< Ezekiel 25 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Ra Anumzamo'a amanage huno nasami'ne,
2 “Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ sí àwọn ará Ammoni kí ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí wọn.
Vahe'mofo mofavre Izikeliga, Amoni vahe moparega kavugosa hunte'nenka, Amoni vahe'mo'zama havizama hanaza kasnampa kea huzmanto.
3 Sì wí fún àwọn ará Ammoni pé, ‘Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè tí ó wí pé. Nítorí tí ìwọ wí pé, “Á hà!” Sí ibi mímọ́ mi nígbà tí ó di àìlọ́wọ̀ àti sí orí ilẹ̀ Israẹli nígbà tí ó di ahoro; àti sí ilẹ̀ Juda, nígbà tí wọ́n lọ sí ìgbèkùn,
Amanage hunka Amoni vahera zamasamio, Mikozama Kegavama Hu'nea Ra Anumzamofo kea antahiho, Ra Anumzana Agra Anumzamo'a amanage hie, Na'ankure kagra amanage hunka puhaha kagerura ru'nane, ra mono nona haviza higeno, Israeli mopamo'a haviza higeno, Juda vahera kina huzmante'za zamavare'za vu'naze hunka hu'nane.
4 kíyèsi i, nítorí náà ni èmi yóò fi fi ọ lé àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn lọ́wọ́ ni ohun ìní. Wọn yóò sì gbé ààfin wọn kalẹ̀ nínú rẹ, wọn yóò sì gbé ibùgbé wọn nínú rẹ, wọn yóò jẹ èso rẹ, wọn yóò sì mu wàrà rẹ.
E'ina hu'negu tamagrira tamavre'na zage hanati kaziga vahe zamisuge'za, tamavre'za kegava huramantegahaze. Ana nehu'za amu'nontamifi seli nonkumara eme kiza manine'za, zafa aragatimia tagiza nene'za, bulimakao afutamimofo amirina tati'za negahaze.
5 Èmi yóò sì sọ Rabba di ibùjẹ, fún àwọn ìbákasẹ àti àwọn ọmọ Ammoni di ibùsùn fún agbo ẹran. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
Hagi Raba rankumara kemori afutamimo'zama traza nesaza mopa eri fore nehu'na, Amoni kumara sipisipi afu'mokizmi kuma erifore hugahue. E'ina hanugeta Nagrikura Ra Anumza mani'ne huta keta antahita hugahaze.
6 Nítorí báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí. Nítorí pé ìwọ pàtẹ́wọ́, ìwọ sì jan ẹsẹ̀ mọ́lẹ̀, tí ìwọ ń yọ̀ pẹ̀lú gbogbo àrankàn rẹ sí ilẹ̀ Israẹli
Hagi Mikozama Kegavama Hu'nea Ra Anumzamo'a amanage hie, Israeli vahe'mo'zama knazampima unefrazageta tamazana neheta, haruhuta marerita tamita nehuta, vahe'nimo'zama havizama nehazageta musena hu'naze.
7 nítorí náà, èmi yóò na ọwọ́ mi lé ọ, èmi yóò sì fi ọ fún àwọn aláìkọlà fún ìkógun. Èmi yóò sì gé ọ kúrò láàrín àwọn ènìyàn, èmi yóò sì jẹ́ kí o parun kúrò ni ilẹ̀ gbogbo. Èmi yóò sì pa ọ́ run, ìwọ yóò sì mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’”
E'ina hu'nagu Nagra nazana rusute'na hara reneramante'na, rohu'ma tamaresaza vahe'mokizmi zamazampi tamavre anta'nena tamazeri haviza hugahaze. Ana nehu'na tamahe vagara'nena ana mopafintira fanane hugahaze. Anama hanugeta Nagrikura Ra Anumza mani'ne huta keta antahita hugahaze.
8 “Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí pé Moabu àti Seiri sọ wí pé, “Wò ó, ilé Juda ti dàbí gbogbo àwọn kèfèrí,”
Miko'zama kegavama hu'nea Ra Anumzamo'a amanage hie, Moapu ne, Seiri vahemo'zanena zamagrama antahi'zana Juda vahe'mo'za ruzahura osu'nazanki, ruga'a mopafi vahe kna hu'naze hu'za nehaze.
9 nítorí náà, Èmi yóò ṣí Moabu sílẹ̀ láti àwọn ìlú gbogbo tí ó wà ní ààlà rẹ̀, ògo ilẹ̀ náà, Beti-Jeṣimoti, Baali-Meoni àti Kiriataimu.
