̀, ní ibi ahoro àtijọ́, pẹ̀lú àwọn tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ihò, ìwọ kì yóò sì padà gbé inú rẹ̀ mọ́, èmi yóò sì gbé ògo kalẹ̀ ní ilẹ̀ àwọn alààyè.
Ayan e tami kadungpoung e tangkom dawk ka cet tangcoung e koevah, na ceisak awh han, talai thung vah, ayan hoi kingdi e kadungpoung e tangkom thung ka cet tangcoung e koevah, kho na sak han, apihai nangmouh thung vah kho a sak hoeh nahan hoi, taminaw koehoi bawilennae hah na hmu hoeh nahanelah,
21 Èmi yóò ṣe ọ ní ẹ̀rù, ìwọ kì yóò sì ṣí mọ́. Bí a tilẹ̀ wá ọ, síbẹ̀ a kì yóò tún rí ọ mọ́, ní Olúwa Olódùmarè wí.”
He na pâmit han, na awm mahoeh toe, tami ni na ka tawng nakunghai, na hmawt awh mahoeh toe telah Bawipa Jehovah ni ati.

< Ezekiel 26 >