E'ina hu'negu ha' vahe'tami huzmante'nuge'za Moapu vahe'mokizimi mopa atumparegati agafa hu'za rankumazmia Bet-Jesimotima, Ba'al-Meonima, Kiriataimi kuma'zmia zamahe'za hanaregahaze.
10 Èmi yóò fi Moabu pẹ̀lú àwọn ará Ammoni lé àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn ní ìní, kí a má bà á lè rántí àwọn ará Ammoni láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo.
Hagi Nagra Moapu vahe'ma hu'noaza hu'na Amoni vahera zage fre kaziga vahe'mokizmi zamazampi zamavare anta'nena, ana vahe'mokizmiza sesageno ruga'a mopafi vahe'mo'za zamagesa antahi nozmisage'na,
11 Èmi yóò sì mú ìdájọ́ sẹ sí Moabu lára, wọn yóò sì mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’”
Nagra Moapu vahera keaga huzmante'na knazana zamigahue. E'ina hanuge'za Nagrikura Ra Anumza mani'ne hu'za ke'za antahi'za hugahaze.
12 “Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí pé: ‘Nítorí pé Edomu gbẹ̀san lára ilé Juda, ó sì jẹ̀bi gidigidi nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀,
Hagi Mikozama kegavama hu'nea Ra Anumzamo'a amanage hie, Na'ankure Idomu vahe'mo'zama Juda vahe'ma nona hu'za ha'ma huzmante'naza zamo'a, ra hazenke eri fore hu'naze.
13 nítorí náà báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí pé: Èmi yóò na ọwọ́ mi sórí Edomu èmi yóò sì pa àwọn ènìyàn àti àwọn ẹranko rẹ̀. Èmi yóò fi ṣófo láti Temani dé Dedani yóò ti ipa idà ṣubú.
E'ina hu'nagu Mikozama Kegavama Hu'nea Ra Anumzamo'a amanage hie, Nagra nazana rusute'na Idomu vahe'ene zagagafazminena zamahe fri hana hugahue. Ana hu'na Temani kumateti'ma erigafa huno Detani kumate'ma uhanati'nea kumazmia eri haviza nehu'na, mika vahera bainati kazinteti zamahe vagarenugeno vahera omanitfa hugahie.
14 Èmi yóò gbẹ̀san lára Edomu láti ọwọ́ àwọn ènìyàn mi Israẹli, wọn sì ṣe sí Edomu gẹ́gẹ́ bí ìbínú àti ìrunú mi, wọn yóò mọ̀ ìgbẹ̀san mi ní Olúwa Olódùmarè wí.’”
Hagi Israeli vaheni'a huzmantesuge'za nona hu'za Idomu vahera zamahegahaze. Nagri narimpa ahe'zamo'ma hu'nenia avamente ante'za zamazeri haviza nehu'za, zamahesage'za Nagri narimpahe'zana ke'za antahi'za hugahaze huno Miko'zama Kegavama Hu'nea Ra Anumzamo'a hu'ne.
15 “Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí pé: ‘Nítorí tí àwọn ará Filistini hùwà ẹ̀san tí wọ́n sì gbẹ̀san pẹ̀lú odì ní ọkàn wọn, àti pẹ̀lú ìkórìíra gbangba àtijọ́ ní wíwá ọ̀nà láti pa Juda run,
Hagi Ra Anumzana Agra Anumzamo'a amanage hie, Filistia vahe'mo'za Israeli vahekura tusi zamavaresra hunezmante'za, hara huzmante vava hu'za neaze.
16 nítorí náà báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí pé, “Èmi ti ṣetán láti na ọwọ́ mi jáde sí àwọn ará Filistini, èmi yóò sì ké àwọn ará Kereti kúrò, èmi yóò sì pa àwọn tí ó kù ní etí kún run.
E'ina hu'nazagu Mikozama Kegavama hu'nea Ra Anumzamo'a amanage hie, Nagra nazana rusute'na Filistia vahera hara hunezmante'na, Kereti vahetamine, ra hagerimofo anke'regama mani'naza vahetaminena zamahe hana hugahue.
17 Èmi yóò sì gbẹ̀san ńlá lára wọn nípa ìbáwí gbígbóná; wọn yóò sì mọ̀ wí pé, Èmi ni Olúwa. Nígbà tí èmi yóò gba ẹ̀san lára wọn.”’”
Hagi kefo avu'ava'ma hu'nazarera, Nagra tusi narimpa ahezmante'na nona hu'na zamazeri haviza hanuge'za Nagrikura Ra Anumza mani'ne hu'za ke'za antahi'za hugahaze.

< Ezekiel 25 >